< Job 39 >

1 “Ìwọ mọ àkókò ìgbà tí àwọn ewúrẹ́ orí àpáta ń bímọ? Ìwọ sì lè kíyèsi ìgbà tí abo àgbọ̀nrín ń bímọ?
“Wee nĩũũĩ rĩrĩa mbũri cia irĩma-inĩ iciaraga? Wee nĩwĩroragĩra rĩrĩa thwariga ĩgũciara kaana kayo?
2 Ìwọ lè ka iye òṣùpá tí wọn ń pé, ìwọ sì mọ àkókò ìgbà tí wọn ń bímọ.
Wee nĩũtaraga mĩeri ĩrĩa ciikaraga ingĩgaaciara? Nĩũũĩ hĩndĩ ĩrĩa iciaraga?
3 Wọ́n tẹ ara wọn ba, wọ́n bímọ, wọ́n sì mú ìkáàánú wọn jáde.
Ciĩthunaga igaciara twana twacio; ruo rwacio rwa gũciara rũgathira.
4 Àwọn ọmọ wọn rí dáradára, wọ́n dàgbà nínú ọ̀dàn; wọ́n jáde lọ, wọn kò sì tún padà wá sọ́dọ̀ wọn.
Twana twacio twagĩraga mwĩrĩ, tũgakũra tũrĩ na hinya o kũu gĩthaka-inĩ; tũkinyaga ihinda rĩa kwehera na tũticookaga.
5 “Ta ni ó jọ̀wọ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ oko lọ́wọ́? Tàbí ta ní ó tú ìdè kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó,
“Nũũ warekereirie njagĩ ĩthiiage ĩtarĩ mũũria? Nũũ wamĩohorire mĩhĩndo?
6 èyí tí mo fi aginjù ṣe ilé fún, àti ilẹ̀ iyọ̀ ní ibùgbé rẹ̀.
Ndaamĩheire werũ ũtuĩke mũciĩ wayo, naguo bũrũri wa cumbĩ ũtuĩke gĩtũũro kĩayo.
7 Ó rẹ́rìn-ín sí ariwo ìlú, bẹ́ẹ̀ ni òun kò sì gbọ́ igbe darandaran.
Ĩthekagĩrĩra inegene rĩrĩ thĩinĩ wa itũũra; ndĩiguaga mũkaĩrĩrio wa mũtwarithia.
8 Orí àtòlé òkè ńlá ni ibùjẹ oko rẹ̀, òun a sì máa wá ewé tútù gbogbo rí.
Ĩrimũthagĩra irĩma-inĩ ĩgĩetha gwa kũrĩa, ĩkahaara kahuti o gothe karuru.
9 “Àgbáǹréré ha jẹ́ sìn ọ́ bí? Tàbí ó jẹ́ dúró ní ibùjẹ ẹran rẹ ní òru?
“Mbogo ya njamba-rĩ, yetĩkĩra gũgũtungata? No ĩkindĩrie mũharatĩ-inĩ waku ũtukũ?
10 Ìwọ le fi òkun tata de àgbáǹréré nínú aporo? Tàbí ó jẹ́ máa fa ìtulẹ̀ nínú aporo oko tọ̀ ọ́ lẹ́yìn?
No ũhote kũmĩoha matandĩko ĩrĩme na mũraũ? No ĩkuume thuutha ituamba-inĩ ĩkĩrĩmaga na mũraũ?
11 Ìwọ ó gbẹ́kẹ̀lé e nítorí agbára rẹ̀ pọ̀? Ìwọ ó sì fi iṣẹ́ rẹ lé e lọ́wọ́?
No ũmĩĩhoke nĩ ũndũ atĩ ĩrĩ na hinya mũingĩ? No ũmĩtigĩre wĩra waku mũritũ ĩrutage?
12 Ìwọ le gbẹ́kẹ̀lé pé, yóò mú èso oko rẹ̀ wá sílé, àti pé yóò sì kó ọ jọ sínú àká rẹ?
No ũmĩĩhoke ĩkũrehere ngano yaku, na ĩmĩcookanĩrĩrie kĩhuhĩro-inĩ gĩaku?
13 “Ìwọ ni yóò ha fi ìyẹ́ dáradára fún ọ̀kín bí, tàbí ìyẹ́ àti ìhùhù bo ògòǹgò?
“Mathagu ma nyaga mabatabataga nĩ gũkena, no matingĩgerekanio na mathagu na njoya cia njũũ.
14 Ó yé ẹ̀yìn rẹ̀ sílẹ̀ lórí ilẹ̀, a sì mú wọn gbóná nínú ekuru;
Ĩrekagĩria matumbĩ mayo tĩĩri-inĩ na ĩkamatiga mũthanga-inĩ magwate ũrugarĩ,
15 tí ó sì gbàgbé pé, ẹsẹ̀ lè tẹ̀ wọ́n fọ́, tàbí pé ẹranko igbó lè tẹ̀ wọ́n fọ́.
ĩtegwĩciiria atĩ no makinywo na magũrũ makue, kana marangwo nĩ nyamũ ya gĩthaka.
16 Kò ní àánú sí àwọn ọmọ rẹ̀ bí ẹni pé wọn kì í ṣe tirẹ̀; asán ni iṣẹ́ rẹ̀ láìní ìbẹ̀rù;
Ĩĩkaga ciana ciayo ũũru ta itarĩ ciayo; ndĩmakaga atĩ wĩra wayo no ũtuĩke wa tũhũ,
17 nítorí pé Ọlọ́run kò fún un ní ọgbọ́n, bẹ́ẹ̀ ni kò sì fi ìpín òye fún un.
nĩgũkorwo Ngai ndaamĩheire ũũgĩ kana akĩmĩhe igai rĩa mwĩciirĩrie mwega.
18 Nígbà tí ó gbé ara sókè, ó gan ẹṣin àti ẹlẹ́ṣin.
No rĩrĩ, rĩrĩa yatambũrũkia mathagu ĩhanyũke, ĩthekagĩrĩra mbarathi na mũmĩhaici.
19 “Ìwọ ni ó fi agbára fún ẹṣin bí, tàbí ṣé ìwọ ni ó fi gọ̀gọ̀ wọ ọrùn rẹ̀ ní aṣọ?
“Wee nĩwe ũheaga mbarathi hinya wayo, kana ũkamĩhumba ngingo na mũreera?
20 Ìwọ le mú fò sókè bí ẹlẹ́ǹgà? Ògo èémí imú rẹ ní ẹ̀rù ńlá.
Wee nĩwe ũtũmaga ĩrũũge ta ngigĩ, ĩkahahũra andũ na mũtiihĩre wayo wa mwĩtĩĩo?
21 Ó fi ẹsẹ̀ halẹ̀ nínú àfonífojì, ó sì yọ̀ nínú agbára rẹ̀; ó lọ jáde láti pàdé àwọn ìhámọ́ra ogun.
Ĩhuragia thĩ na ũcamba ĩgĩkenagĩra hinya wayo, ĩkaguthũka ĩtoonyete mbaara-inĩ.
22 Ó fi ojú kékeré wo ẹ̀rù, àyà kò sì fò ó; bẹ́ẹ̀ ni kì í sì í padà sẹ́yìn kúrò lọ́wọ́ idà.
Ĩthekagĩrĩra guoya, ĩtarĩ ũndũ ĩngĩtigĩra; ndĩmakagio nĩ rũhiũ rwa njora.
23 Lọ́dọ̀ rẹ ni apó-ọfà ń mì pẹkẹpẹkẹ, àti ọ̀kọ̀ dídán àti àpáta.
Thiaka wa mũmĩhaici ũbocabocaga mbaru-inĩ ciayo, hamwe na itimũ rĩkũhenia na mĩcengi.
24 Ó fi kíkorò ojú àti ìbínú ńlá gbé ilé mi, bẹ́ẹ̀ ni òun kò sì gbà á gbọ́ pé, ìró ìpè ni.
Irĩĩaga tĩĩri nĩ ũrũme; ndĩngĩrũgama ĩkindĩirie hĩndĩ ĩrĩa karumbeta kagamba.
25 Ó wí nígbà ìpè pé, Háà! Háà! Ó sì gbóhùn ogun lókèèrè réré, igbe àwọn balógun àti ìhó ayọ̀ ogun wọn.
Hĩndĩ ĩrĩa karumbeta kagamba ĩgatiiha, ‘Hĩ!’ Ĩnyiitaga thaaha wa mbaara ĩrĩ o haraaya, na ĩkaigua kayũ ka anene a mbaara, o na mbugĩrĩrio ya mbaara.
26 “Àwòdì ha máa ti ipa ọgbọ́n rẹ̀ fò sókè, tí ó sì na ìyẹ́ apá rẹ̀ sí ìhà gúúsù?
“Rwĩgĩ-rĩ, nĩwe ũrũhotithagia kũmbũka na ũũgĩ waku, kana gũtambũrũkia mathagu maruo rwerekeire mwena wa gũthini?
27 Idì ha máa fi àṣẹ rẹ̀ fò sókè, kí ó sì lọ tẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ sí òkè gíga?
Nderi nĩwe ũmĩathaga yũmbũke na igũrũ, na ĩkeyakĩra gĩtara kĩayo igũrũ mũno?
28 Ó ń gbé, ó sì ń wò ní orí àpáta, lórí pàlàpálá òkúta àti ibi orí òkè.
Ĩtũũraga kĩharũrũka-inĩ kĩa ihiga, na nĩ ho ĩraaraga; rũhĩa-inĩ rwa ihiga iraaya mũno nĩ ho mwĩgitio wayo.
29 Láti ibẹ̀ lọ ni ó ti ń wá oúnjẹ kiri, ojú rẹ̀ sì ríran rí òkè réré.
Ĩrĩ hau nĩguo ĩcaragĩria gĩa kũrĩa; maitho mayo moonaga irio irĩ o kũraya.
30 Àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀lú a máa mu ẹ̀jẹ̀, níbi tí òkú bá gbé wà, níbẹ̀ ni òun wà pẹ̀lú.”
Tũcui twayo tũnyuuaga thakame, na handũ harĩa arĩa moragĩtwo marĩ, hau nĩ ho ĩkoragwo.”

< Job 39 >