< Job 31 >

1 “Mo ti bá ojú mi dá májẹ̀mú, èmi yó ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?
Szövetséget kötöttem szemeimmel, hogyan vetnék hát ügyet hajadonra?
2 Nítorí pé kí ni ìpín Ọlọ́run láti ọ̀run wá? Tàbí kí ni ogún Olódùmarè láti òkè ọ̀run wá.
Hisz mely osztályrész jut Istentől felülről s mely örökség a Mindenhatótól a magasból?
3 Kò ṣe pé àwọn ènìyàn búburú ni ìparun wà fún, àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀?
Nemde balsors a jogtalannak s viszontagság a gonosztevőknek.
4 Òun kò ha ri ipa ọ̀nà mi, òun kò ha sì ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?
Nemde ő látja útaimat s mind a lépéseimet megszámlálja!
5 “Bí ó bá ṣe pé èmi bá fi àìṣòótọ́ rìn, tàbí tí ẹsẹ̀ mi sì yára sí ẹ̀tàn,
Ha hamissággal jártam és csalárdságra sietett a lábam –
6 (jẹ́ kí Ọlọ́run wọ́n mí nínú ìwọ̀n òdodo, kí Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)
mérjen meg engem igaz serpenyőn s tudja meg Isten gáncstalanságomat –
7 Bí ẹsẹ̀ mí bá yà kúrò lójú ọ̀nà, tí àyà mí sì tẹ̀lé ipa ojú mi, tàbí bí àbàwọ́n kan bá sì lẹ̀ mọ́ mi ní ọwọ́,
ha léptem elhajolt az útról és szemeim után járt a szívem, kezeimhez hiba tapadt:
8 ǹjẹ́ kí èmi kí ó gbìn kí ẹlòmíràn kí ó sì mújẹ, àní kí a fa irú-ọmọ mi tu.
hadd vessek és más egyék, és sarjaim tépessenek ki gyökerestül!
9 “Bí àyà mi bá di fífà sí ipasẹ̀ obìnrin kan, tàbí bí mo bá lọ í ba de ènìyàn ní ẹnu-ọ̀nà ilé aládùúgbò mi,
Ha szívem elcsábíttatta magát asszony miatt, felebarátom ajtaján leskelődtem:
10 kí àyà mi kí ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn, kí àwọn ẹlòmíràn kí ó tẹ̀ ara wọn ní ara rẹ̀.
másnak őröljön a feleségem és mások hajoljanak reá;
11 Nítorí pé yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní, ẹ̀ṣẹ̀ tí a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.
mert gazság az, s bírák elé való bűn az,
12 Nítorí pé iná ní èyí tí ó jó dé ibi ìparun, tí ìbá sì fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.
mert tűz az, mely az enyészetig emészt, s minden termésemet gyökerestül tépi ki!
13 “Tí mo bá sì ṣe àìka ọ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi sí, nígbà tí wọ́n bá ń bá mi jà;
Ha megvetettem szolgám és szolgálóm jogát, mikor pöröltek velem –
14 kí ni èmi ó ha ṣe nígbà tí Ọlọ́run bá dìde? Nígbà tí ó bá sì ṣe ìbẹ̀wò, ohùn kí ni èmi ó dá?
hiszen mit teszek majd, midőn Isten fölkel s midőn számon kér, mit felelek neki,
15 Ẹni tí ó dá mi ní inú kọ́ ni ó dá a? Ẹnìkan náà kí ó mọ wá ní inú ìyá wa?
hiszen az anyaméhben ki engem alkotott, alkotta őt és Egy formált minket a méhben –
16 “Bí mo bá fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà, tàbí bí mo bá sì mú kí ojú opó rẹ̀wẹ̀sì,
ha megvontam a kívántat a szegényektől s az özvegy szemeit epesztettem,
17 tàbí tí mo bá nìkan bu òkèlè mi jẹ, tí aláìní baba kò jẹ nínú rẹ̀;
s én egyedül ettem falatomat s árva nem evett belőle
18 nítorí pé láti ìgbà èwe mi wá ni a ti tọ́ ọ dàgbà pẹ̀lú mi bí ẹni pé baba, èmi sì ń ṣe ìtọ́jú opó láti inú ìyá mi wá:
– hisz ifjúkorom óta nálam nőtt fel, mint atyánál, s mint anyám méhéből valót úgy vezettem -;
19 bí èmi bá rí olùpọ́njú láìní aṣọ, tàbí tálákà kan láìní ìbora;
ha láttam bujdosót öltözet nélkül s takarója nincs a szűkölködőnek,
20 bí ọkàn rẹ̀ kò bá súre fún mi, tàbí bí ara rẹ̀ kò sì gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;
ha nem áldottak engem ágyékai s bárányaim nyíretéből fel nem melegedett;
21 bí mo bá sì gbé ọwọ́ mi sókè sí aláìní baba, nítorí pé mo rí ìrànlọ́wọ́ mi ní ẹnu ibodè,
ha fölemeltem kezemet az árvára, midőn a kapuban láttam segítségemet:
22 ǹjẹ́, ní apá mi kí o wọ́n kúrò ní ihò èjìká rẹ̀, kí apá mi kí ó sì ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ wá.
vállam essék ki a lapoczkájából és törjék el karom a szárából;
23 Nítorí pé ìparun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ẹ̀rù ńlá fún mi, àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi kò le è dúró.
mert rettenet nekem az Istentől való balsors, s fensége miatt nem tehetném!
24 “Bí ó bá ṣe pé mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé mi, tàbí tí mo bá wí fún fàdákà dídára pé, ‘Ìwọ ni ààbò mi,’
Ha aranyat tettem bizalmammá és a színaranyat mondtam bizodalmamnak;
25 bí mo bá yọ̀ nítorí ọrọ̀ mí pọ̀, àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,
ha örültem, hogy nagy a vagyonom s hogy sokat ért el kezem;
26 bí mo bá bojú wo oòrùn nígbà tí ń ràn, tàbí òṣùpá tí ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,
ha láttam a napvilágot, hogy ragyog, s a holdat, a mint dicsőn halad,
27 bí a bá tàn ọkàn mi jẹ láti fi ẹnu mi kò ọwọ́ mi,
és szívem elcsábult titokban és kezem csókra nyúlt a szájamhoz:
28 èyí pẹ̀lú ni ẹ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ ní láti bẹ̀wò, nítorí pé èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run tí ó wà lókè.
az is bíró elé való bűn, mert megtagadtam volna Istent felülről!
29 “Bí ó bá ṣe pé mo yọ̀ sì ìparun ẹni tí ó kórìíra mi. Tàbí bí mo bá sì gbéraga sókè, nígbà tí ibi bá a.
Ha örültem gyűlölőm elesésén s felbuzdultam, midőn baj érte –
30 Bẹ́ẹ̀ èmi kò sì jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀ nípa fífẹ́ ègún sí ọkàn rẹ̀.
hisz nem engedtem ínyemet, hogy vétkezzen, hogy átokkal kérjem lelkét -;
31 Bí àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi kò bá lè wí pé, ‘Ta ni kò ì tí ì jẹ ẹran rẹ̀ ní àjẹyó?’
ha nem mondták sátram emberei: bár volna, ki húsából nem lakott jól
32 Àlejò kò wọ̀ ni ìgboro rí; èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.
az utczán nem hált meg jövevény, az út felé tártam ki ajtaimat -;
33 Bí mo bá bò ẹ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ bí Adamu ni pápá, ẹ̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.
ha emberek módjára takargattam bűntetteimet, keblemre rejtve bűnömet,
34 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀rù bí? Tàbí ẹ̀gàn àwọn ìdílé ní ń bà mí ní ẹ̀rù? Tí mo fi pa ẹnu mọ́, tí èmí kò sì fi sọ̀rọ̀ jáde?
mert rettegtem a nagy tömegtől s megijesztett a családok gúnyja, úgy hogy csendben voltam, nem mentem ki a kapun!
35 (“Ìbá ṣe pé ẹnìkan le gbọ́ ti èmí! Kíyèsi i, àmì mi, kí Olódùmarè kí ó dá mi lóhùn, kí èmí kí ó sì rí ìwé náà tí olùfisùn mi ti kọ.
Vajha volna, ki rám hallgatna – íme jegyem, feleljen nekem a Mindenható – és a vádlevél, melyet írt a pörös felem:
36 Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi, èmi ìbá sì dé bí adé mọ́ orí mi.
bizony, vállamon hordanám azt, felfűzném koszorúnak magamra,
37 Èmi ìbá sì sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un, bí ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀.)
lépéseim számát bevallanám neki, akár egy fejedelem közeledném hozzá!
38 “Bí ilẹ̀ mi bá sì ké rara lòdì sí mi tí a sì fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.
Ha ellenem kiáltott földem s egyaránt sírtak barázdái;
39 Bí mo bá jẹ èso oko mi láìsan owó tàbí tí mo sì mú ọkàn olúwa rẹ̀ fò lọ,
ha erejét emésztettem pénz nélkül és gazdájával kileheltettem lelkét:
40 kí ẹ̀gún òṣùṣú kí ó hù dípò alikama, àti èpò búburú dípò ọkà barle.” Ọ̀rọ̀ Jobu parí.
búza helyett sarjadjon bogáncs, és árpa helyett gazfű! Vége Jób beszédeinek.

< Job 31 >