< Joel 3 >
1 “Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àti ní àkókò náà, nígbà tí èmi tún mú ìgbèkùn Juda àti Jerusalẹmu padà bọ̀.
Hatnae tueng navah, yampa vah man lah kaawm e Judahnaw khocanaw hoi Jerusalem khocanaw bout ka thokhai toteh,
2 Èmi yóò kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ pẹ̀lú èmi yóò sì mú wọn wá sí àfonífojì Jehoṣafati. Èmi yóò sì bá wọn wíjọ́ níbẹ̀ nítorí àwọn ènìyàn mi, àti nítorí Israẹli ìní mi, tí wọ́n fọ́nká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè, wọ́n sì pín ilẹ̀ mi.
miphun pueng ka pâkhueng vaiteh, Jehoshaphat yon koe ka kaw han. Ahnimouh ni ka ram heh a kârei awh teh, ram tangkuem dawk kâkayei e kaie râw tami Isarelnaw koe lah, ka kampangkhai vaiteh lawk ka ceng han.
3 Wọ́n si ti di ìbò fún àwọn ènìyàn mi; wọ́n sì ti fi ọmọdékùnrin kan fún panṣágà obìnrin kan, wọ́n sì ta ọmọdébìnrin kan fún ọtí wáìnì, kí wọ́n kí ó lè mu.
Ka taminaw hah cungpam lah a rayu awh toe. Tongpa camonaw hah a tak kâyawtnaw hoi thoseh napui camonaw hah a nei awh hane misurtui hoi thoseh, athung awh toe.
4 “Nísinsin yìí, kí ni ẹ̀yin ní fi mí ṣe Tire àti Sidoni, àti gbogbo ẹ̀yin ẹkún Filistia? Ẹ̀yin yóò ha sàn ẹ̀san fún mi? Bí ẹ̀yin bá sì san ẹ̀san fún mi, ní kánkán àti ní kíákíá ní èmi yóò san ẹ̀san ohun ti ẹ̀yin ṣe padà sórí ara yín.
Oe, Taire kho, Sidon kho, Filistin ram hoi kâhnai e ramnaw, kai hah na taran awh han namaw. Kai na taran awh pawiteh, hote taran hah nangmouh koe bout ka pha sak han.
5 Nítorí tí ẹ̀yin tí mú fàdákà mi àti wúrà mi, ẹ̀yin si tí mú ohun rere dáradára mi lọ sínú tẹmpili yín.
Nangmouh ni kaie sui ngun hah na la teh, ka ngai kawi e hnonaw hah namamae bawkim dawk na hruek awh dawk thoseh,
6 Àti àwọn ọmọ Juda, àti àwọn ọmọ Jerusalẹmu ní ẹ̀yin ti tà fún àwọn ará Giriki, kí ẹ̀yin bá à lè sí wọn jìnnà kúrò ní agbègbè ilẹ̀ ìní wọn.
Judahnaw, Jerusalem khocanaw hah amamae kho thung hoi kho hlanae koe a kampuen awh nahanlah Jentelnaw koe na yo awh dawk thoseh,
7 “Kíyèsi í, èmi yóò gbé wọ́n dìde kúrò níbi tì ẹ̀yin ti tà wọ́n sí, èmi yóò sì san ẹ̀san ohun ti ẹ ṣe padà sórí ara yín.
nangmouh ni na yonae hmuen koehoi ka kangdue vaiteh ahnimouh koe na sak awh e naw hah nangmae lû dawk ka pha sak han.
8 Èmi yóò si tà àwọn ọmọkùnrin yín àti àwọn ọmọbìnrin yín sí ọwọ́ àwọn ọmọ Juda, wọ́n yóò sì tà wọ́n fún àwọn ara Sabeani, fún orílẹ̀-èdè kan tí ó jìnnà réré.” Nítorí Olúwa ní o ti sọ ọ.
Nangmae canu capanaw hai Judahnaw koe ka yo vaiteh ahnimouh ni kho hlanae koe, Sheba ram lah na yo awh han. Hottelah BAWIPA ni a dei toe.
9 Ẹ kéde èyí ní àárín àwọn kèfèrí; ẹ dira ogun, ẹ jí àwọn alágbára. Jẹ kí àwọn ajagun kí wọn bẹ̀rẹ̀ ogun.
Hete hno heh alouke miphunnaw koe pathang loe. Taran tuk hanelah kârakueng awh nateh athakaawme taminaw hah pâhlaw awh leih. Ransanaw abuemlah pâkhueng nateh tho awh naseh.
10 Ẹ fi irin ìtulẹ̀ yín rọ idà, àti dòjé yín rọ ọ̀kọ̀. Jẹ́ kí aláìlera wí pé, “Ara mi le koko.”
Thenaw hah tahloi lah, tangkounnaw hah tahroe lah, dei awh. Tha kayoun e tami ni a thakasai poung e lah kâdei naseh.
11 Ẹ wá kánkán, gbogbo ẹ̀yin kèfèrí láti gbogbo àyíká, kí ẹ sì gbá ara yín jọ yí káàkiri. Níbẹ̀ ní kí o mú àwọn alágbára rẹ sọ̀kalẹ̀, Olúwa.
Tengpam kaawm e miphunnaw pueng kamkhueng awh nateh tho awh haw. Kâpâkhueng awh haw. Kamkhuengnae hmuen koe nangmae athakaawme taminaw hah BAWIPA ni rahimlah a pabo han.
12 “Ẹ jí, ẹ sì gòkè wá sí àfonífojì Jehoṣafati ẹ̀yin kèfèrí: nítorí níbẹ̀ ní èmi yóò jókòó láti ṣe ìdájọ́ àwọn kèfèrí yí káàkiri.
Alouke miphunnaw, Jehoshaphat yawn koe tho awh naseh. Tengpam kaawm e miphunnaw pueng lawkceng hanelah hote hmuen koe kai ka tahung han.
13 Ẹ tẹ dòjé bọ̀ ọ́, nítorí ìkórè pọ́n. Ẹ wá, ẹ sọ̀kalẹ̀, nítorí ìfúntí kún, nítorí àwọn ọpọ́n kún àkúnwọ́sílẹ̀, nítorí ìwà búburú wọn pọ̀!”
Cang a hmin toung dawkvah, a nahanelah tangkoun lat leih. Misur katinnae a kawi teh, Maroi dawk misurtui a poum toung dawkvah, tho nateh kum awh. Bangkongtetpawiteh, ahnimae yonnae teh a len poung toe.
14 Ọ̀pọ̀lọpọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní àfonífojì ìpinnu! Nítorí ọjọ́ Olúwa kù si dẹ̀dẹ̀ ní àfonífojì ìdájọ́.
Lawkcengnae ayawn dawk taminaw teh a kamkhueng awh. Lawkcengnae ayawn dawk BAWIPA e hnin teh a hnai toe.
15 Oòrùn àti òṣùpá yóò ṣú òkùnkùn, àti àwọn ìràwọ̀ kí yóò tan ìmọ́lẹ̀ wọn mọ́.
Kanî hoi thapa a hmo han. Âsinaw hai ang laipalah ao awh han.
16 Olúwa yóò sí ké ramúramù láti Sioni wá, yóò sì fọ ohùn rẹ̀ jáde láti Jerusalẹmu wá; àwọn ọ̀run àti ayé yóò sì mì tìtì. Ṣùgbọ́n Olúwa yóò ṣe ààbò àwọn ènìyàn rẹ̀, àti agbára àwọn ọmọ Israẹli.
BAWIPA ni Zion mon dawk hoi a huk toteh Jerusalem khothung hoi lawk a pathang toteh kalvan hoi talai ni a pâyaw han. Hatei BAWIPA teh a taminaw e kâuepnae, Isarelnaw hanlah thaonae lah ao han.
17 “Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, tí ń gbé Sioni òkè mímọ́ mi. Ìgbà náà ni Jerusalẹmu yóò jẹ́ mímọ́; àwọn àjèjì kì yóò sì kó o mọ́.
Kathounge Zion mon dawk kaawm e ka tamikathoungnaw e BAWIPA lah ka o e a panue awh han. Jerusalem khopui hai a thoung han. Hote khopui teh Jentelnaw ni bout coungroe awh mahoeh.
18 “Ní ọjọ́ náà, àwọn òkè ńlá yóò máa kán ọtí wáìnì tuntun sílẹ̀, àwọn òkè kéékèèké yóò máa sàn fún wàrà; gbogbo odò Juda tí ó gbẹ́ yóò máa sàn fún omi. Orísun kan yóò sì ṣàn jáde láti inú ilé Olúwa wá, yóò sì rin omi sí àfonífojì Ṣittimu.
Hote atueng navah ka radip poung e misurtui mon dawk hoi a yu han. Monrui dawk hoi sanutui a tâco han. Judah tuipui pueng tui a lawng han. BAWIPA e Imthungkhu dawk hoi tuihnu a phuek vaiteh Shittim yawn a duk sak han.
19 Ṣùgbọ́n Ejibiti yóò di ahoro, Edomu yóò sì di aṣálẹ̀ ahoro, nítorí ìwà ipá tí a hù sì àwọn ọmọ Juda, ní ilẹ̀ ẹni tí wọ́n ti ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀.
Judah ram dawk, yon ka tawn hoeh e taminaw hah a thei awh teh, Judahnaw hah a rektap awh dawkvah, Izip ram teh tami kingkadi lah ao han. Edom ram haiyah kahrawng patetlah kingdi han.
20 Ṣùgbọ́n Juda yóò jẹ́ ibùgbé títí láé, àti Jerusalẹmu láti ìran dé ìran.
Judah ram teh yungyoe e ram, Jerusalem khopui teh a yungyoe kangning e khopui lah ao han.
21 Nítorí èmi yóò wẹ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ wọn nù, tí èmi kò tí ì wẹ̀nù.
BAWIPA teh Zion mon dawk ao dawkvah, hote khocanaw a thei awh dawkvah ka khang sak hoeh rae Judahnaw e thiphu hah bout ka pathung han.