< Job 4 >

1 Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani dáhùn wí pé,
Ilaifa: se da amane sia: i,
2 “Bí àwa bá fi ẹnu lé e, láti bá ọ sọ̀rọ̀, ìwọ o ha banújẹ́? Ṣùgbọ́n ta ni ó lè pa ọ̀rọ̀ mọ́ ẹnu láìsọ?
“Yoube! Na da dima sia: sea, di da ougima: bela: ? Na bu ouiya: mu hamedei ba: sa!
3 Kíyèsi i, ìwọ sá ti kọ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn, ìwọ ṣá ti mú ọwọ́ aláìlera le.
Di da dunu bagohame ilima olelesu. Di da dunu bagohame, ili gasa lama: ne fidisu.
4 Ọ̀rọ̀ rẹ ti gbé àwọn tí ń ṣubú lọ dúró, ìwọ sì ti mú eékún àwọn tí ń wárìrì lera.
Dunu afae da helebeba: le goaiyane didigabone dafaloba, dia sia: beba: le, e da dogo denesini, aligi.
5 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ó dé bá ọ, ó sì rẹ̀ ọ́, ó kọlù ọ́; ara rẹ kò lélẹ̀.
Be wali bidi hamosu da dima doaga: i, amola di da amoga gasa fili mae aligili sidadabonei agoai ba: sa.
6 Ìbẹ̀rù Ọlọ́run rẹ kò ha jẹ́ ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ àti ìdúró ọ̀nà rẹ kò ha sì jẹ́ ìrètí rẹ?
Di da Godema nodone sia: sa hawa: hamosu, amola dia esalusu amo ganodini dima sia: i afae hame fada: su, amaiba: le di da dia dafawane hamoma: beyale dawa: su amoga ga: nasili aligimu da defea.
7 “Èmi bẹ̀ ọ́ rántí, ta ni ó ṣègbé rí láìṣẹ̀? Tàbí níbo ni a gbé gé olódodo kúrò rí?
Waha bu sinidigili, musa: hamosu dawa: ma! Nowa da moloidafa hou hamoi, be e da baligiliwane se nabasu ba: bela: ? Agoaiwane hame ba: su.
8 Àní bí èmi ti rí i pé, àwọn tí ń ṣe ìtulẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀, tí wọ́n sì fún irúgbìn ìwà búburú, wọn a sì ká èso rẹ̀ náà.
Na da ba: loba, dunu ilia wadela: i hou fawane hawa: agoane bugimusa: dawa: lala. Be waha ilia da wadela: i hou bugi gamisu agoane gugunufinisisu hou ba: sa.
9 Nípa ìfẹ́ sí Ọlọ́run wọn a ṣègbé, nípa èémí ìbínú rẹ̀ wọn a parun.
Gode da amo wadela: i hamosu dunuma ougi bagadeba: le, E da mulu bagade defele ili wadela: lesisa.
10 Bíbú ramúramù kìnnìún àti ohùn òǹrorò kìnnìún àti eyín àwọn ẹgbọrọ kìnnìún ní a ká.
Wadela: i hou hamosu dunu ilia da laione wa: me agoane husa amola hagega: sa. Be Gode da ili ouiya: lesisa amola ilia bese gugulisisa.
11 Kìnnìún kígbe, nítorí àìrí ohun ọdẹ, àwọn ẹgbọrọ kìnnìún sísanra ni a túká kiri.
Ilia da laione wa: me amo da ohe fane manu hamedei ba: sa, amola ha: i manu hame galea, bogobe, amo defele bogogia: sa. Ilia da bogosea, ilia mano huluane da afagogosa.
12 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí a fi ohun àṣírí kan hàn fún mi, etí mi sì gbà díẹ̀ nínú rẹ̀.
Eso afaega, sia: nama misi da ouiya: lewane nama mabeba: le, na da fada: ne hame nabi.
13 Ní ìrò inú lójú ìran òru, nígbà tí oorun èjìká kùn ènìyàn.
Amo sia: da golaiya wadela: i liligi agoai ba: beba: le amoga na da fofogadigili nedigi.
14 Ẹ̀rù bà mí àti ìwárìrì tí ó mú gbogbo egungun mi jí pépé.
Na da fofogadigili, beda: ga, na da: i huluane yagugui.
15 Nígbà náà ni ẹ̀mí kan kọjá lọ ní iwájú mi, irun ara mi dìde dúró ṣánṣán.
Fo hisi da na odagia fogala: le, na da beda: ga, na dialuma hinabo afafai.
16 Ó dúró jẹ́ẹ́, ṣùgbọ́n èmi kò le wo àpẹẹrẹ ìrí rẹ̀, àwòrán kan hàn níwájú mi, ìdákẹ́rọ́rọ́ wà, mo sì gbóhùn kan wí pé,
Na da liligi afae lelebe ba: i, be na da sosodolaligi, be amo liligi na fada: ne hame dawa: i galu. Eno liligi da ouiya: le dialebe ba: i. Amalalu, na da amane sia: be nabi,
17 ‘Ẹni kíkú le jẹ́ olódodo ju Ọlọ́run, ènìyàn ha le mọ́ ju ẹlẹ́dàá rẹ̀ bí?
“Dunu afae da Gode Ea ba: ma: ne moloidafa esalabala? Dunu afae da Osobo Bagade Hahamosu Ea ba: ma: ne ledo hamedei esalabala?
18 Kíyèsi i, òun kò gbẹ́kẹ̀lé àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, nínú àwọn angẹli rẹ̀ ní ó sì rí ẹ̀ṣẹ̀.
Gode da Hebene ganodini hawa: hamosu dunu, ilia da Ea liligi noga: le ouligima: ne hame ilegesa. E da Ea a: igele dunu amolawane ilima giadofasu hou ba: sa.
19 Mélòó mélòó àwọn tí ń gbé inú ilé amọ̀, ẹni tí ìpìlẹ̀ wọ́n jásí erùpẹ̀ tí yóò di rírun kòkòrò.
Amaiba: le, dia dawa: loba Gode da osoboga hamoi dunu amo Ea liligi noga: le ouligima: ne ilegema: bela: ? Hame mabu! Bai osobo bagade dunu da guluga hamoiba: le, aowaba defele hedolo gagoudai dagoi ba: sa.
20 A pa wọ́n run láàrín òwúrọ̀ àti àṣálẹ́ wọ́n sì parun títí láé, láìrí ẹni kà á sí.
Amabela: ? Ninia da hahabe esalebe ba: sa, be mae daeyagili, bogoi dagoi ba: mu.
21 A kò ha ké okùn iye wọ́n kúrò bí? Wọ́n kú, àní láìlọ́gbọ́n?’
Ninia gagui huluane da bu sasamogene dagoi ba: mu. Ninia asigi dawa: su hame fada: iyawane bogosa.”

< Job 4 >