< Job 36 >
1 Elihu sì tún sọ̀rọ̀ wí pé,
Ac Elihu el sifilpa fahk:
2 “Fún mi láyè díẹ̀ èmi ó sì fihàn ọ́, nítorí ọ̀rọ̀ sísọ ní ó kún fún Ọlọ́run.
“Sifilpa mongfisrasr kitin pacl ac lohng Kas ma nga ac aolla God ac fahk.
3 Èmi ó mú ìmọ̀ mi ti ọ̀nà jíjìn wá, èmi ó sì fi òdodo fún Ẹlẹ́dàá mi.
Yohk ma nga kalem kac; nga ac orekmakin ma kalem sik uh In akkalemye lah God, su oreyula, El suwosna.
4 Rí i dájú pé ọ̀rọ̀ mi kì yóò ṣèké nítòótọ́; ẹni tí ó pé ní ìmọ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Wangin kas kikiap ke ma nga ac fahk nu sum inge; Kom liye sie mwet na lalmwetmet ye motom.
5 “Kíyèsi i, Ọlọ́run ni alágbára, òun kò i sì gàn ènìyàn; ó ní agbára ní ipá àti òye.
“Arulana yohk ku lun God! Wangin sie mwet El srunga; Wangin kutena ma El tia kalem kac.
6 Òun kì í dá ẹ̀mí ènìyàn búburú sí, ṣùgbọ́n ó fi òtítọ́ fún àwọn tálákà.
El tia lela mwet koluk uh in moul na, Ac El oru ma suwohs nu sin mwet sukasrup in pacl nukewa.
7 Òun kì í mú ojú rẹ̀ kúrò lára olódodo, ṣùgbọ́n àwọn ọba ni wọ́n wà lórí ìtẹ́; àní ó fi ìdí wọn múlẹ̀ láéláé, a sì gbé wọn lékè.
El loangelos su suwosna moul la; Ac lela tuh elos in leumi oana tokosra, Ac oru in akfulatyeyuk elos nwe tok.
8 Bí ó bá sì dè wọ́n nínú àbà, tí a sì fi okùn ìpọ́njú dè wọ́n,
Tusruktu mwet uh fin kapiri ke sein, Ac keok ke sripen ma koluk elos orala,
9 nígbà náà ni ó ń sọ àwọn ohun tí wọn ti ṣe fún wọn, wí pé wọ́n ti ṣẹ̀ pẹ̀lú ìgbéraga wọn.
God El akkalemye nu selos ma koluk lalos ac inse fulat lalos.
10 Ó sí wọn létí pẹ̀lú sí ọ̀nà ẹ̀kọ́, ó sì pàṣẹ kí wọn kí ó padà kúrò nínú àìṣedédé.
El oru elos in lohng kas in sensenkakin lal nu selos Tuh elos in forla liki orekma koluk.
11 Bí wọ́n bá gbàgbọ́ tí wọ́n sì sìn ín, wọn ó lo ọjọ́ wọn ní ìrọ̀rùn, àti ọdún wọn nínú afẹ́.
Elos fin akos God ac kulansupal, Na elos ac insewowokin moul lalos uh in misla ac wo ouiya.
12 Ṣùgbọ́n, bí wọn kò bá gbàgbọ́, wọ́n ó ti ọwọ́ idà ṣègbé, wọ́n á sì kú láìní òye.
A elos fin tia akos ac kulansupu God, na elos ac anwuki ke cutlass, Ac misa in nikin lalos.
13 “Ṣùgbọ́n àwọn àgàbàgebè ní ayé kó ìbínú jọ; wọn kò kígbe fún ìrànlọ́wọ́ nígbà tí ó bá wọ́n wí.
“Mwet su tia etu God uh elos ac mutana in kasrkusrak lalos, Ac finne akkeokyeyuk elos, elos tia pre in suk kasru.
14 Nígbà náà ni ọkàn wọn yóò kú ní èwe, ní àárín àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà.
Elos ac srakna fusr na elos misa, Eli ke sie moul lusrongten.
15 Òun gba òtòṣì nínú ìpọ́njú wọn, a sì sọ̀rọ̀ sí wọn ní etí nínú ìnira wọn.
Tusruktu God El luti mwet uh ke mwe keok nu selos, Ac ikasla mutalos ke mwe ongoiya.
16 “Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lúpẹ̀lú ó fa wọn yọ láti inú ìhágágá sí ibi gbòòrò, sí ibi tí ó ní ààyè tí kò ní wàhálà nínú rẹ̀, ohun tí a sì gbé kalẹ̀ ní tábìlì rẹ̀ jẹ́ kìkì ọ̀rá oúnjẹ tí ó fẹ́.
“God El ke folokinkomme liki ongoiya, Nu ke sie acn mwesas, yen wangin ma ikus kom; Ac tepu lom uh sessesla ke mwe mongo yuyu.
17 Ṣùgbọ́n ìwọ kún fún ìdájọ́ àwọn búburú; ìdájọ́ àti òtítọ́ dì ọ́ mú.
Tusruktu, inge akkeokyeyuk kom oana ma fal in orek nu sum.
18 Nítorí ìbínú ń bẹ, ṣọ́ra kí òtítọ́ rẹ máa bá a tàn ọ; láti jẹ́ kí títóbi rẹ mú ọ ṣìnà.
Taranna kom in tia lela molin eyeinse in kiapwekomla, Ku mwe kasrup in aktafongyekomla.
19 Ọrọ̀ rẹ pọ̀ tó, tí wàhálà kì yóò fi dé bá ọ bí? Tàbí ipa agbára rẹ?
Kom finne pang ke kuiyom nufon in suk kasru, ac fah wangin sripa; Ku lom nufon tia ku in akwoye kom inge.
20 Má ṣe ìfẹ́ òru, nígbà tí a ń ké àwọn orílẹ̀-èdè kúrò ní ipò wọn.
Nimet kom ke in tari fongeni, In sun pacl ma mutunfacl lulap uh ac fah wanginla.
21 Máa ṣọ́ra kí ìwọ ki ó má yí ara rẹ̀ padà sí búburú, nítorí èyí tí ìwọ rò pé ó dára jù ìpọ́njú lọ.
Karinganang kom in tia forla nu ke ma koluk; Mwe keok lom inge ma tuku in tuh sruokkomi liki ma koluk.
22 “Kíyèsi i, Ọlọ́run ni gbéga nípa agbára rẹ̀; ta ni jẹ́ olùkọ́ni bí rẹ̀?
“Esam lupan yokiyen ku lun God uh; Su sie mwet luti oana El?
23 Ta ni ó là ọ̀nà iṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ fún un, tàbí ta ni ó lè wí pé ìwọ ti ń ṣe àìṣedéédéé?
Wangin mwet ku in fahk nu sin God ma Elan oru, Ku fahk mu koluk ma El oru uh.
24 Rántí kí ìwọ kí ó gbé iṣẹ́ rẹ̀ ga, ti ènìyàn ni yín nínú orin.
Nuna kaksakinyuk El pacl nukewa ke ma El oru; Enenu na kom in wi pac kaksakunul.
25 Olúkúlùkù ènìyàn a máa rí i; ẹni ikú a máa wò ó ní òkèrè.
Mwet nukewa liye tari ma El orala; Tusruktu kut ac tu na oe saya liye.
26 Kíyèsi i, Ọlọ́run tóbi, àwa kò sì mọ̀ bí ó ti ní òye tó, bẹ́ẹ̀ ni a kò lè wádìí iye ọdún rẹ̀ rí.
Kut tia ku in etu na pwaye lupan fulat lal uh, Ku oakla pisen yac lal uh.
27 “Nítorí pé òun ni ó fa ìkán omi òjò sílẹ̀, kí wọn kí ó kán bí òjò ní ìkùùkuu rẹ̀,
“God pa orauk kof uh liki faclu, Ac ekulla nu ke tulin af uh.
28 tí àwọsánmọ̀ ń rọ̀ ìrì rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì fi ń sẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ lórí ènìyàn.
El oru tuh kof uh in kahkla liki pukunyeng uh Ac afi nu fin mwet nukewa.
29 Pẹ̀lúpẹ̀lú ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè ní ìmọ̀ ìtànká àwọsánmọ̀, tàbí ariwo àrá láti àgọ́ rẹ̀?
Wangin mwet etu lah pukunyeng uh mukuikui fuka, Ku lah fuka tuh pulahl uh ngirngir In acn engyeng uh yen God El muta we.
30 Kíyèsi i, ó tan ìmọ́lẹ̀ yí ara rẹ̀ ká ó sì bo ìsàlẹ̀ òkun mọ́lẹ̀.
El supu sarom nu in acn nukewa yen engyeng uh, Tusruktu acn loal in meoa uh nuna lohsr na.
31 Nítorí pé nípa wọn ní ń ṣe dájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ènìyàn; ó sí ń pèsè oúnjẹ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Pa inge luman kiteyen mwet uh sel, Ac El sang mwe mongo puspis nun mwet uh.
32 Ó fi ìmọ́lẹ̀ bo ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì ó sì rán an sí ẹni olódì.
El sang paol sruokya sarom uh, Ac sap tuh in tungalya acn El ac fahk uh.
33 Ariwo àrá rẹ̀ fi ìjì hàn ní; ọ̀wọ́ ẹran pẹ̀lú wí pé, ó súnmọ́ etílé!
Pusren pulahl uh sulkakin lah paka se ac tuku, Ac un cow uh etu lah ac pakala.