< Job 32 >
1 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí dákẹ́ láti dá Jobu lóhùn, nítorí ó ṣe olódodo lójú ara rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio andũ acio atatũ nĩmatigire gũcookeria Ayubu, nĩ ũndũ eeyonaga arĩ mũthingu.
2 Nígbà náà ni inú bí Elihu ọmọ Barakeli ará Busi, láti ìbátan ìdílé Ramu; ó bínú si Jobu nítorí ti ó dá ara rẹ̀ láre kàkà ki ó dá Ọlọ́run láre.
No rĩrĩ, Elihu mũrũ wa Barakeli ũrĩa Mũbuzi, wa nyũmba ya Ramu, nĩarakaririo mũno nĩ Ayubu nĩ ũndũ wa gwĩtua aarĩ na kĩhooto gũkĩra Ngai.
3 Inú sì bí i sí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta, nítorí tí wọn kò rí ọ̀nà láti dá Jobu lóhùn bẹ́ẹ̀ ni wọ́n dá Jobu lẹ́bi.
Ningĩ nĩarakarĩtio nĩ arata acio atatũ tondũ nĩmagĩte ũndũ mangĩcookeria Ayubu, o na gũtuĩka nĩmamũtuĩrĩire ciira.
4 Ǹjẹ́ Elihu ti dúró títí tí Jobu fi sọ̀rọ̀ tán nítorí tí àwọn wọ̀nyí dàgbà ju òun lọ ní ọjọ́ orí.
Na rĩrĩ, Elihu aambĩte gweterera acio angĩ maarie atanaaria na Ayubu, tondũ o maarĩ akũrũ kũmũkĩra.
5 Nígbà tí Elihu rí i pé ìdáhùn ọ̀rọ̀ kò sí ní ẹnu àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí nígbà náà ni ó bínú.
No rĩrĩa onire atĩ andũ acio atatũ matiarĩ na ũndũ ũngĩ wa kuuga-rĩ, agĩakanwo nĩ marakara.
6 Elihu, ọmọ Barakeli, ará Busi, dáhùn ó sì wí pé, “Ọmọdé ni èmi, àgbà sì ní ẹ̀yin; ǹjẹ́ nítorí náà ní mo dúró, mo sì ń bẹ̀rù láti fi ìmọ̀ mi hàn yin.
Nĩ ũndũ ũcio Elihu, mũrũ wa Barakeli ũcio Mũbuzi, akiuga atĩrĩ: “Niĩ ndĩ na mĩaka mĩnini, na inyuĩ mũrĩ akũrũ; nĩkĩo ngwĩtigagĩra, ngaaga ũũmĩrĩru wa kũmwĩra ũrĩa njũũĩ.
7 Èmi wí pé ọjọ́ orí ni ìbá sọ̀rọ̀, àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ní ìbá kọ́ ni ní ọgbọ́n.
Ndeciiragia atĩrĩ, ‘Ũkũrũ nĩwaagĩrĩire warie; ũingĩ wa mĩaka nĩwaagĩrĩire kũrutana ũũgĩ.’
8 Ṣùgbọ́n ẹ̀mí kan ní ó wà nínú ènìyàn àti ìmísí Olódùmarè ní ì sì máa fún wọn ní òye.
No nĩ roho ũrĩa ũrĩ thĩinĩ wa mũndũ, o yo mĩhũmũ ya Mwene-Hinya-Wothe, ũheaga mũndũ ũmenyo.
9 Ènìyàn ńlá ńlá kì í ṣe ọlọ́gbọ́n, bẹ́ẹ̀ ni àwọn àgbà ní òye ẹ̀tọ́ kò yé.
To arĩa akũrũ oiki oogĩ, na to arĩa akũrũ mamenyaga ũrĩa kwagĩrĩire.
10 “Nítorí náà ní èmí ṣe wí pé, ẹ dẹtí sílẹ̀ sí mi; èmí pẹ̀lú yóò fi ìmọ̀ mi hàn.
“Nĩ ũndũ ũcio nguuga atĩrĩ, ‘Thikĩrĩriai; o na niĩ nĩngũmwĩra ũrĩa njũũĩ.’
11 Kíyèsi i, èmí ti dúró de ọ̀rọ̀ yín; èmi fetísí àròyé yín, nígbà tí ẹ̀yin ń wá ọ̀rọ̀ ti ẹ̀yin yóò sọ;
Nĩngwetereire rĩrĩa mũkwaragia, ndathikĩrĩria ihooto cianyu; rĩrĩa mũgũcaragia ciugo-rĩ,
12 àní, mo fiyèsí yín tinútinú. Sì kíyèsi i, kò sí ẹnìkan nínú yín tí ó le já Jobu ní irọ́; tàbí tí ó lè dá a lóhùn àríyànjiyàn rẹ̀!
nĩngũmũtegeire matũ biũ. No gũtirĩ o na ũmwe wanyu wonanirie mahĩtia ma Ayubu; gũtirĩ o na ũmwe wanyu ũmũcookeirie mĩario yake.
13 Kí ẹ̀yin kí ó má ṣe wí pé, ‘Àwa wá ọgbọ́n ní àwárí; Ọlọ́run ni ó lè bì í ṣubú kì í ṣe ènìyàn.’
Tigai kuuga atĩrĩ, ‘Nĩtũgĩĩte na ũũgĩ; rekei Mũrungu amũkararie, no ti mũndũ.’
14 Bí òun kò ti sọ̀rọ̀ sí mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò fi ọ̀rọ̀ yín dá a lóhùn.
No rĩrĩ, Ayubu ti niĩ ekwerekeirie ciugo ciake, na niĩ ndikũmũcookeria kũringana na mĩario yanyu.
15 “Ẹnu sì yà wọ́n, wọn kò sì dáhùn mọ́, wọ́n ṣíwọ́ ọ̀rọ̀ í sọ.
“Nĩmamakĩte, na matirĩ na ũndũ ũngĩ mangiuga; nĩmarigĩtwo nĩ atĩa mangiuga.
16 Mo sì retí, nítorí wọn kò sì fọhùn, wọ́n dákẹ́ jẹ́ẹ́; wọn kò sì dáhùn mọ́.
no nginya njeterere, nĩ ũndũ rĩu nĩmakirĩte, tondũ atĩ rĩu marũgamĩte hau matarĩ na macookio?
17 Bẹ́ẹ̀ ni èmí ó sì dáhùn nípa ti èmi, èmí pẹ̀lú yóò sì fi ìmọ̀ mi hàn.
O na niĩ nĩngwaria; o na niĩ nĩnguuga ũrĩa njũũĩ.
18 Nítorí pé èmi kún fún ọ̀rọ̀ sísọ, ẹ̀mí ń rọ̀ mi ni inú mi.
Nĩgũkorwo njiyũrĩtwo nĩ ciugo, naguo roho ũrĩa ũrĩ thĩinĩ wakwa nĩũrandindĩkĩrĩria;
19 Kíyèsi i, ikùn mi dàbí ọtí wáìnì, tí kò ní ojú-ìhò; ó múra tán láti bẹ́ bí ìgò-awọ tuntun.
thĩinĩ wakwa haana ta ndibei ĩrĩ cuba ngunĩke, ngahaana ta mondo njerũ ya ndibei ĩkirie gũtuthũka.
20 Èmí ó sọ, kí ara kí ó le rọ̀ mí, èmí ó sí ètè mi, èmí ó sì dáhùn.
no nginya njarie hũũcũke, no nginya ndumũre mĩromo yakwa njookie ũhoro.
21 Lóòtítọ́ èmi kì yóò ṣe ojúsàájú sí ẹnìkankan, bẹ́ẹ̀ ni èmí kì yóò sì ṣe ìpọ́nni fún ẹnìkan.
Ndigũtĩĩra mũndũ o na ũ maũthĩ, kana ngaathĩrĩrie mũndũ o na ũrĩkũ tũhũ;
22 Nítorí pé èmí kò mọ̀ ọ̀rọ̀ ìpọ́nni í sọ ní ṣíṣe bẹ́ẹ̀, ẹlẹ́dàá mi yóò mú mi kúrò lọ́gán.
nĩ ũndũ korwo ndĩ mwara na kũgaathĩrĩria, Mũnyũũmbi no anjeherie narua.