< Job 35 >
OLELO aku la hoi o Elihu, i aku la,
2 “Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé, òdodo mi ni èyí níwájú Ọlọ́run?
Ke manao nei oe he pono keia, O kau i olelo mai, O ko'u pono, ua oi mamua o ko ke Akua?
3 Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ, tàbí èrè kí ni èmi yóò fi jẹ́ ju èrè ẹ̀ṣẹ̀ mi lọ.
No ka mea, ua ninau mai oe, Heaha ka pono no'u? Heaha hoi ko'u pomaikai no kuu hewa ole ana?
4 “Èmi ó dá ọ lóhùn àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ pẹ̀lú rẹ.
Owau ke hoihoi aku ia olelo iou la, A i kou mau hoalauna me oe.
5 Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì bojú wo àwọsánmọ̀ tí ó ga jù ọ́ lọ.
E nana ae oe i ka lani, a ike; A e nana i na ao, ua kiekie lakou mamua ou.
6 Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí? Tàbí bí ìrékọjá rẹ di púpọ̀, kí ni ìwọ fi èyí nì ṣe sí i?
Ina e hana hewa oe, heaha kau hana ia ia? Ina e hoonuiia kou mau hala, heaha kau e hana'i nana?
7 Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un, tàbí kí ni òun rí gbà láti ọwọ́ rẹ wá?
Ina ua pono oe, heaha kau e haawi aku ai ia ia? Heaha kana e loaa'i mai kou lima aku?
8 Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ; òdodo rẹ sì ni fún ọmọ ènìyàn.
No ke kanaka e like me oe kou hala, A no ke keiki a ke kanaka kou pono.
9 “Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe; wọ́n kígbe nípa apá àwọn alágbára.
Ke uwe ae nei ka poe kaumaha no ka hooluhiia; I uwe lakou no ka lima o na mea koikoi.
10 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé, ‘Níbo ni Ọlọ́run Ẹlẹ́dàá mi wà tí ó sì fi orin fún mi ní òru;
Aka, aole e i mai kekahi, Auhea ke Akua nana au i hana, Ka mea i haawi mai i na mele olioli i ka po;
11 tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ, tí ó sì mú wa gbọ́n ju àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run lọ?’
O ka mea i ao mai ia kakou mamua o na holoholona o ka honua, A ua hoonaauao oia ia kakou mamua o na manu o ka lewa?
12 Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn nítorí ìgbéraga ènìyàn búburú.
Malaila lakou e uwe ai, aole mea i ekemu mai, No ka haaheo o ka poe hewa.
13 Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán; bẹ́ẹ̀ ní Olódùmarè kì yóò kà á sí.
He oiaio, aole ke Akua e hoolohe mai i ka mea wahahee, Aole ka Mea mana e maliu mai ia.
14 Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i, ọ̀rọ̀ ìdájọ́ ń bẹ níwájú rẹ, ẹni tí ìwọ sì gbọdọ̀ dúró dè.
Ina paha e olelo oe, aole oe i ike ia ia, Imua ona ka hooponopono, nolaila e kali aku oe ia ia.
15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni, òun kò ni ka ìwà búburú si?
Ano hoi, he mea ole ka hoopai ana o kona inaina, Aole ia e haka pono mai i na hewa;
16 Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀ lásán ó sọ ọ̀rọ̀ di púpọ̀ láìsí ìmọ̀.”
Nolaila i oaka hewa mai ai ko Ioba waha, He hoonui olelo kana me ko ike ole.