< Job 36 >

1 Elihu sì tún sọ̀rọ̀ wí pé,
Elihu agĩthiĩ na mbere kwaria, akiuga atĩrĩ:
2 “Fún mi láyè díẹ̀ èmi ó sì fihàn ọ́, nítorí ọ̀rọ̀ sísọ ní ó kún fún Ọlọ́run.
“Ngirĩrĩria hanini, na nĩngũkuonia atĩ harĩ maũndũ mangĩ mangiugwo ma gũciirĩrĩra Ngai.
3 Èmi ó mú ìmọ̀ mi ti ọ̀nà jíjìn wá, èmi ó sì fi òdodo fún Ẹlẹ́dàá mi.
Ũmenyo wakwa ndĩũrutĩte kũraihu; niĩ ngũtũũgĩria kĩhooto kĩa ũcio Mũnyũũmbi.
4 Rí i dájú pé ọ̀rọ̀ mi kì yóò ṣèké nítòótọ́; ẹni tí ó pé ní ìmọ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Menya wega atĩ ndeto ciakwa ti cia maheeni; ũyũ mũrĩ nake arĩ na ũmenyo mũkinyanĩru.
5 “Kíyèsi i, Ọlọ́run ni alágbára, òun kò i sì gàn ènìyàn; ó ní agbára ní ipá àti òye.
“Mũrungu nĩwe mwene hinya, no ndairaga andũ; we nĩ mwene hinya, na nĩarũmagia muoroto wake.
6 Òun kì í dá ẹ̀mí ènìyàn búburú sí, ṣùgbọ́n ó fi òtítọ́ fún àwọn tálákà.
Ndatũũragia arĩa aaganu muoyo, no nĩaheaga arĩa anyariire kĩhooto kĩao.
7 Òun kì í mú ojú rẹ̀ kúrò lára olódodo, ṣùgbọ́n àwọn ọba ni wọ́n wà lórí ìtẹ́; àní ó fi ìdí wọn múlẹ̀ láéláé, a sì gbé wọn lékè.
Ndeheragia maitho make harĩ arĩa athingu; amaikaragĩria gĩtĩ kĩa ũnene hamwe na athamaki, na akamatũũgĩria nginya tene.
8 Bí ó bá sì dè wọ́n nínú àbà, tí a sì fi okùn ìpọ́njú dè wọ́n,
No rĩrĩ, andũ mangĩkorwo mohetwo na mĩnyororo, makanyiitio na mĩhĩndo ya mĩnyamaro,
9 nígbà náà ni ó ń sọ àwọn ohun tí wọn ti ṣe fún wọn, wí pé wọ́n ti ṣẹ̀ pẹ̀lú ìgbéraga wọn.
we nĩameeraga ũrĩa mekĩte, atĩ mehĩtie na ũtũrĩka.
10 Ó sí wọn létí pẹ̀lú sí ọ̀nà ẹ̀kọ́, ó sì pàṣẹ kí wọn kí ó padà kúrò nínú àìṣedédé.
We nĩatũmaga mathikĩrĩrie ũtaaro, na akamaatha merire ũũru wao.
11 Bí wọ́n bá gbàgbọ́ tí wọ́n sì sìn ín, wọn ó lo ọjọ́ wọn ní ìrọ̀rùn, àti ọdún wọn nínú afẹ́.
Mangĩmwathĩkĩra na mamũtungatĩre, megũtũũra matukũ mao marĩa matigaru magaacĩire, na mĩaka yao o maiganĩire.
12 Ṣùgbọ́n, bí wọn kò bá gbàgbọ́, wọ́n ó ti ọwọ́ idà ṣègbé, wọ́n á sì kú láìní òye.
No mangĩaga kũigua, nĩmakaniinwo na rũhiũ rwa njora, na makue matarĩ na ũmenyo.
13 “Ṣùgbọ́n àwọn àgàbàgebè ní ayé kó ìbínú jọ; wọn kò kígbe fún ìrànlọ́wọ́ nígbà tí ó bá wọ́n wí.
“Arĩa matarĩ na Ngai ngoro-inĩ meiigagĩra marakara; o na rĩrĩa aramooha na mĩnyororo, matikayaga mateithio.
14 Nígbà náà ni ọkàn wọn yóò kú ní èwe, ní àárín àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà.
Makuuaga marĩ ethĩ, magakua hamwe na arũme arĩa maraya ma mahooero-inĩ.
15 Òun gba òtòṣì nínú ìpọ́njú wọn, a sì sọ̀rọ̀ sí wọn ní etí nínú ìnira wọn.
No arĩa mathĩĩnĩkaga, nĩamakũũraga kuuma thĩĩna-inĩ wao; nĩamaragĩria marĩ mĩnyamaro-inĩ.
16 “Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lúpẹ̀lú ó fa wọn yọ láti inú ìhágágá sí ibi gbòòrò, sí ibi tí ó ní ààyè tí kò ní wàhálà nínú rẹ̀, ohun tí a sì gbé kalẹ̀ ní tábìlì rẹ̀ jẹ́ kìkì ọ̀rá oúnjẹ tí ó fẹ́.
“We-rĩ, nĩarakũguucĩrĩria uume magego-inĩ ma mĩnyamaro, agũtware handũ haariĩ hatarĩ na ũkunderu, na agũtware akũhurũkie metha-inĩ yaku ĩiyũrĩte irio iria njega.
17 Ṣùgbọ́n ìwọ kún fún ìdájọ́ àwọn búburú; ìdájọ́ àti òtítọ́ dì ọ́ mú.
No rĩu-rĩ, ũtitikithĩtio ituĩro rĩrĩa rĩagĩrĩire arĩa aaganu; ituĩro rĩa ciira na kĩhooto nĩcigũkumbatĩte.
18 Nítorí ìbínú ń bẹ, ṣọ́ra kí òtítọ́ rẹ máa bá a tàn ọ; láti jẹ́ kí títóbi rẹ mú ọ ṣìnà.
Wĩmenyerere mũndũ o na ũrĩkũ ndakanakũheenererie na ũtonga; ndũgetĩkĩrie ihaki inene rĩkũhĩtithie njĩra.
19 Ọrọ̀ rẹ pọ̀ tó, tí wàhálà kì yóò fi dé bá ọ bí? Tàbí ipa agbára rẹ?
Ũtonga waku o na kana kĩyo gĩaku kĩnene-rĩ, no ikũnyiitĩrĩre nĩguo ndũgatoonye mĩnyamaro-inĩ?
20 Má ṣe ìfẹ́ òru, nígbà tí a ń ké àwọn orílẹ̀-èdè kúrò ní ipò wọn.
Tiga kwĩrirĩria ũtukũ, nĩguo ũguucũrũrie andũ kuuma kwao mĩciĩ.
21 Máa ṣọ́ra kí ìwọ ki ó má yí ara rẹ̀ padà sí búburú, nítorí èyí tí ìwọ rò pé ó dára jù ìpọ́njú lọ.
Wĩmenyerere ndũkeerekere ũũru-inĩ, tondũ ũkuoneka taarĩ guo wendete gũkĩra gũthĩĩnĩka.
22 “Kíyèsi i, Ọlọ́run ni gbéga nípa agbára rẹ̀; ta ni jẹ́ olùkọ́ni bí rẹ̀?
“Mũrungu nĩatũgĩrĩtio nĩ ũndũ wa ũhoti wake. Nũũ mũrutani take?
23 Ta ni ó là ọ̀nà iṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ fún un, tàbí ta ni ó lè wí pé ìwọ ti ń ṣe àìṣedéédéé?
Nũũ ũmwathĩrĩire njĩra ciake, kana akamwĩra atĩrĩ, ‘Wee nĩwĩkĩte ũũru’?
24 Rántí kí ìwọ kí ó gbé iṣẹ́ rẹ̀ ga, ti ènìyàn ni yín nínú orin.
Ririkanaga gwĩkĩrĩra wĩra wake, ũrĩa andũ manakumia na rwĩmbo.
25 Olúkúlùkù ènìyàn a máa rí i; ẹni ikú a máa wò ó ní òkèrè.
Andũ othe nĩmawonete; andũ mawĩroragĩra marĩ o kũraya.
26 Kíyèsi i, Ọlọ́run tóbi, àwa kò sì mọ̀ bí ó ti ní òye tó, bẹ́ẹ̀ ni a kò lè wádìí iye ọdún rẹ̀ rí.
Ĩ Mũrungu ndakĩrĩ mũnene; nĩ mũnene gũkĩra ũmenyi witũ! Mũigana wa mĩaka yake ndũngĩtuĩrĩka.
27 “Nítorí pé òun ni ó fa ìkán omi òjò sílẹ̀, kí wọn kí ó kán bí òjò ní ìkùùkuu rẹ̀,
“Ambatagia matata ma maaĩ, marĩa macookaga gũtaatĩra tũrũũĩ ta mbura;
28 tí àwọsánmọ̀ ń rọ̀ ìrì rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì fi ń sẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ lórí ènìyàn.
matu magaita ũigũ wamo, nayo mbura nyingĩ ĩkoirĩra andũ.
29 Pẹ̀lúpẹ̀lú ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè ní ìmọ̀ ìtànká àwọsánmọ̀, tàbí ariwo àrá láti àgọ́ rẹ̀?
Nũũ ũngĩmenya ũrĩa atambũrũkagia matu, kana ũhoro wa marurumĩ marĩa moimaga hema-inĩ yake?
30 Kíyèsi i, ó tan ìmọ́lẹ̀ yí ara rẹ̀ ká ó sì bo ìsàlẹ̀ òkun mọ́lẹ̀.
Kĩone ũrĩa ahurunjaga rũheni rwake rũkamũthiũrũrũkĩria, agathambia iria kũrĩa kũriku.
31 Nítorí pé nípa wọn ní ń ṣe dájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ènìyàn; ó sí ń pèsè oúnjẹ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Ũũ nĩguo aathaga ndũrĩrĩ na akaheana irio nyingĩ.
32 Ó fi ìmọ́lẹ̀ bo ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì ó sì rán an sí ẹni olódì.
Akumbatagĩria rũheni na moko make, na akarwatha rũringe kĩrĩa kĩorotetwo.
33 Ariwo àrá rẹ̀ fi ìjì hàn ní; ọ̀wọ́ ẹran pẹ̀lú wí pé, ó súnmọ́ etílé!
Marurumĩ make nĩmanagĩrĩra kĩhuhũkanio kĩrĩa kĩroka; o na ngʼombe nĩimenyithanagia atĩ kũrĩ kĩhuhũkanio kĩroka.

< Job 36 >