< John 11 >
1 Ara ọkùnrin kan kò sì dá, Lasaru, ará Betani, tí í ṣe ìlú Maria àti Marta arábìnrin rẹ̀.
Bedani moilai dunu afae ea dio amo La: salase, da oloi dialu. Bedani moilaiga Meli amola ea aba Mada da esalu.
2 Maria náà ni ẹni tí ó fi òróró ìkunra kun Olúwa, tí ó sì fi irun orí rẹ̀ nù ún, arákùnrin rẹ̀ ni Lasaru í ṣe, ara ẹni tí kò dá.
(Meli da gabusiga: manoma Yesu Ea emo amoga sogadigili, ea dialuma hinaboga doga: i. Ea ola La: salase da oloi dialu.)
3 Nítorí náà, àwọn arábìnrin rẹ̀ ránṣẹ́ sí i, wí pé, “Olúwa, wò ó, ara ẹni tí ìwọ fẹ́ràn kò dá.”
Amo a: fini aduna da Yesuma sia: si, “Hina! Dia dogolegei na: iyado da oloi diala.”
4 Nígbà tí Jesu sì gbọ́, ó wí pé, “Àìsàn yìí kì í ṣe sí ikú, ṣùgbọ́n fún ògo Ọlọ́run, kí a lè yin Ọmọ Ọlọ́run lógo nípasẹ̀ rẹ̀.”
Amo sia: nababeba: le, Yesu E amane sia: i, “Amo oloi da La: salase dafawane bogoma: ne hame misi. Be dunu huluane Gode Ea hadigi ida: iwane ba: ma: ne, amola Gode Egefe hadigi lama: ne, amo oloi da mui dagoi.”
5 Jesu sì fẹ́ràn Marta, àti arábìnrin rẹ̀ àti Lasaru.
Yesu da Mada, Meli amola La: salase, ilima bagadewane asigisu.
6 Nítorí náà, nígbà tí ó ti gbọ́ pé, ara rẹ̀ kò dá, ó gbé ọjọ́ méjì sí i níbìkan náà tí ó gbé wà.
Be La: salase da oloi dialu nababeba: le, E da hedolo mae asili, eso aduna eno ouesalu
7 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí ni ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí a tún padà lọ sí Judea.”
Amalalu, E da Ea ado ba: su dunuma amane sia: i, “Ninia Yudia sogega ahoa: di!”
8 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wí fún un pé, “Rabbi, ní àìpẹ́ yìí ni àwọn Júù ń wá ọ̀nà láti sọ ọ́ ní òkúta; ìwọ sì tún padà lọ síbẹ̀?”
Yesu Ea ado ba: su dunu ilia da bu adole i, “Olelesu! Eso enoga, gasidawane, Yudia soge dunu da Di igiga medole legemusa: dawa: i galu. Di da abuliba: le buhagimusa: dawa: bela: ?”
9 Jesu dáhùn pé, “Wákàtí méjìlá kọ́ ni ó bẹ nínú ọ̀sán kan bí? Bí ẹnìkan bá rìn ní ọ̀sán, kì yóò kọsẹ̀, nítorí tí ó rí ìmọ́lẹ̀ ayé yìí.
Yesu E amane sia: i, “Esoga da hawa: hamomusa: gini hadigi diala. Nowa da esomogoa ahoasea, e da osobo bagade hadigi amo ganodini ahoabeba: le, hame sadenane dafasa.
10 Ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá rìn ní òru, yóò kọsẹ̀, nítorí tí kò sí ìmọ́lẹ̀ nínú rẹ̀.”
Be e da gasimogoa ahoasea, hadigi hameba: le, hedolowane sadenane dafasa.”
11 Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ, lẹ́yìn èyí nì ó sì wí fún wọn pé, “Lasaru ọ̀rẹ́ wa sùn; ṣùgbọ́n èmi ń lọ kí èmi kí ó lè jí i dìde nínú orun rẹ̀.”
Amo sia: dagoloba, Yesu E bu sia: i “Ninia na: iyado La: salase, e da golai dialebe ba: i. Be Na da e didilisimusa: masunu.”
12 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olúwa, bí ó bá ṣe pé ó sùn, yóò sàn.”
Yesu Ea ado ba: su dunu da bu adole i, “E da midi fawane dialebeba: le hedolo uhimu.”
13 Ṣùgbọ́n Jesu ń sọ ti ikú rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n rò pé, ó ń sọ ti orun sísùn.
La: salase da bogoidafa, Yesu da sia: musa: dawa: i. Be ilia dawa: loba, Yesu da La: salase golai fawane sia: i.
14 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn gbangba pé, “Lasaru ti kú.
Amaiba: le, Yesu da moloiwane olelei, “La: salase da bogoidafa.
15 Èmi sì yọ̀ nítorí yín, tí èmi kò sí níbẹ̀. Kí ẹ le gbàgbọ́; ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí a lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.”
Be dilia da Na hou dafawaneyale dawa: ma: ne, Na da La: salase ea bogoi sogebi amoga e fidima: ne hame esalebeba: le, Na da hahawane gala. Ninia da e ba: la ahoa: di!”
16 Nítorí náà Tomasi, ẹni tí à ń pè ní Didimu, wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí àwa náà lọ, kí a lè bá a kú pẹ̀lú.”
Domase (amo dawa: loma: ne da mano aduna ame afae, eso afae amoga lalelegei) e da eno ado ba: su dunuma amane sia: i, “Defea! Ninia huluane gilisili bogoma: ne, Olelesu sigi masunu da defea.”
17 Nítorí náà nígbà tí Jesu dé, ó rí i pé a ti tẹ́ ẹ sínú ibojì ní ọjọ́ mẹ́rin ná,
Yesu da Bedani moilaiga doaga: beba: le, La: salase da eso biyadu agoane bogoi uli dagoi ganodini dialebe, amo E da nabi dagoi.
18 ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Bedani da Yelusaleme moilai bai bagade amoga sedade defei da1 gilomida dialu.
19 Ọ̀pọ̀ nínú àwọn Júù sì wá sọ́dọ̀ Marta àti Maria láti tù wọ́n nínú nítorí ti arákùnrin wọn.
Yudia dunu bagohame, Mada amola Meli ela ola bogoiba: le, ela fidimusa: misi esalu.
20 Nítorí náà, nígbà tí Marta gbọ́ pé Jesu ń bọ̀ wá, ó jáde lọ pàdé rẹ̀, ṣùgbọ́n Maria jókòó nínú ilé.
Yesu Ea misi nababeba: le, Mada da logoga E yosia: musa: asi. Be Meli da diasuga esalu.
21 Nígbà náà, ni Marta wí fún Jesu pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.
Mada da Yesuma amane sia: i, “Hina! Di guiguda: esala ganiaba, naola da hame bogola: loba.
22 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí náà, mo mọ̀ pé, ohunkóhun tí ìwọ bá béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run yóò fi fún ọ.”
Be na dawa: ! Di da Godema adole ba: sea, E da Dia hanai liligi Dima imunu.”
23 Jesu wí fún un pé, “Arákùnrin rẹ yóò jíǹde.”
Yesu bu adole i, “Diola da uhini bu wa: legadomu.”
24 Marta wí fún un pé, “Mo mọ̀ pé yóò jíǹde ní àjíǹde ìkẹyìn.”
Mada amane sia: i, “Na dawa: ! Soge wadela: mu esoha, dunu huluane da wa: legadomu.”
25 Jesu wí fún un pé, “Èmi ni àjíǹde àti ìyè, ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, bí ó tilẹ̀ kú, yóò yè.
Yesu E amane sia: i, “Na da Wa: legadosudafa. Na da Fifi Ahoanusudafa. Nowa da bogoiwane dialebe be Na sia: dafawaneyale dawa: sea, e da bu esalumu.
26 Ẹnikẹ́ni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì gbà mí gbọ́, kì yóò kú láéláé ìwọ gbà èyí gbọ́?” (aiōn )
Nowa esala dunu da Na sia: dafawaneyale dawa: sea, e da mae bogole esalalalumu. Amo sia: di dafawaneyale dawa: bela: ?” (aiōn )
27 Ó wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Olúwa, èmi gbàgbọ́ pé, ìwọ ni Kristi náà Ọmọ Ọlọ́run, ẹni tí ń bọ̀ wá sí ayé.”
Mada da bu adole i, “Ma! Hina! Di da Mesaia, Gode Egefedafa amo da osobo bagadega misunu galu.”
28 Nígbà tí ó sì ti wí èyí tan, ó lọ, ó sì pe Maria arábìnrin rẹ̀ sẹ́yìn wí pé, “Olùkọ́ dé, ó sì ń pè ọ́.”
Amo sia: nanu, Mada buhagili, ea eya Melima wamowane sia: i, “Olelesu da doaga: i dagoi. E da Di Ema misa: ne sia: sa!”
29 Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Amo sia: nababeba: le, Meli da hedolowane wa: legadole, asili, Yesu yosia: musa: asi.
30 Jesu kò tí ì wọ ìlú, ṣùgbọ́n ó wà ní ibi kan náà tí Marta ti pàdé rẹ̀.
(Yesu da moilaidafa amoga hame doaga: i. E da Mada ea Ema yosia: i sogebi amogai esalu.)
31 Nígbà tí àwọn Júù tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú ilé, tí wọ́n ń tù ú nínú rí Maria tí ó dìde kánkán, tí ó sì jáde, wọ́n tẹ̀lé, wọ́n ṣe bí ó ń lọ sí ibojì láti sọkún níbẹ̀.
Meli da hedolowane wa: legadole, asili ba: loba, ea fidisu na: iyado da e da bogoi uli dogoi amoga dimusa: masunu dawa: i galu. Amaiba: le, ilia da ema fa: no bobogei.
32 Nígbà tí Maria sì dé ibi tí Jesu wà, tí ó sì rí i, ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó wí fún un pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.”
Yesu E esalu sogebi doaga: loba, Meli da Ea emo gadenene diasa: ili, amane sia: i, “Hina! Di da guiguda: esala ganiaba, naola da hame bogola: loba.”
33 Nígbà tí Jesu rí i, tí ó ń sọkún, àti àwọn Júù tí ó bá a wá ń sọkún pẹ̀lú rẹ̀, ó kérora nínú ẹ̀mí, inú rẹ̀ sì bàjẹ́.
Meli da dinanebe, amola ea fidisu dunu huluane ilia dinanebe, amo ba: loba, Yesu Ea dogo ganodini dimusa: dawa: i galu.
34 Ó sì wí pé, “Níbo ni ẹ̀yin gbé tẹ́ ẹ sí?” Wọ́n sì wí fún un pé, “Olúwa, wá wò ó.”
E da ilima amane sia: i, “Dilia ea da: i hodo habi uli dogone salila: ?” Ilia bu adole i, “Hina! Ba: la misa.”
36 Nítorí náà àwọn Júù wí pé, “Sá wò ó bí ó ti fẹ́ràn rẹ̀ tó!”
Dunu huluane da amane sia: i, “Ba: ma! E da ema bagade asigisa!”
37 Àwọn kan nínú wọn sì wí pé, “Ọkùnrin yìí, ẹni tí ó la ojú afọ́jú, kò lè ṣe é kí ọkùnrin yìí má kú bí?”
Be eno dunu da amane sia: i, “E da si dofoi dunu bu ba: ma: ne, ea si hahamoi. Ebeda! E da gui esala ganiaba, E da La: salase ea bogomu logo hedofala: lobala: ?”
38 Nígbà náà ni Jesu tún kérora nínú ara rẹ̀, ó wá sí ibojì, ó sì jẹ́ ihò, a sì gbé òkúta lé ẹnu rẹ̀.
Yesu da ea dogo ganodini se nabawane, La: salase ea uli dogoi amoga doaga: i. Amo da gele gelabo, ea logo holei igi bagadega bebesole ga: si.
39 Jesu wí pé, “Ẹ gbé òkúta náà kúrò!” Marta, arábìnrin ẹni tí ó kú náà wí fún un pé, “Olúwa, ó ti ń rùn nísinsin yìí, nítorí pé ó di ọjọ́ kẹrin tí ó tí kú.”
Yesu E amane sia: i, “Gele ga: i bebesole fasima!” Be bogoi ea aba Mada da Yesuma amane sia: i, “Hina! E da eso biyaduyale gala uli dogoi ganodini salabeba: le, dasai dagoi. Gaha bagade ganumu.”
40 Jesu wí fún un pé, “Èmi kò ti wí fún ọ pé, bí ìwọ bá gbàgbọ́, ìwọ yóò rí ògo Ọlọ́run?”
Yesu da bu adole i, “Na musa: dima sia: i dagoi! Di dafawaneyale dawa: sea, Gode Ea hadigidafa ba: mu.”
41 Nígbà náà ni wọ́n gbé òkúta náà kúrò (níbi tí a tẹ́ ẹ sí). Jesu sì gbé ojú rẹ̀ sókè, ó sì wí pé, “Baba, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí tí ìwọ gbọ́ tèmi.
Amalalu, ilia da gele logo ga: su besole fasi. Yesu da ba: le gadole, Godema nodone sia: i, “Ada! Di da Na sia: nababeba: le, Na Dima nodone sia: sa.
42 Èmi sì ti mọ̀ pé, ìwọ a máa gbọ́ ti èmi nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n nítorí ìjọ ènìyàn tí ó dúró yìí ni mo ṣe wí i, kí wọn ba à lè gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi.”
Di da eso huluane Na sia: naba! Amo Na dawa: Be dunu gui esala ilia da Dia Na asunasi dagoi amo dafawaneyale dawa: ma: ne, Na da amo sia: sa!”
43 Nígbà tí ó sì wí bẹ́ẹ̀ tan, ó kígbe lóhùn rara pé, “Lasaru, jáde wá.”
Amo sia: nanu, E da ha: giwane wele sia: i, “La: salase! Di wa: legadole, misa!”
44 Ẹni tí ó kú náà sì jáde wá, tí a fi aṣọ òkú dì tọwọ́ tẹsẹ̀ a sì fi gèlè dì í lójú. Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ tú u, ẹ sì jẹ́ kí ó máa lọ!”
La: salase da wa: legadole, gadili misi. Ea da: i hodo amola ea odagi da bogoi abula amoga sosoi ba: i. Yesu E amane sia: i, “E hahawane masa: ne, ea bogoi abula fadegale fasima.”
45 Nítorí náà ni ọ̀pọ̀ àwọn Júù tí ó wá sọ́dọ̀ Maria, tí wọ́n rí ohun tí Jesu ṣe, ṣe gbà á gbọ́.
Dunu bagohame Melima fidimusa: misi, amo Yesu Ea hou ba: beba: le, ilia Yesu Ea hou lalegagumusa: dafawaneyale dawa: i dagoi.
46 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn tọ àwọn Farisi lọ, wọ́n sì sọ fún wọn ohun tí Jesu ṣe.
Be mogili da Fa: lisi dunu ilima buhagili, Yesu Ea hou ilima adole i.
47 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi pe ìgbìmọ̀ jọ. Wọ́n sì wí pé, “Kín ni yóò jẹ àṣeyọrí wa? Nítorí ọkùnrin yìí ń ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì.
Amalalu, Fa: lisi dunu, gobele salasu ouligisu dunu, amola asigilai Gasolo dunu, ilia da gilisili fofada: lalu, amane sia: i, “Ninia adi hamoma: bela: ? Amo dunu da musa: hame ba: su dawa: digima: ne olelesu bagohame hamonana.
48 Bí àwa bá fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀, gbogbo ènìyàn ni yóò gbà á gbọ́, àwọn ará Romu yóò sì wá gba ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè wa pẹ̀lú.”
Ninia da Ea logo hame hedofasea, dunu huluanedafa da ea hou dafawaneyale dawa: mu. Amasea, Louma dadi gagui dunu da wa: legadole, ninia Debolo Diasu amola ninia fi dunu gugunufinisimu.”
49 Ṣùgbọ́n Kaiafa, ọ̀kan nínú wọn, ẹni tí í ṣe olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin kò mọ ohunkóhun rárá!
Amo ode, dunu ea dio amo Ga: iafa: se da Gobele salasu Ouligisu dunu esalu. E da ilima amane sia: i, “Dilia da gagaoui dunu.
50 Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì ronú pé, ó ṣàǹfààní fún wa, kí ènìyàn kan kú fún àwọn ènìyàn kí gbogbo orílẹ̀-èdè má ba à ṣègbé.”
Ninia fi dunu huluane bogosa: besa: le, dunu afadafa fawane da dunu huluane mae bogoma: ne hi fawane bogomu da defea. Dilia da amo hame dawa: bela: ?”
51 Kì í ṣe fún ara rẹ̀ ni ó sọ èyí ṣùgbọ́n bí ó ti jẹ́ olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó sọtẹ́lẹ̀ pé, Jesu yóò kú fún orílẹ̀-èdè náà,
E da amo sia: hisu fawane hame sia: i. Be e da Gobele salasu Ouligisu dunu hawa: hamobeba: le, Yesu da Yu fi dunu ili wadela: i hou hamoiba: le dabe ima: ne bogomu, amo e da mae dawa: iwane ba: la: lusu.
52 kì sì í ṣe kìkì fún orílẹ̀-èdè náà nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn ọmọ Ọlọ́run tí ó fọ́nká kiri, kí ó le kó wọn papọ̀, kí ó sì sọ wọ́n di ọ̀kan.
Be Yu fi dunu fidima: ne amo fawane hame. Be Gode Ea fidafa dunu huluane osobo bagadega afafai, amo huluane gilisisu afadafa fawane bu hamoma: ne, e da Yesu da bogomu sia: i.
53 Nítorí náà, láti ọjọ́ náà lọ ni wọ́n ti jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti pa á.
Amogalu, Yu ouligisu dunu mae helefili, Yesu medole legemu logo hogoi helei.
54 Nítorí náà Jesu kò rìn ní gbangba láàrín àwọn Júù mọ́; ṣùgbọ́n ó ti ibẹ̀ lọ sí ìgbèríko kan tí ó súnmọ́ aginjù, sí ìlú ńlá kan tí a ń pè ní Efraimu, níbẹ̀ ni ó sì wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Amaiba: le, dunu huluane da ba: sa: besa: le, Yesu da Yudia soge ganodini hame ahoasu. Be E da wamowane diasu ea dio amo Ifala: ime, wadela: i hafoga: i soge amo ganodini dialu, amoga asili, E amola Ea ado ba: su dunu esalu.
55 Àjọ ìrékọjá àwọn Júù sì súnmọ́ etílé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ láti ìgbèríko sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu ṣáájú ìrékọjá, láti ya ara wọn sí mímọ́.
Baligisu Lolo Nasu da gadeneiba: le, dunu bagohame da ilia soge yolesili, Yelusaleme moilai bai bagadega doaga: musa: asi. Ilia musa: hou hahamomusa: , amola sema dodofesu hou hamomusa: , asi.
56 Nígbà náà ni wọ́n ń wá Jesu, wọ́n sì ń bá ara wọn sọ̀, bí wọ́n ti dúró ní tẹmpili, wí pé, “Kín ni ẹyin ti rò ó sí pé kì yóò wá sí àjọ?”
Ilia da Yesu hogosu. Be Debolo Diasu ganodini ilia gilisisia, ilia amane sia: dasu, “Dilia adi dawa: bela: ? E da Lolo Nasu amoma misa: bela: ? Ma hame misa: bela: ?”
57 Ǹjẹ́ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi ti pàṣẹ pé bí ẹnìkan bá mọ ibi tí ó gbé wà, kí ó fi í hàn, kí wọn ba à lè mú un.
Gobele salasu ouligisu dunu amola Fa: lisi dunu, ilia da dunu huluane ilima ilia da Yesu ba: sea, ilima adoma: ne gasa bagadewane sia: i dagoi. Ilia da Yesu afugili gagulaligimusa: dawa: i galu.