< Job 9 >

1 Jobu sì dáhùn ó sì wí pé,
Job ni bout a pathung teh,
2 “Èmi mọ̀ pe bẹ́ẹ̀ ni ní òtítọ́. Báwo ní ènìyàn yóò ha ti ṣe jẹ́ aláre níwájú Ọlọ́run?
Hetheh doeh tie hah atangcalah ka panue, hateiteh, Cathut e hmalah bangtelamaw tami teh a lan thai han.
3 Bí ó bá ṣe pé yóò bá a jà, òun kì yóò lè dalóhùn kan nínú ẹgbẹ̀rún ọ̀rọ̀.
Ama oun han ka ngai e awm pawiteh, avai 1,000 touh dawkvah vai touh boehai pathung thai mahoeh.
4 Ọlọ́gbọ́n nínú àwọn alágbára ní ipa ní Òun. Ta ni ó ṣe agídí sí i tí ó sì gbé fún rí?
Cathut teh, lungkaang poung e, athakaawme thayung lah ao. Ama taranlahoi lung ka patak sak e, a lam ka cawn e apimaw kaawm boi.
5 Ẹni tí ó sí òkè nídìí tí wọn kò sì mọ́: tí ó taari wọn ṣubú ní ìbínú rẹ̀.
Monnaw hah a puen teh, a lungkhueknae hoi a pathung torei teh, panuek awh hoeh.
6 Tí ó mi ilẹ̀ ayé tìtì kúrò ní ipò rẹ̀, ọwọ̀n rẹ̀ sì mì tìtì.
Talai a onae hmuen koehoi a kâhuet teh, a khomnaw hah koung a kâhuet sak.
7 Ó pàṣẹ fún oòrùn kò sì le è ràn, kí ó sì dí ìmọ́lẹ̀ ìràwọ̀ mọ́.
Kanî hah kâ a poe teh, tâcawt hoeh. Âsi angnae hah muen a ramuk.
8 Òun nìkan ṣoṣo ni ó ta ojú ọ̀run, ti ó sì ń rìn lórí ìgbì Òkun.
Ama dueng lahoi kalvan hah a ramuk teh, tuipui tuicapa van a cei.
9 Ẹni tí ó dá ìràwọ̀ Beari àti Orioni, Pleiadesi àti ìràwọ̀ púpọ̀ ti gúúsù.
Ama ni Latum, Kangduetaphai, Baritca, hoi akalae âsinaw hah a sak.
10 Ẹni tí ń ṣe ohun tí ó tóbi jù àwárí lọ, àní ohun ìyanu láìní iye.
Be panue thai hoeh e hnokalen e hai, touk thai hoeh e kângairu hnonaw hah a sak.
11 Kíyèsi i, ó ń kọjá lọ ní ẹ̀bá ọ̀dọ̀ mi, èmi kò sì rí i, ó sì kọjá síwájú, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò rí ojú rẹ̀.
Ka teng vah a cei ei ama teh, ka hmawt hoeh. Na ceihlawi e hai ka panuek hoeh.
12 Kíyèsi i, ó já a gbà lọ, ta ni ó lè fà á padà? Ta ni yóò bi í pé kí ni ìwọ ń ṣe nì?
Ama ni lat pawiteh, apinimaw a haw pouh thai han. Apinimaw bangmaw na sak, atipouh thai han.
13 Ọlọ́run kò ní fa ìbínú rẹ̀ sẹ́yìn, àwọn onírànlọ́wọ́ ti Rahabu a sì tẹríba lábẹ́ rẹ̀.
A lungkhueknae dawk hoi, Cathut ni kamlang takhai mahoeh toe. A khok rahim vah tami kâoup e kabawmnaw teh a tabut awh.
14 “Kí ní ṣe tí èmi ti n o fi ba ṣàròyé? Tí èmi yóò fi ma ṣe àwáwí?
Kai ni ama teh bangtelamaw, ka pathung thai han. Ama oun nahanelah, bangpatet e lawk maw kârawi han
15 Bí ó tilẹ̀ ṣe pé mo ṣe aláìlẹ́bi, èmi kò gbọdọ̀ dá a lóhùn; ṣùgbọ́n èmi ó gbàdúrà fún àánú.
Bangtelah kalan nakunghai, ama teh ka pathung thai mahoeh. Kai lawkcengkung koe pahrennae doeh ka hei hnawn han.
16 Bí èmi bá sì ké pè é, tí Òun sì dá mi lóhùn, èmi kì yóò sì gbàgbọ́ pé, Òun ti fetí sí ohùn mi.
Ka kaw pawiteh, ama ni na pato han. Ama ni ka lawk na thai pouh hane ka yuem hoeh.
17 Nítorí pé òun yóò lọ̀ mí lúúlúú pẹ̀lú ìjì ńlá, ó sọ ọgbẹ́ mi di púpọ̀ láìnídìí.
Bangkongtetpawiteh, kahlî kathout ni na hmang teh, a khuekhaw awm laipalah ka hmânaw hah a kampai sak.
18 Òun kì yóò jẹ́ kí èmi kí ó rí ẹ̀mí mi, ṣùgbọ́n ó mú ohun kíkorò kún un fún mi.
Ka kâha thai laipalah, reithai hoi na kawi sak.
19 Bí mo bá sọ ti agbára, wò ó! Alágbára ni, tàbí ní ti ìdájọ́, ta ni yóò dá àkókò fún mi láti rò?
A thasainae dawkvah ama teh, athakaawme lah ao. A lannae, kong dawk tetpawiteh, lawkcengnae dawk apinimaw ka hnin hah a khoe thai han.
20 Bí mo tilẹ̀ dá ara mi láre, ẹnu ara mi yóò dá mi lẹ́bi; bí mo wí pé olódodo ni èmi yóò sì fi mí hàn ní ẹni ẹ̀bi.
Ka kuep nakunghai, ka pahni ni yon na pen han, tanouk hanelah kaawm hoeh nakunghai, ka lanhoehnae hah a kamnue sak han.
21 “Olóòótọ́ ni mo ṣe, síbẹ̀ èmi kò kíyèsi ara mi, ayé mi ní èmi ìbá máa gàn.
Toun hoeh nahanlah ka o. Hateiteh, ka kâpanuek hoeh, ka hringnae heh ka hnueai toe.
22 Ohùn kan náà ni, nítorí náà ni èmi ṣe sọ: ‘Òun a pa ẹni òtítọ́ àti ènìyàn búburú pẹ̀lú.’
Be kâvan doeh. Hat dawk nahoehmaw, tamikathoutnaw hoi toun han kaawm hoeh e hoi, be raphoe han telah ka dei vaw.
23 Bí ìjàǹbá bá pa ni lójijì, yóò rẹ́rìn-ín nínú ìdààmú aláìṣẹ̀.
Hemnae ni vai touh hoi thet boipawiteh, kayonhoehe khangnae teh, a panuikhai han.
24 Nígbà tí a bá fi ayé lé ọwọ́ ènìyàn búburú; ó sì bo àwọn onídàájọ́ rẹ̀ lójú; bí kò bá rí bẹ́ẹ̀ ǹjẹ́ ta ni?
Talai heh tamikathout e kut dawk poe lah ao teh, a lawkcengkungnaw e minhmai a ramuk. Ahni hoehpawiteh, api han na maw.
25 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí ọjọ́ mi yára ju oníṣẹ́ lọ, wọ́n fò lọ, wọn kò rí ayọ̀.
Ka hninnaw hateh, ka yawng e hlak hai hoe a rang, a kamleng awh teh, hawinae hmawt awh hoeh.
26 Wọ́n kọjá lọ bí ọkọ̀ eèsún papirusi tí ń sáré lọ; bí idì tí ń yára si ohùn ọdẹ.
Karang poung e lawng patetlah a khup teh, Mataw ni moithang a ka cawp e patetlah a rang.
27 Bí èmi bá wí pé, ‘Èmi ó gbàgbé arò ìbìnújẹ́ mi, èmi ó fi ọkàn lélẹ̀, èmi ó sì rẹ ara mi lẹ́kún.’
Ka phuenangnae ka pahnim vaiteh, ka lungmathoenae minhmai he ka ta vaiteh, minhmai kapancala ka o han ka ti navah,
28 Ẹ̀rù ìbànújẹ́ mi gbogbo bà mí, èmi mọ̀ pé ìwọ kì yóò mú mi bí aláìṣẹ̀.
Ka khangnae naw pueng heh, makkhak ka taki teh, tamikayon hoeh e lah na pouk hoeh langvaih tie hah ka panue.
29 Bí ó bá ṣe pé ènìyàn búburú ni èmi, ǹjẹ́ kí ni èmi ń ṣe làálàá lásán sí?
Yon pen e lah kaawm pawiteh, bangdawkmaw ahrawnghrang e meng ka tawk han.
30 Bí mo tilẹ̀ fi ọṣẹ dídì wẹ ara mi, tí mo fi omi aró wẹ ọwọ́ mi mọ́,
Tadamtui hoi ka kamhluk nakunghai, ka kut heh sapet hoi ka kamsin nakunghai,
31 síbẹ̀ ìwọ ó gbé mi wọ inú ihò ọ̀gọ̀dọ̀ aṣọ ara mi yóò sọ mi di ìríra.
tangdong dawk na tâkhawng teh, ka khohna ni patenghai na panuet han doeh.
32 “Nítorí Òun kì í ṣe ènìyàn bí èmi, tí èmi ó fi dá a lóhùn tí àwa o fi pàdé ní ìdájọ́.
Bangkongtetpawiteh, lawkcengnae koe rei cet vaiteh, ama teh ka pathung thai nahanelah, ama teh tami lah tho hoeh.
33 Bẹ́ẹ̀ ni kò sí alátúnṣe kan ní agbede-méjì wa tí ìbá fi ọwọ́ rẹ̀ lé àwa méjèèjì lára.
Maimouh roi e van kut ka toung hanelah, maimae rahak laicei awm hoeh.
34 Kí ẹnìkan sá à mú ọ̀pá Ọlọ́run kúrò lára mi, kí ìbẹ̀rù rẹ̀ kí ó má sì ṣe dáyà fò mí.
Kai koe e sonron lat naseh taki a thonae ni na taket sak hanh seh.
35 Nígbà náà ni èmi ìbá sọ̀rọ̀, èmi kì bá sì bẹ̀rù rẹ̀; ṣùgbọ́n bí ó tí dúró tì mí, kò ri bẹ́ẹ̀ fún mi.
Hatdawkvah ama taket laipalah lawk hah ka dei han. Hateiteh, kai koevah hottelah bout awm kalawn hoeh.

< Job 9 >