< Job 35 >

1 Elihu sì wí pe:
Yoube! Di da Gode Ea siga ba: ma: ne moloidafa fawane hamosa sia: be, amo da defea hame.
2 “Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé, òdodo mi ni èyí níwájú Ọlọ́run?
3 Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ, tàbí èrè kí ni èmi yóò fi jẹ́ ju èrè ẹ̀ṣẹ̀ mi lọ.
Di da Godema amane sia: sa. ‘Na wadela: i hou da Dima bai hame gala. Na da wadela: i hou hame hamoiba: le, bidi noga: i hamedafa ba: i.’ Amo sia: amola da defea hame.
4 “Èmi ó dá ọ lóhùn àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ pẹ̀lú rẹ.
Na da dima amola dia samalalima gilisili adole imunu.
5 Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì bojú wo àwọsánmọ̀ tí ó ga jù ọ́ lọ.
Mu ba: ma! Mu mobi gadodafa dialebe amo ba: ma!
6 Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí? Tàbí bí ìrékọjá rẹ di púpọ̀, kí ni ìwọ fi èyí nì ṣe sí i?
Di da wadela: le hamoi ganiaba, Gode da se hame naba: loba. Di da wadela: i hou gebewane hamonanea, Gode da Ea hou afadenema: bela: ?
7 Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un, tàbí kí ni òun rí gbà láti ọwọ́ rẹ wá?
Di da moloidafa hou hamobeba: le, Godema fidima: bela: ? Gode da dima fidisu lamu da hamedei.
8 Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ; òdodo rẹ sì ni fún ọmọ ènìyàn.
Dia da wadela: le hamobeba: le, dunu eno da se naba. Amola dia da noga: i hou hamosea, amo da ilia hou fidisa.
9 “Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe; wọ́n kígbe nípa apá àwọn alágbára.
Gasa fi dunu da eno dunu banenesisia, ilia da gogonomosa. Ilia dunu eno ili gaga: ma: ne wele sia: sa.
10 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé, ‘Níbo ni Ọlọ́run Ẹlẹ́dàá mi wà tí ó sì fi orin fún mi ní òru;
Be ilia da ili hahamosu Godema hame sinidigisa. Be ilia da gasi dunasi amo ganodini se nabawane esalea, Gode da ilima hobea misunu hahawane hou dafawane hamoma: beyale dawa: lusu imunusa: dawa:
11 tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ, tí ó sì mú wa gbọ́n ju àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run lọ?’
Ilia Godema hame sinidigisa. Be Gode da bagade dawa: su hou ninima iaha. Amola E da amo ninima iabeba: le, ninia asigi dawa: su da ohe fi amola sio fi huluane ilia asigi dawa: su baligisa.
12 Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn nítorí ìgbéraga ènìyàn búburú.
Ilia da Godema, ili fidima: ne wele sia: sa, be Gode da ilima dabe hame adole iaha. Bai ilia da hidale gasa fili agoane wadela: le hamosa.
13 Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán; bẹ́ẹ̀ ní Olódùmarè kì yóò kà á sí.
Ilia udigili agoane fidima: ne wele sia: sa. Bai Gode Bagadedafa da ili hame ba: sa amola ilia sia: hame naba.
14 Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i, ọ̀rọ̀ ìdájọ́ ń bẹ níwájú rẹ, ẹni tí ìwọ sì gbọdọ̀ dúró dè.
Yoube! Di Gode hame ba: sa sia: sa! Be gebewane ouesaloma! Gode da Ea ilegei eso doaga: sea, fofada: mu.
15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni, òun kò ni ka ìwà búburú si?
Di da Gode da se dabe hame iaha dawa: sa. Di da Gode da wadela: i hou hame abodesayale dawa: sa.
16 Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀ lásán ó sọ ọ̀rọ̀ di púpọ̀ láìsí ìmọ̀.”
Di da bu gebewane sia: nanumu da hamedei. Na ba: loba, dia da bai hame dawa: beba: le, udigili sia: daha.

< Job 35 >