< Job 7 >
1 “Ṣé ìjà kò ha si fún ènìyàn lórí ilẹ̀? Ọjọ́ rẹ̀ pẹ̀lú kò ha dàbí ọjọ́ alágbàṣe?
Osobo bagade dunu ea esalusu da sesesu dadi gagui dunu ea hawa: hamosu defele amola udigili gasa bagade hawa: hamosu agoane.
2 Bí ọmọ ọ̀dọ̀ tí máa ń kánjú bojú wo òjìji, àti bí alágbàṣe ti í kánjú wo ọ̀nà owó iṣẹ́ rẹ̀.
Ea esalusu da udigili hawa: hamosu dunu amo da anegagima: ne, ifa ougiha esalumusa: hanai gala. Ea esalusu da hamosu dunu amo da ea bidi lama: ne, hanaiwane ouesalebe ba: sa.
3 Bẹ́ẹ̀ ni a mú mi ní ìbànújẹ́ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ oṣù, òru ìdáni-lágara ni a sì là sílẹ̀ fún mi.
Oubi uduli, eno uduli, na da udigili se nabawane esala. Na bu esaloma: ne da bai hame gala. Gasili asili bu eno gasili, na da da: i dioi fawane ba: sa.
4 Nígbà ti mo dùbúlẹ̀, èmi wí pé, ‘Nígbà wo ni èmi ó dìde?’ Tí òru yóò sì kọjá, ó sì tó fún mi láti yí síyìn-ín yí sọ́hùn-ún, títí yóò fi di àfẹ̀mọ́júmọ́.
Na da golai be sidagane esala. Gasi huluane na da sidagane gilala, soge hedolo hadigima: ne dawa: lala.
5 Kòkòrò àti ògúlùtu erùpẹ̀ ni á fi wọ̀ mi ni aṣọ, awọ ara mi bù, o sì di bíbàjẹ́.
Na da: i da fioso amoga nabai. Na da: i da aiya heheya: amoga dedeboi dagoi. Na aiya amoga guhi da daha.
6 “Ọjọ́ mi yára jù ọkọ̀ ìhunṣọ lọ, o sì di lílò ní àìní ìrètí.
Na da hobea misunu dafawane hamoma: beyale dawa: lusu hamedene, eso da hedolowane hehenasa.
7 Háà! Rántí pé afẹ́fẹ́ ni ẹ̀mí mi; ojú mi kì yóò padà rí rere mọ́.
Gode! Mae gogolema! Na esalusu da mifo lai afadafa fawane agoai gala. Na hahawane hou da fisi dagoi.
8 Ojú ẹni tí ó rí mi, kì yóò rí mi mọ́; ojú rẹ̀ tẹ̀ mọ́ra mi, èmi kò sí mọ́.
Dia da wahadafa na ba: sa. Be hobea bu hamedafa ba: mu. Dia na hogosea, na da asi dagoi ba: mu.
9 Bí ìkùùkuu tí i túká, tí í sì fò lọ, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń lọ sí ipò òkú tí kì yóò padà wa mọ́. (Sheol )
10 Kì yóò padà sínú ilé rẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀ ní ipò rẹ̀ kì yóò mọ̀ ọn mọ́.
Mu mobi da ba: lalu, hedolowane gilasi dagoi ba: sa. Amo defele, ninia osobo bagade dunu da bogosea, hame buhagisa. Nini dawa: su dunu, ilia da nini hedolo gogolesa. (Sheol )
11 “Nítorí náà èmi kì yóò pa ẹnu mi mọ́, èmi yóò máa sọ nínú ìrora ọkàn mi, èmi yóò máa ṣe ìráhùn nínú kíkorò ọkàn mi.
Hame mabu! Na da hamedafa ouiya: mu! Na da ougi amola gia: i bagade gala. Na da sia: mu!
12 Èmi a máa ṣe Òkun tàbí ẹ̀mí búburú, tí ìwọ fi ń yan olùṣọ́ tì mi?
Gode! Dia da abuliba: le na sosodo aligisala: ? Na da wayabo bagade wadela: i ohe bagade, Dia da dawa: sala: ?
13 Nígbà tí mo wí pé, ibùsùn mi yóò tù mí lára, ìtẹ́ mi yóò mú ara mi fúyẹ́ pẹ̀lú.
Na da helefimusa: diala be golamu hamedei. Na da na se nabasu fisima: ne, logo hogosa.
14 Nígbà náà ni ìwọ fi àlá da yọ mi lénu bò mi, ìwọ sì fi ìran òru dẹ́rùbà mí.
Be Dia da na beda: ma: ne simasia olelesa. Dia da na esala ba: la: lusu amola wadela: i simasia ba: su nama iasisa.
15 Bẹ́ẹ̀ ni ọkàn mí yàn láti fún pa àti ikú ju kí ń wà láààyè ní ipò tí ara mí wà yìí lọ.
Amaiba: le, na da na da: i ganodini bu esalumu higasa. Dunu eno da na galogoa gaguli, na fane legemu da defea gala.
16 O sú mi, èmi kò le wà títí: jọ̀wọ́ mi jẹ́, nítorí pé asán ni ọjọ́ mi.
Na da yolesimu galebe. Na da esalumu higasa. Dia na yolesima! Na esalusu da bai hamedafa gala.
17 “Kí ni ènìyàn tí ìwọ o máa kókìkí rẹ̀? Àti tí ìwọ ìbá fi gbé ọkàn rẹ lé e?
Dia abuliba: le osobo bagade dunu da mimogoayale dawa: sala: ? Dia abuliba: le ilia hamobe sosodolalala: ?
18 Àti ti ìwọ ó fi máa wá í bẹ̀ ẹ́ wò ni òròòwúrọ̀, ti ìwọ o sì máa dán an wò nígbàkígbà!
Dia da hahabe huluane ili abodelala. Dia da mae fisili ilima adoba: lala.
19 Yóò ti pẹ́ tó kí ìwọ kí ó tó fi mí sílẹ̀ lọ, tí ìwọ o fi mí sílẹ̀ jẹ́ẹ́ títí èmi yóò fi lè dá itọ́ mi mì.
Na defo hano ni da: gima: ne, Di da nama sosodobe fonobahadi yolesimu da defea gala.
20 Èmi ti ṣẹ̀, ki ní èmi ó ṣe sí ọ. Ìwọ Olùsójú ènìyàn? Èéṣe tí ìwọ fi fi mí ṣe àmì itasi níwájú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni èmi sì di ẹrẹ̀ wíwo fún ọ?
Di da nama se iasu diasu ouligisu dunu agoai gala. Na wadela: i hou da Dima se iahabela: ? Dia da abuliba: le, dimaga: su adoba: ma: ne, nama dadiga dimaga: sala: ? Na da Dima dioi bagade gaguli ahoabe liligila: ?
21 Èéṣe tí ìwọ kò sì dárí ìrékọjá mi jìn, kí ìwọ kí ó sì mú àìṣedéédéé mi kúrò? Ǹjẹ́ nísinsin yìí ni èmi ìbá sùn nínú erùpẹ̀, ìwọ ìbá sì wá mi kiri ní òwúrọ̀, èmi kì bá tí sí.”
Dia da na wadela: i hou hamedafa gogolema: ne olofoma: bela: ? Dia da na wadela: i hamobe amo gogolema: ne olofomu hamedei ba: sala: ? Na da hedolowane bogole, uli dogoi ganodini sali ba: mu. Amola, Dia na hogole ba: sea, na da asi dagoi ba: mu.”