< Job 40 >

1 Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,
A tak odpovídaje Hospodin Jobovi, řekl:
2 “Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́? Ẹni tí ń bá Ọlọ́run wí jẹ́ kí ó dáhùn!”
Zdali hádající se s Všemohoucím obviní jej? Kdo chce viniti Boha, nechť odpoví na to.
3 Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,
Tehdy odpověděl Job Hospodinu a řekl:
4 “Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.
Aj, chaternýť jsem, což bych odpovídal tobě? Ruku svou kladu na ústa svá.
5 Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́; lẹ́ẹ̀kejì ni, èmi kò sì le ṣe é mọ́.”
Jednou jsem mluvil, ale nebudu již odmlouvati, nýbrž i podruhé, ale nebudu více přidávati.
6 Nígbà náà ní Olúwa dá Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká wá, ó sì wí pé,
Ještě odpovídaje Hospodin z vichru Jobovi, i řekl:
7 “Di àmùrè gírí ní ẹgbẹ́ rẹ bí ọkùnrin, èmi ó bi ọ léèrè, kí ìwọ kí ó sì dá mi lóhùn.
Přepaš nyní jako muž bedra svá, a nač se tebe tázati budu, oznam mi.
8 “Ìwọ ha fẹ́ mú ìdájọ́ mi di asán? Ìwọ ó sì dá mi lẹ́bi, kí ìwọ lè ṣe olódodo.
Zdaliž pak i soud můj zrušiti chceš? Což mne odsoudíš, jen abys se sám ospravedlnil?
9 Ìwọ ni apá bí Ọlọ́run tàbí ìwọ lè fi ohùn sán àrá bí òun?
Èili máš rámě jako Bůh silný, a hlasem jako on hřímáš?
10 Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ní ọ̀ṣọ́, tí ó sì fi ògo àti títóbi ọ̀ṣọ́ bo ara ní aṣọ.
Ozdobiž se nyní vyvýšeností a důstojností, v slávu a okrasu oblec se.
11 Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde; kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ kí o sì rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
Rozprostři prchlivost hněvu svého, a pohleď na všelikého pyšného, a sniž ho.
12 Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn kí o sì rẹ ẹ sílẹ̀ kí o sì tẹ ènìyàn búburú mọ́lẹ̀ ní ipò wọn.
Pohleď, pravím, na všelikého pyšného, a sehni jej, anobrž setři bezbožné na místě jejich.
13 Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀, kí o sì di ojú ìkọ̀kọ̀ wọn ní isà òkú.
Skrej je v prachu spolu, tvář jejich zavěž v skrytě.
14 Nígbà náà ní èmi ó yìn ọ́ pé, ọwọ́ ọ̀tún ara rẹ lè gbà ọ́ là.
A tak i já budu tě oslavovati, že tě zachovává pravice tvá.
15 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti, tí mo dá pẹ̀lú rẹ, òun a máa jẹ koríko bí ọ̀dá màlúù.
Aj, hle slon, jejž jsem jako i tebe učinil, trávu jí jako vůl.
16 Wò o nísinsin yìí, agbára rẹ wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, àti ipa rẹ nínú ìṣàn ìkún rẹ.
Aj, hle moc jeho v bedrách jeho, a síla jeho v pupku břicha jeho.
17 Òun a máa jù ìrù rẹ̀ bí i igi kedari, iṣan itan rẹ̀ dìjọ pọ̀.
Jak chce, ohání ocasem svým, ačkoli jest jako cedr; žily lůna jeho jako ratolesti jsou spletené.
18 Egungun rẹ̀ ní ògùṣọ̀ idẹ, Egungun rẹ̀ dàbí ọ̀pá irin.
Kosti jeho jako trouby měděné, hnátové jeho jako sochor železný.
19 Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run; síbẹ̀ Ẹlẹ́dàá rẹ̀ fi idà rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Onť jest přední z účinků Boha silného, učinitel jeho sám na něj doložiti může meč svůj.
20 Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá ní i mu ohun jíjẹ fún un wá, níbi tí gbogbo ẹranko igbó máa ṣiré ní ẹ̀gbẹ́ ibẹ̀.
Hory zajisté přinášejí mu pastvu, a všecka zvěř polní hrá tam.
21 Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì, lábẹ́ eèsún àti ẹrẹ̀.
V stínu léhá, v soukromí mezi třtím a bahnem.
22 Igi lótusì síji wọn bò o; igi arọrọ odò yí i káàkiri.
Dříví stín dávající stínem svým jej přikrývá, a vrbí potoční obkličuje jej.
23 Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun kò sálọ; ó wà láìléwu bí ó bá ṣe pé odò Jordani ti ṣàn lọ sí ẹnu rẹ̀.
Aj, zadržuje řeku tak, že nemůže pospíchati; tuší sobě, že požře Jordán v ústa svá.
24 Ẹnìkan ha lè mú un ní ojú rẹ̀, tàbí dẹkùn fún tàbí a máa fi ọ̀kọ̀ gún imú rẹ̀?
Zdaž kdo před očima jeho polapí jej, aneb provazy protáhne chřípě jeho?

< Job 40 >