< Job 40 >

1 Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,
Korero mai ano a Ihowa ki a Hopa, i mea,
2 “Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́? Ẹni tí ń bá Ọlọ́run wí jẹ́ kí ó dáhùn!”
E tohe ana ranei ki te Kaha Rawa te tangata whakatohutohu? Ma te tangata e whakatupehupehu ana ki te Atua, mana e korero mai.
3 Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,
Ano ra ko Hopa ki a Ihowa; i mea ia,
4 “Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.
Nana, ehara noa iho ahau. Ko te aha taku e whakahoki atu ai ki a koe? Ka kopania toku ringa ki toku mangai.
5 Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́; lẹ́ẹ̀kejì ni, èmi kò sì le ṣe é mọ́.”
Kua kotahi taku koreotanga, a e kore ahau e whakahoki kupu atu; a tuarua rawa, otira kahore atu aku.
6 Nígbà náà ní Olúwa dá Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká wá, ó sì wí pé,
Katahi ka whakahokia mai e Ihowa ki a Hopa i roto i te tukauati, ka mea,
7 “Di àmùrè gírí ní ẹgbẹ́ rẹ bí ọkùnrin, èmi ó bi ọ léèrè, kí ìwọ kí ó sì dá mi lóhùn.
Tena ra, whakatane, whitikiria tou hope, a ka ui atu ahau ki a koe, mau ano e whakaatu mai ki ahau.
8 “Ìwọ ha fẹ́ mú ìdájọ́ mi di asán? Ìwọ ó sì dá mi lẹ́bi, kí ìwọ lè ṣe olódodo.
Me whakakahore ano ranei e koe taku whakawa? Me whakahe ki ahau kia whakatikaia ai tau?
9 Ìwọ ni apá bí Ọlọ́run tàbí ìwọ lè fi ohùn sán àrá bí òun?
He ringa pera ranei tou i to te Atua? He reo whatitiri ranei tou, he pera i tona?
10 Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ní ọ̀ṣọ́, tí ó sì fi ògo àti títóbi ọ̀ṣọ́ bo ara ní aṣọ.
Tena ra, rakai i a koe inaianei ki te rangatiratanga, ki te kororia; tatai i a koe ki te honore, ki te mana.
11 Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde; kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ kí o sì rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
Ringihia atu te puhaketanga o tou riri; tirohia atu nga mea whakakake katoa, whakaititia iho.
12 Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn kí o sì rẹ ẹ sílẹ̀ kí o sì tẹ ènìyàn búburú mọ́lẹ̀ ní ipò wọn.
Titiro atu ki nga mea whakakake katoa, whakapikoa iho; takahia iho ano hoki te hunga kino i te wahi e tu na ratou.
13 Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀, kí o sì di ojú ìkọ̀kọ̀ wọn ní isà òkú.
Huihuia atu ratou, huna ki te puehu, herea o ratou mata ki te wahi ngaro.
14 Nígbà náà ní èmi ó yìn ọ́ pé, ọwọ́ ọ̀tún ara rẹ lè gbà ọ́ là.
Na ko reira ahau whakaae ai ki a koe, ma tou ringa matau ano koe e whakaora.
15 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti, tí mo dá pẹ̀lú rẹ, òun a máa jẹ koríko bí ọ̀dá màlúù.
Na whakaaroa a Pehemoto, he mea hanga ngatahi korua naku; e kai ra i te tarutaru, ano he kau.
16 Wò o nísinsin yìí, agbára rẹ wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, àti ipa rẹ nínú ìṣàn ìkún rẹ.
Nana, ko tona kaha kei tona hope, ko tona pakaritanga kei nga uaua o tona kopu.
17 Òun a máa jù ìrù rẹ̀ bí i igi kedari, iṣan itan rẹ̀ dìjọ pọ̀.
Ko tona hiawero, ano he hita e tawhiria ana e ia: powhiwhiwhi tonu nga uaua o tona huha.
18 Egungun rẹ̀ ní ògùṣọ̀ idẹ, Egungun rẹ̀ dàbí ọ̀pá irin.
Ko ona wheua, ano he korere parahi; ko ona rara, he poro rino.
19 Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run; síbẹ̀ Ẹlẹ́dàá rẹ̀ fi idà rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Ko ia te tino mea nui o nga ara o te Atua: ko tona kaihanga anake hei whakapa i tana hoari ki a ia.
20 Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá ní i mu ohun jíjẹ fún un wá, níbi tí gbogbo ẹranko igbó máa ṣiré ní ẹ̀gbẹ́ ibẹ̀.
He pono ko nga maunga hei homai kai mana; kei reira ano e takaro ana nga kirehe katoa o te parae.
21 Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì, lábẹ́ eèsún àti ẹrẹ̀.
Ko tona takotoranga ko raro i nga rakau kouru nui, i te rake kakaho, i te repo.
22 Igi lótusì síji wọn bò o; igi arọrọ odò yí i káàkiri.
Hei taupoki mona te whakamarumaru o nga rakau kouru nui, kei tetahi taha ona, kei tetahi taha, nga wirou o te awa.
23 Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun kò sálọ; ó wà láìléwu bí ó bá ṣe pé odò Jordani ti ṣàn lọ sí ẹnu rẹ̀.
Nana, ki te aki mai te waipuke, e kore ia e tuiri; u tonu tona whakaaro, ahakoa kokiri noa mai a Horano ki tona mangai.
24 Ẹnìkan ha lè mú un ní ojú rẹ̀, tàbí dẹkùn fún tàbí a máa fi ọ̀kọ̀ gún imú rẹ̀?
E hopukia ranei ia e tetahi i a ia e mataara ana, e poka ranei i tona ihu ki te rore, puta noa?

< Job 40 >