< Job 8 >

1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, sì dáhùn wí pé,
Nake Bilidadi ũrĩa Mũshuhi agĩcookia, akĩũria atĩrĩ:
2 “Ìwọ yóò ti máa sọ nǹkan wọ̀nyí pẹ́ tó? Tí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ yóò sì máa bí ẹ̀fúùfù ńlá?
“Nĩ nginya rĩ ũgũikara ũkĩaragia maũndũ ta macio? Ciugo ciaku no ta inegene rĩa rũhuho rũkĩhurutana.
3 Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí? Tàbí Olódùmarè a máa gbé ẹ̀bi fún aláre?
Mũrungu-rĩ, nĩogomagia ciira wa kĩhooto? Ũcio Mwene-Hinya-Wothe nĩogomagia ũndũ ũrĩa ũrĩ wa ma?
4 Nígbà tí àwọn ọmọ rẹ̀ ṣẹ̀ sí i, ó sì gbá wọn kúrò nítorí ìrékọjá wọn.
Rĩrĩa ciana ciaku ciamwĩhĩirie-rĩ, nĩacirekereirie iherithio nĩ ũndũ wa mehia ma cio.
5 Bí ìwọ bá sì ké pe Ọlọ́run ní àkókò, tí ìwọ sì gbàdúrà ẹ̀bẹ̀ sí Olódùmarè.
No rĩrĩ, wee ũngĩcũthĩrĩria Mũrungu na wĩthaithanĩrĩre harĩ Ũcio Mwene-Hinya-Wothe,
6 Ìwọ ìbá jẹ́ mímọ, kí ó sì dúró ṣinṣin: ǹjẹ́ nítòótọ́ nísinsin yìí òun yóò tají fún ọ, òun a sì sọ ibùjókòó òdodo rẹ di púpọ̀.
ũngĩkorwo ũrĩ mũtheru na mũrũngĩrĩru-rĩ, o na rĩu no arahũke nĩ ũndũ waku nĩguo agũcookie handũ harĩa hakwagĩrĩire.
7 Ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ ìbá tilẹ̀ kéré si í, bẹ́ẹ̀ ìgbẹ̀yìn rẹ ìbá pọ̀ sí i gidigidi.
O na gũtuĩka kĩambĩrĩria gĩaku no kĩoneke kĩrĩ kĩnini, thuutha-inĩ nĩũkagaacĩra mũno.
8 “Èmi bẹ̀ ọ́ ǹjẹ́, béèrè lọ́wọ́ àwọn ará ìgbà nì kí o sì kíyèsi ìwádìí àwọn baba wọn.
“Ũria ũhoro harĩ njiarwa cia tene, na ũtuĩrie maũndũ marĩa maithe mao meerutire,
9 Nítorí pé ọmọ-àná ni àwa, a kò sì mọ nǹkan, nítorí pé òjìji ni ọjọ́ wa ni ayé.
nĩgũkorwo ithuĩ tũraciarirwo o ro ira na tũtirĩ ũndũ tũũĩ, namo matukũ maitũ ma gũikara gũkũ thĩ no ta kĩĩruru.
10 Àwọn kì yóò wa kọ ọ́, wọn kì yóò sì sọ fún ọ? Wọn kì yóò sì sọ̀rọ̀ láti inú òye wọn jáde wá?
Acio githĩ to makũrute na makũhe ũhoro? Acio githĩ to maarie ũhoro marĩ na ũmenyo?
11 Papirusi ha lè dàgbà láìní ẹrẹ̀ tàbí eèsún ha lè dàgbà láìlómi?
Irura-rĩ, no rĩkũre handũ hatarĩ itomboya? Ithanjĩ-rĩ, no rĩtheereme handũ hatarĩ maaĩ?
12 Nígbà tí ó wà ní tútù, tí a kò ké e lulẹ̀, ó rọ dànù, ewéko gbogbo mìíràn hù dípò rẹ̀.
Rĩngĩkũrĩra handũ hatarĩ maaĩ rĩũmaga narua gũkĩra nyeki, o na rĩtakinyĩte rĩa gũtuuo.
13 Bẹ́ẹ̀ ni ipa ọ̀nà gbogbo àwọn tí ó gbàgbé Ọlọ́run, bẹ́ẹ̀ ni ìrètí àwọn àgàbàgebè yóò di òfo.
Ũcio nĩguo mũthia wa arĩa othe mariganagĩrwo nĩ Mũrungu; ũguo no ta guo mwĩhoko wa arĩa matooĩ Ngai ũthiraga.
14 Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò, àti ìgbẹ́kẹ̀lé ẹni tí ó dàbí ilé aláǹtakùn.
Kĩrĩa ehokete no kĩndũ kĩhũthũ; kĩrĩa egiritanagia nakĩo no ta rũrenda rwa mbũmbũĩ.
15 Yóò fi ara ti ilé rẹ̀, ṣùgbọ́n kì yóò lè dúró, yóò fi di ara rẹ̀ mú ṣinṣin ṣùgbọ́n kì yóò lè dúró pẹ́.
Etiiranagia na rũrenda rwake, naruo rũgatuĩka; akenyiitĩrĩra harĩ ruo, no rũtingĩmũtiirĩrĩra.
16 Ó tutù bí irúgbìn tí a bomirin níwájú oòrùn, ẹ̀ka rẹ̀ sì yọ jáde nínú ọgbà rẹ̀.
Ahaana ta mũtĩ ũitĩrĩirio maaĩ wega ũrĩ riũa-inĩ, ũtambũrũkĩtie thuuna ciaguo mũgũnda-inĩ;
17 Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká, ó sì wó ibi òkúta wọ̀n-ọn-nì.
mĩri yaguo ĩĩthiororokeirie kĩhumbu kĩa mahiga, na ĩcaragia ha kwĩgwatĩrĩra rwaro-inĩ rwa mahiga.
18 Bí ó bá sì pa á run kúrò ní ipò rẹ̀, nígbà náà ni ipò náà yóò sọ, ‘Èmi kò ri ọ rí!’
No rĩrĩa wakũũrwo harĩa ũraarĩ-rĩ, handũ hau hagakaana mũtĩ ũcio, hakoiga atĩrĩ, ‘Niĩ ndirĩ ndakuona.’
19 Kíyèsi i, ayé rẹ̀ gbẹ dànù àti láti inú ilẹ̀ ní irúgbìn òmíràn yóò hù jáde wá.
Ti-itherũ muoyo waguo ũmaga ũgathira, naho hau tĩĩri-inĩ ũcio hagakũra mĩtĩ ĩngĩ.
20 “Kíyèsi i, Ọlọ́run kì yóò ta ẹni òtítọ́ nù, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ran oníwà búburú lọ́wọ́
“Ti-itherũ Mũrungu ndangĩrega mũndũ ũtarĩ ũcuuke, kana ekĩre moko ma arĩa mekaga ũũru hinya.
21 títí yóò fi fi ẹ̀rín kún ọ ní ẹnu, àti ètè rẹ pẹ̀lú ìhó ayọ̀,
Na rĩrĩ, no arĩiyũria kanua gaku mĩtheko, nayo mĩromo yaku yanĩrĩre nĩ gũkena.
22 ìtìjú ní a o fi bo àwọn tí ó kórìíra rẹ̀, àti ibùjókòó ènìyàn búburú kì yóò sí mọ́.”
Thũ ciaku nĩikahumbwo thoni, nacio hema cia arĩa aaganu itigacooka kuonwo.”

< Job 8 >