< John 10 >
1 “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹni tí kò bá gba ẹnu-ọ̀nà wọ inú agbo àgùntàn, ṣùgbọ́n tí ó bá gba ibòmíràn gun òkè, òun náà ni olè àti ọlọ́ṣà.
[Jesus continuava dizendo aos fariseus, e sobre eles ][MET], “Escutem bem o que digo. Quem não quiser entrar no curral das ovelhas pela porta, se ele pular o muro e entrar por outra maneira, é ladrão ou bandido.
2 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ti ẹnu-ọ̀nà wọlé, Òun ni olùṣọ́ àwọn àgùntàn.
O homem que entra no curral pela porta é o pastor das ovelhas.
3 Òun ni aṣọ́nà yóò ṣílẹ̀kùn fún; àwọn àgùntàn gbọ́ ohùn rẹ̀, ó sì pe àwọn àgùntàn tirẹ̀ lórúkọ, ó sì ṣe amọ̀nà wọn jáde.
O homem que vigia a porta [de noite ]abre a porta para ele. As ovelhas reconhecem a voz dele. Ele chama suas próprias ovelhas, [chamando ]os nomes [que ele ]lhes [deu. ]Então ele as guia para fora do curral.
4 Nígbà tí ó bá sì ti mú àwọn àgùntàn tirẹ̀ jáde, yóò síwájú wọn, àwọn àgùntàn yóò sì máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, nítorí tí wọ́n mọ ohùn rẹ̀.
Após fazer saírem todas as ovelhas dele, ele vai na frente delas. As ovelhas dele o seguem porque reconhecem [e obedecem ]a voz dele.
5 Wọn kò jẹ́ tọ àlejò lẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọn a sá kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí tí wọn kò mọ ohùn àlejò.”
Mas elas nunca seguem um estranho. Pelo contrário, vão fugir dele, pois não reconhecem a voz do estranho”.
6 Òwe yìí ni Jesu pa fún wọn, ṣùgbọ́n òye ohun tí nǹkan wọ̀nyí tí ó ń sọ fún wọn kò yé wọn.
Jesus disse isso [para ilustrar a diferença entre si mesmo e os fariseus, que enganavam o povo. ]Mas eles não entendiam o que Ele lhes dizia.
7 Nítorí náà Jesu tún wí fún wọn pé, “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, Èmi ni ìlẹ̀kùn àwọn àgùntàn.
Por isso Jesus falou de novo com eles, dizendo, “Escutem bem o que digo. Estou dizendo que sou [como ][MET] uma porta para as ovelhas [entrarem no curral por ser eu aquele que permite que as pessoas entrem na presença de Deus. ]
8 Olè àti ọlọ́ṣà ni gbogbo àwọn tí ó ti wà ṣáájú mi, ṣùgbọ́n àwọn àgùntàn kò gbọ́ tiwọn.
Todos [os seus líderes religiosos ]que vinham antes, [sem minha autoridade, ]são [como ][MET] ladrões e bandidos [porque agem de uma forma violenta e desonesta em benefício deles mesmos. ]Mas, [assim como as ]ovelhas não [prestam atenção aos estranhos, o povo de Deus não ]lhes dá ouvidos.
9 Èmi ni ìlẹ̀kùn, bí ẹnìkan bá bá ọ̀dọ̀ mi wọlé, òun ni a ó gbàlà, yóò wọlé, yóò sì jáde, yóò sì rí koríko.
Sou [como ]uma porta. Todos aqueles serão salvos {[Deus ]vai salvar todos} que vierem [a Ele, confiando em ]mim. [Assim como as ovelhas ]entram e saem [em segurança ]pela porta para encontrar pasto [MET], [vou providenciar tudo para elas e protegê-las. ]
10 Olè kì í wá bí kò ṣe láti jalè, láti pa, àti láti parun; èmi wá kí wọn lè ní ìyè, àní kí wọn lè ní i lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Os ladrões entram [no curral das ovelhas ]só para roubar ou matar ou destruir [as ovelhas ][MET]. [Da mesma forma, seus líderes religiosos prejudicam espiritualmente o povo de Deus. ]Mas eu vim para que as pessoas possam ter a vida [eterna/espiritual], e que possam ter abundantemente [tudo que precisam para sustentá-las espiritualmente.]
11 “Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, olùṣọ́-àgùntàn rere fi ọkàn rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn.
Sou [como ]um bom pastor. Um bom pastor [está disposto a ]morrer para salvar as ovelhas [MET]. [Semelhantemente, estou disposto a me sacrificar para salvar aqueles que me pertencem. ]
12 Ṣùgbọ́n alágbàṣe, tí kì í ṣe olùṣọ́-àgùntàn, ẹni tí àwọn àgùntàn kì í ṣe tirẹ̀, ó rí ìkookò ń bọ̀, ó sì fi àgùntàn sílẹ̀, ó sì fọ́n wọn ká kiri.
Um empregado contratado [para cuidar das ovelhas ]não é o pastor, o dono das ovelhas. Portanto, quando ele vê um lobo se aproximar, ele abandona as ovelhas e foge. Então o lobo ataca o rebanho de ovelhas, [pega uma das ovelhas e ]faz as outras se espalharem.
13 Òun sálọ nítorí tí ó jẹ́ alágbàṣe, kò sì náání àwọn àgùntàn.
O empregado foge porque é apenas um homem contratado. Ele não se preocupa sobre [o que acontece à]s ovelhas [MET]. [Semelhantemente, seus líderes religiosos não se preocupam sobre o que acontece ao povo de Deus. ]
14 “Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, mo sì mọ àwọn tèmi, àwọn tèmi sì mọ̀ mí.
Sou [como ]um bom pastor. [Assim como um pastor conhece suas ]ovelhas [MET], conheço aqueles que me pertencem, e eles me conhecem,
15 Gẹ́gẹ́ bí Baba ti mọ̀ mí, tí èmi sì mọ Baba, mo sì fi ọkàn mi lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn.
bem como meu Pai me conhece e eu conheço meu Pai. Além disso, estou [disposto a ]me sacrificar em benefício [daqueles que me pertencem. ]
16 Èmi sì ní àwọn àgùntàn mìíràn, tí kì í ṣe agbo yìí: àwọn ni èmi yóò mú wá pẹ̀lú, wọn yóò sì gbọ́ ohùn mi; wọn ó sì jẹ́ agbo kan, olùṣọ́-àgùntàn kan.
E tenho outros que vão me pertencer [algum dia, e que não são judeus. ]Eles serão [como ][MET] ovelhas de outro curral. Devo trazê-los [para Deus/para mim ]também. Eles vão prestar atenção àquilo que digo, e eventualmente [todos aqueles que me pertencem ]serão [como ]um rebanho, e serei [como ][MET] seu único pastor.
17 Nítorí náà ni Baba mi ṣe fẹ́ràn mi, nítorí tí mo fi ẹ̀mí mi lélẹ̀, kí èmi lè tún gbà á.
Meu pai me ama porque vou sacrificar minha vida. Mas [depois de fazer isso, ]vou voltar a viver.
18 Ẹnìkan kò gbà á lọ́wọ́ mi, ṣùgbọ́n mo fi í lélẹ̀, mo sì lágbára láti tún gbà á. Àṣẹ yìí ni mo ti gbà wá láti ọ̀dọ̀ Baba mi.”
Ninguém me faz morrer. Pelo contrário, eu mesmo me sacrifico. Tenho autoridade para me sacrificar e autoridade para tornar a viver novamente. É isso que meu Pai me mandou fazer”.
19 Nítorí náà ìyapa tún wà láàrín àwọn Júù nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.
Após ouvir estas palavras ditas por Jesus, os judeus ficaram novamente divididos.
20 Ọ̀pọ̀ nínú wọn sì wí pé, “Ó ní ẹ̀mí èṣù, orí rẹ̀ sì dàrú; èéṣe tí ẹ̀yin fi ń gbọ́rọ̀ rẹ̀?”
Muitos deles disseram “Um demônio O controla, fazendo com que fique louco. É inútil/Por que devemos— [RHQ] escutá-lo!?”
21 Àwọn mìíràn wí pé, “Ìwọ̀nyí kì í ṣe ọ̀rọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù. Ẹ̀mí èṣù lè la ojú àwọn afọ́jú bí?”
Mas outros disseram, “O que Ele está dizendo não é coisa que diria um homem controlado por um demônio. Nenhum demônio/Como é que um demônio— [RHQ] poderia fazer um cego ver [como Ele fez]!?”
22 Àkókò náà sì jẹ́ àjọ̀dún ìyàsímímọ́ ní Jerusalẹmu, ni ìgbà òtútù.
Tinha chegado o dia do festival [dedicado à lembrança da época quando os antepassados ]dedicaram novamente [o templo em Jerusalém. ]Era inverno.
23 Jesu sì ń rìn ní tẹmpili, ní ìloro Solomoni.
Jesus estava no pátio do templo, andando pelo [lugar que as pessoas chamavam o ]Alpendre do [Rei ]Salomão.
24 Nítorí náà àwọn Júù wá dúró yí i ká, wọ́n sì wí fún un pé, “Ìwọ ó ti mú wa ṣe iyèméjì pẹ́ tó? Bí ìwọ bá ni Kristi náà, wí fún wa gbangba.”
Os [líderes ]judaicos [SYN] se reuniram ao redor dele, dizendo, “Até quando você vai nos deixar —na dúvida/sem saber na certa— [se é o Messias ou não]? Se você é o Messias, diga-nos claramente”!
25 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi ti wí fún yín, ẹ̀yin kò sì gbàgbọ́; iṣẹ́ tí èmi ń ṣe lórúkọ Baba mi, àwọn ni ó ń jẹ́rìí mi.
Jesus lhes respondeu, “Já lhes disse [que sou o Messias, ]mas vocês não me acreditam! Vocês devem saber quem sou eu por causa dos milagres que faço com autoridade do meu Pai [MTY].
26 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbàgbọ́, nítorí ẹ̀yin kò sí nínú àwọn àgùntàn mi, gẹ́gẹ́ bí mo tí wí fún yín.
Mas em vez disso, pois vocês não [me ]pertencem [como ][MET] ovelhas [que pertencem ao seu pastor, ]vocês não creem em mim.
27 Àwọn àgùntàn mi ń gbọ́ ohùn mi, èmi sì mọ̀ wọ́n, wọn a sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
[Assim como as ovelhas obedecem ]a voz [do seu pastor ][MET], meu [povo me obedece. ]Conheço os de meu povo, e eles se tornaram meus discípulos.
28 Èmi sì fún wọn ní ìyè àìnípẹ̀kun; wọn kì yóò sì ṣègbé láéláé, kò sí ẹni tí ó lè já wọn gbà kúrò lọ́wọ́ mi. (aiōn , aiōnios )
Vou dar-lhes a vida eterna. Ninguém jamais vai separá-los de mim para sempre. Ninguém vai arrancá-los de mim. (aiōn , aiōnios )
29 Baba mi, ẹni tí ó fi wọ́n fún mi pọ̀ ju gbogbo wọn lọ; kò sì ṣí ẹni tí ó lè já wọn gbà kúrò lọ́wọ́ Baba mi.
[O grupo ]que meu Pai me deu é mais caro/precioso que qualquer outra coisa (OU, Meu Pai, que os deu a mim, é maior que qualquer força oposta a eles). Portanto, ninguém pode arrancá-los de mim [MTY].
30 Ọ̀kan ni èmi àti Baba mi.”
Meu pai e eu somos iguais”.
31 Àwọn Júù sì tún mú òkúta, láti sọ lù ú.
Os [líderes ]judaicos [SYN] voltaram a pegar pedras com intenção de apedrejá-lo [e matá-lo, pois estavam zangados por Ele haver dito que era igual a Deus.]
32 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ rere ni mo fihàn yín láti ọ̀dọ̀ Baba mi wá, nítorí èwo nínú iṣẹ́ wọ̀nyí ni ẹ̀yin ṣe sọ mí ní òkúta?”
Mas Jesus lhes disse, “Vocês me viram fazer muitos milagres que meu Pai [me mandou fazer. Vocês devem se dar conta, ao verem tais coisas, que sou igual a Deus. ]Então, por qual desse milagres [IRO] vocês querem [matar-me], apedrejando-me?”
33 Àwọn Júù sì dá a lóhùn pé, “Àwa kò sọ ọ́ lókùúta nítorí iṣẹ́ rere, ṣùgbọ́n nítorí ọ̀rọ̀-òdì, àti nítorí ìwọ tí í ṣe ènìyàn ń fi ara rẹ pe Ọlọ́run.”
Os [líderes ]judaicos [SYN] responderam, “[Queremos ]apedrejá-lo, não porque tenha feito um grande milagre. Em vez disso, estamos querendo fazê-lo porque você não passa de um simples homem, mas alega que é Deus”!
34 Jesu dá wọn lóhùn pé, “A kò ha tí kọ ọ́ nínú òfin yín pé, ‘Mo ti wí pé, Ọlọ́run ni ẹ̀yin jẹ́’?
Jesus lhes respondeu, “Nas Escrituras está escrito {—[alguém/o salmista— ]escreveu} [RHQ] [o que Deus disse aos governantes que Ele tinha nomeado, ]‘Eu já disse que vocês são [como ]deuses.’
35 Bí ó bá pè wọ́n ní ‘ọlọ́run,’ àwọn ẹni tí a fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún, a kò sì lè ba ìwé mímọ́ jẹ́.
Deus disso isso [àqueles líderes quando Ele os nomeou. Ninguém se opôs a isso. ]E nenhuma afirmação das Escrituras pode ser anulada {ninguém pode anular algo que consta nas Escrituras}. Mas sou eu que meu Pai consagrou para lhe pertencer integralmente. Ele me mandou para cá, a este mundo.
36 Kín ni ẹyin ha ń wí ní ti ẹni tí Baba yà sọ́tọ̀, tí ó sì rán sí ayé kín lo de ti ẹ fi ẹ̀sùn kàn mi pé mò ń sọ̀rọ̀-òdì nítorí pé mo sọ pé, ‘Èmi ni Ọmọ Ọlọ́run.’
Por isso, —vocês não devem/por que vocês— [RHQ] queixar-se/se queixam por eu afirmar que sou Deus? Por que vocês estão/Vocês não devem estar— [RHQ] zangados comigo por eu haver dito que [sou igual a Deus quando digo que ]sou o Filho de Deus/o homem que é também Deus.
37 Bí èmi kò bá ṣe iṣẹ́ Baba mi, ẹ má ṣe gbà mí gbọ́.
Se não fossem os milagres que meu Pai [me mandou fazer, eu não esperaria que ]vocês me acreditassem.
38 Ṣùgbọ́n bí èmi bá ṣe wọ́n, bí ẹ̀yin kò tilẹ̀ gbà mí gbọ́, ẹ gbà iṣẹ́ náà gbọ́, kí ẹ̀yin ba à lè mọ̀, kí ó sì lè yé yín pé, Baba wà nínú mi, èmi sì wà nínú rẹ̀.”
Mas, já que faço estes milagres, acreditem [aquilo que ]estes milagres [esclarecem sobre mim, ]mesmo que não acreditem o que [digo. ]Se assim fizerem, saberão e entenderão que meu Pai tem verdadeira intimidade comigo e eu com meu Pai”.
39 Wọ́n sì tún ń wá ọ̀nà láti mú un: ó sì bọ́ lọ́wọ́ wọn.
Após ouvirem isso, eles tentaram pegá-lo novamente, mas Ele se livrou deles.
40 Ó sì tún kọjá lọ sí apá kejì Jordani sí ibi tí Johanu ti kọ́kọ́ ń bamitiisi; níbẹ̀ ni ó sì jókòó.
Então Jesus voltou [conosco ]para [o lado leste ]do [Rio ]Jordão. Fomos até o lugar onde João antigamente batizava [as pessoas. ]Ele ficou lá [por —algum tempo/umas semanas. ]
41 Àwọn ènìyàn púpọ̀ sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Johanu kò ṣe iṣẹ́ àmì kan, Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni ohun gbogbo tí Johanu sọ nípa ti ọkùnrin yìí.”
Muitas pessoas foram ter com Ele. Elas diziam, “João nunca fez nenhum milagre, [mas este homem já fez muitos milagres! ]Tudo que João disse acerca deste homem é verdade”!
42 Àwọn ènìyàn púpọ̀ níbẹ̀ sì gbà á gbọ́.
Muitas pessoas [que ]lá [foram ]passaram a crer —[que era Ele o Messias/que Ele realmente tinha vindo de Deus.]