< Joel 3 >
1 “Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti ní àkókò náà, nígbà tí èmi tún mú ìgbèkùn Juda àti Jerusalẹmu padà bọ̀.
Pagammoan, iti dayta met laeng a tiempo, inton isublik idiay Juda ken Jerusalem dagiti naitalaw a tattao,
2 Èmi yóò kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ pẹ̀lú èmi yóò sì mú wọn wá sí àfonífojì Jehoṣafati. Èmi yóò sì bá wọn wíjọ́ níbẹ̀ nítorí àwọn ènìyàn mi, àti nítorí Israẹli ìní mi, tí wọ́n fọ́nká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè, wọ́n sì pín ilẹ̀ mi.
ummongekto dagiti amin a nasion, ket paapanek ida iti tanap ni Jehosafat. Ukomekto ida sadiay gapu kadagiti tattaok ken iti tawidko nga Israel nga inwarawarasda kadagiti nasion, ken gapu ta biningay-bingayda ti dagak.
3 Wọ́n si ti di ìbò fún àwọn ènìyàn mi; wọ́n sì ti fi ọmọdékùnrin kan fún panṣágà obìnrin kan, wọ́n sì ta ọmọdébìnrin kan fún ọtí wáìnì, kí wọ́n kí ó lè mu.
Pinagbibinnunotanda dagiti tattaok, insukatda dagiti lallaki kadagiti balangkantis, ken naglakoda iti babai a kasukat ti arak tapno makainumda.
4 “Nísinsin yìí, kí ni ẹ̀yin ní fi mí ṣe Tire àti Sidoni, àti gbogbo ẹ̀yin ẹkún Filistia? Ẹ̀yin yóò ha sàn ẹ̀san fún mi? Bí ẹ̀yin bá sì san ẹ̀san fún mi, ní kánkán àti ní kíákíá ní èmi yóò san ẹ̀san ohun ti ẹ̀yin ṣe padà sórí ara yín.
Ita, apay a kaungetdak, Tiro, Sidon, ken amin a rehion ti Filistia? Balsendak kadi? Urayno balsendak, ipalak-amkonto a dagus kadakayo ti panangibalesyo.
5 Nítorí tí ẹ̀yin tí mú fàdákà mi àti wúrà mi, ẹ̀yin si tí mú ohun rere dáradára mi lọ sínú tẹmpili yín.
Ta innalayo ti pirak ken balitokko, ket impanyo dagiti napapateg a gamengko kadagiti temployo.
6 Àti àwọn ọmọ Juda, àti àwọn ọmọ Jerusalẹmu ní ẹ̀yin ti tà fún àwọn ará Giriki, kí ẹ̀yin bá à lè sí wọn jìnnà kúrò ní agbègbè ilẹ̀ ìní wọn.
Inlakoyo dagiti tattao ti Juda ken Jerusalem kadagiti Griego, tapno maipanawda kadagiti dagada.
7 “Kíyèsi í, èmi yóò gbé wọ́n dìde kúrò níbi tì ẹ̀yin ti tà wọ́n sí, èmi yóò sì san ẹ̀san ohun ti ẹ ṣe padà sórí ara yín.
Ngem kitaenyo, dandanik idan ipanaw kadagiti lugar a nangilakoanyo kadakuada, ket supapakankayonto iti maiparbeng kadakayo.
8 Èmi yóò si tà àwọn ọmọkùnrin yín àti àwọn ọmọbìnrin yín sí ọwọ́ àwọn ọmọ Juda, wọ́n yóò sì tà wọ́n fún àwọn ara Sabeani, fún orílẹ̀-èdè kan tí ó jìnnà réré.” Nítorí Olúwa ní o ti sọ ọ.
Ilakokto dagiti annakyo a lallaki ken babbai kadagiti ima dagiti tattao ti Juda. Ilakodanto ida kadagiti taga-Saba, iti adayo a nasion. Ta ni Yahweh ti nagsao iti daytoy.
9 Ẹ kéde èyí ní àárín àwọn kèfèrí; ẹ dira ogun, ẹ jí àwọn alágbára. Jẹ kí àwọn ajagun kí wọn bẹ̀rẹ̀ ogun.
Iwaragawagyo daytoy kadagiti nasion: 'Agsaganakayo a makigubat, ummongenyo dagiti nabileg a lallaki, paasitgenyo ida, pagpuestoenyo dagiti amin a mannakigubat.
10 Ẹ fi irin ìtulẹ̀ yín rọ idà, àti dòjé yín rọ ọ̀kọ̀. Jẹ́ kí aláìlera wí pé, “Ara mi le koko.”
Pitpitenyo dagiti aradoyo tapno agbalin a kampilan ken dagiti kumpayyo tapno agbalin a gayang. Kunaen koma dagiti nakapuy, “Napigsaak.”
11 Ẹ wá kánkán, gbogbo ẹ̀yin kèfèrí láti gbogbo àyíká, kí ẹ sì gbá ara yín jọ yí káàkiri. Níbẹ̀ ní kí o mú àwọn alágbára rẹ sọ̀kalẹ̀, Olúwa.
Darasenyo ti umay, dakayo amin a kabangibang a nasion, aguummongkayo.' O Yahweh, paapanem sadiay dagiti nabileg a mannakigubatmo.
12 “Ẹ jí, ẹ sì gòkè wá sí àfonífojì Jehoṣafati ẹ̀yin kèfèrí: nítorí níbẹ̀ ní èmi yóò jókòó láti ṣe ìdájọ́ àwọn kèfèrí yí káàkiri.
Agriing koma dagiti nasion ket mapanda idiay tanap ni Jehosafat. Ta agtugawakto sadiay a mangukom kadagiti amin a kabangibang a nasion.
13 Ẹ tẹ dòjé bọ̀ ọ́, nítorí ìkórè pọ́n. Ẹ wá, ẹ sọ̀kalẹ̀, nítorí ìfúntí kún, nítorí àwọn ọpọ́n kún àkúnwọ́sílẹ̀, nítorí ìwà búburú wọn pọ̀!”
Alaenyo dagiti kumpay, ta naluomen ti apit. Umaykayo, pespesenyo dagiti ubas, ta napnon ti pagpespesan ti ubas, agluplupias dagiti pagkargaan, ta kasta unay ti kinadangkesda.”
14 Ọ̀pọ̀lọpọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní àfonífojì ìpinnu! Nítorí ọjọ́ Olúwa kù si dẹ̀dẹ̀ ní àfonífojì ìdájọ́.
Adda iti ariwawa, ariwawa idiay tanap ti Panangukom. Ta asidegen ti aldaw ni Yahweh iti tanap ti Panangukom.
15 Oòrùn àti òṣùpá yóò ṣú òkùnkùn, àti àwọn ìràwọ̀ kí yóò tan ìmọ́lẹ̀ wọn mọ́.
Sumipnget ti init ken bulan, saanen nga agraniag dagiti bituen.
16 Olúwa yóò sí ké ramúramù láti Sioni wá, yóò sì fọ ohùn rẹ̀ jáde láti Jerusalẹmu wá; àwọn ọ̀run àti ayé yóò sì mì tìtì. Ṣùgbọ́n Olúwa yóò ṣe ààbò àwọn ènìyàn rẹ̀, àti agbára àwọn ọmọ Israẹli.
Agpukkawto ni Yahweh manipud Sion, ken ipigsananto ti timekna idiay Jerusalem. Agkintayegto ti langit ken daga, ngem agbalinto ni Yahweh a kamang dagiti tattaona, ken sarikedked dagiti tattao ti Israel.
17 “Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, tí ń gbé Sioni òkè mímọ́ mi. Ìgbà náà ni Jerusalẹmu yóò jẹ́ mímọ́; àwọn àjèjì kì yóò sì kó o mọ́.
“Ket maammoanyonto a siak ni Yahweh a Diosyo, nga agnanaed idiay Sion, ti nasantoan a bantayko. Kalpasanna, agbalinto a nasantoan ti Jerusalem, ken awanto ti armada a mangparmek manen kenkuana.
18 “Ní ọjọ́ náà, àwọn òkè ńlá yóò máa kán ọtí wáìnì tuntun sílẹ̀, àwọn òkè kéékèèké yóò máa sàn fún wàrà; gbogbo odò Juda tí ó gbẹ́ yóò máa sàn fún omi. Orísun kan yóò sì ṣàn jáde láti inú ilé Olúwa wá, yóò sì rin omi sí àfonífojì Ṣittimu.
Iti dayta nga aldaw, agtedtedto ti nasam-it nga arak kadagiti kabanbantayan, agayusto iti gatas kadagiti turturod, agayusto iti danum kadagiti amin a waig ti Juda, ken agtaudto ti burayok iti balay ni Yahweh ket padanumannanto ti tanap ti Acacia.
19 Ṣùgbọ́n Ejibiti yóò di ahoro, Edomu yóò sì di aṣálẹ̀ ahoro, nítorí ìwà ipá tí a hù sì àwọn ọmọ Juda, ní ilẹ̀ ẹni tí wọ́n ti ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀.
Agbalinto a langalang ti Egipto, ken agbalinto a disierto ti Edom, gapu iti kinaranggas nga inaramidda kadagiti tattao ti Juda, gapu ta pinapatayda dagiti inosente a tattao idiay daga dagiti tattao ti Juda.
20 Ṣùgbọ́n Juda yóò jẹ́ ibùgbé títí láé, àti Jerusalẹmu láti ìran dé ìran.
Ngem agbiagto ti Juda iti agnanayon, ken agbiagto ti Jerusalem iti tunggal henerasion.
21 Nítorí èmi yóò wẹ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ wọn nù, tí èmi kò tí ì wẹ̀nù.
Ibaleskonto ti pannakatayda a saanko pay a naibales,” ta agnanaed ni Yahweh idiay Sion.