< Job 31 >

1 “Mo ti bá ojú mi dá májẹ̀mú, èmi yó ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?
“Niĩ nĩtwarĩĩkanĩire na maitho makwa ndikanarore mũirĩtu ndĩmwĩrirĩrie.
2 Nítorí pé kí ni ìpín Ọlọ́run láti ọ̀run wá? Tàbí kí ni ogún Olódùmarè láti òkè ọ̀run wá.
Nĩ ũndũ-rĩ, kaĩ rũgai rwa mũndũ kuuma igũrũ kwa Ngai rũkĩrĩ kĩĩ? Igai rĩake nĩ rĩrĩkũ kuuma kũrĩ ũcio Mwene-Hinya-Wothe ũrĩ igũrũ?
3 Kò ṣe pé àwọn ènìyàn búburú ni ìparun wà fún, àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀?
Githĩ ti kwanangwo kwa arĩa aaganu, na mũtino kũrĩ arĩa meekaga maũndũ mooru?
4 Òun kò ha ri ipa ọ̀nà mi, òun kò ha sì ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?
Githĩ we ndonaga njĩra ciakwa, na agatara o ikinya o ikinya rĩakwa?
5 “Bí ó bá ṣe pé èmi bá fi àìṣòótọ́ rìn, tàbí tí ẹsẹ̀ mi sì yára sí ẹ̀tàn,
“Ingĩkorwo thiiaga na njĩra itarĩ cia ma-rĩ, kana kũgũrũ gwakwa gũkahiũha thiĩ ngaheenanie-rĩ,
6 (jẹ́ kí Ọlọ́run wọ́n mí nínú ìwọ̀n òdodo, kí Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)
Ngai nĩathime na ratiri cia kĩhooto, nake nĩekũmenya atĩ niĩ ndirĩ ũcuuke;
7 Bí ẹsẹ̀ mí bá yà kúrò lójú ọ̀nà, tí àyà mí sì tẹ̀lé ipa ojú mi, tàbí bí àbàwọ́n kan bá sì lẹ̀ mọ́ mi ní ọwọ́,
makinya makwa mangĩkorwo nĩmahũkĩte makoima njĩra-inĩ, nayo ngoro yakwa ĩngĩkorwo nĩĩtongoretio nĩ maitho makwa, kana moko makwa makorwo nĩmathaahĩtio-rĩ,
8 ǹjẹ́ kí èmi kí ó gbìn kí ẹlòmíràn kí ó sì mújẹ, àní kí a fa irú-ọmọ mi tu.
hĩndĩ ĩyo kĩrĩa haandĩte kĩrorĩĩo nĩ andũ angĩ, nacio irio cia mĩgũnda yakwa iromunywo.
9 “Bí àyà mi bá di fífà sí ipasẹ̀ obìnrin kan, tàbí bí mo bá lọ í ba de ènìyàn ní ẹnu-ọ̀nà ilé aládùúgbò mi,
“Ngoro yakwa ĩngĩkorwo yanaheenererio nĩ mũndũ-wa-nja, kana ngorwo ndanaceema mũrango-inĩ wa mũndũ wa itũũra,
10 kí àyà mi kí ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn, kí àwọn ẹlòmíràn kí ó tẹ̀ ara wọn ní ara rẹ̀.
hĩndĩ ĩyo mũtumia wakwa arothĩa ngano ya mũndũ ũngĩ, na arũme angĩ tiga niĩ marokoma nake.
11 Nítorí pé yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní, ẹ̀ṣẹ̀ tí a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.
Nĩgũkorwo ũndũ ũcio nĩ ũmaramari wa thoni, na nĩ rĩĩhia rĩa gũtuĩrwo ciira nĩ kĩama.
12 Nítorí pé iná ní èyí tí ó jó dé ibi ìparun, tí ìbá sì fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.
Tondũ ũcio nĩ mwaki ũrĩa ũcinaga nginya ũkaananga; na nĩũngĩamunyĩte magetha makwa mothe.
13 “Tí mo bá sì ṣe àìka ọ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi sí, nígbà tí wọ́n bá ń bá mi jà;
“Ingĩkorwo nĩnyimĩte ndungata ciakwa cia arũme na cia andũ-a-nja kĩhooto rĩrĩa manateta nĩ ũndũ wakwa-rĩ,
14 kí ni èmi ó ha ṣe nígbà tí Ọlọ́run bá dìde? Nígbà tí ó bá sì ṣe ìbẹ̀wò, ohùn kí ni èmi ó dá?
niĩ ngeeka atĩa rĩrĩa Mũrungu akaanjũkĩrĩra? Ngaacookia atĩa rĩrĩa ngeetwo ndĩĩtetere ũhoro-inĩ ũcio?
15 Ẹni tí ó dá mi ní inú kọ́ ni ó dá a? Ẹnìkan náà kí ó mọ wá ní inú ìyá wa?
Githĩ ũcio wanyũũmbire kũu nda ya maitũ to we wamoombire? Githĩ tiwe watũthondekire tũrĩ kũu nda cia aa maitũ?
16 “Bí mo bá fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà, tàbí bí mo bá sì mú kí ojú opó rẹ̀wẹ̀sì,
“Ingĩkorwo ndanaima athĩĩni kĩrĩa maanerirĩria, kana ngareka maitho ma mũtũmia wa ndigwa morwo nĩ hinya-rĩ,
17 tàbí tí mo bá nìkan bu òkèlè mi jẹ, tí aláìní baba kò jẹ nínú rẹ̀;
ingĩkorwo ndĩĩaga irio ciakwa nyiki, ngaaga kũgayana na ũrĩa ũtarĩ ithe-rĩ,
18 nítorí pé láti ìgbà èwe mi wá ni a ti tọ́ ọ dàgbà pẹ̀lú mi bí ẹni pé baba, èmi sì ń ṣe ìtọ́jú opó láti inú ìyá mi wá:
(no niĩ kuuma ũnini wakwa, mwana ta ũcio ndaamũreraga o ta ũrĩa angĩarerirwo nĩ ithe, na kuuma gũciarwo gwakwa ndũire ndongoragia mũtumia wa ndigwa)
19 bí èmi bá rí olùpọ́njú láìní aṣọ, tàbí tálákà kan láìní ìbora;
ingĩkorwo ndanoona mũndũ agĩkua nĩ ũndũ wa kwaga nguo, kana ngoona mũndũ mũbatari atarĩ kĩndũ gĩa kwĩhumba,
20 bí ọkàn rẹ̀ kò bá súre fún mi, tàbí bí ara rẹ̀ kò sì gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;
na ngoro yake ndĩandathimire nĩ ũndũ wa kũmũiguithia ũrugarĩ na guoya wa ngʼondu ciakwa-rĩ,
21 bí mo bá sì gbé ọwọ́ mi sókè sí aláìní baba, nítorí pé mo rí ìrànlọ́wọ́ mi ní ẹnu ibodè,
ingĩkorwo ndanoya guoko gwakwa ngookĩrĩra mwana ũtarĩ ithe, nĩkũmenya atĩ no nyone wa kũndeithia kwagĩa ciira igooti-inĩ-rĩ,
22 ǹjẹ́, ní apá mi kí o wọ́n kúrò ní ihò èjìká rẹ̀, kí apá mi kí ó sì ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ wá.
hĩndĩ ĩyo guoko gwakwa kũroahũkĩra kĩande-inĩ kũgwe, kũroinĩkĩra o irũngo-inĩ.
23 Nítorí pé ìparun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ẹ̀rù ńlá fún mi, àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi kò le è dúró.
Nĩ ũndũ nĩndetigagĩra mwanangĩko uumĩte kũrĩ Mũrungu, na nĩ ũndũ wa gwĩtigĩra riiri wake, ndingĩekire maũndũ ta macio.
24 “Bí ó bá ṣe pé mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé mi, tàbí tí mo bá wí fún fàdákà dídára pé, ‘Ìwọ ni ààbò mi,’
“Ingĩkorwo nĩnjigĩte mwĩhoko wakwa harĩ thahabu, kana ngeera thahabu ĩrĩa therie mũno atĩrĩ, ‘Wee nĩwe ũgitĩri wakwa,’
25 bí mo bá yọ̀ nítorí ọrọ̀ mí pọ̀, àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,
ingĩkorwo ndanakenera ũtonga wakwa mũnene, kana ngakenera uumithio ũrĩa moko makwa mecarĩirie-rĩ,
26 bí mo bá bojú wo oòrùn nígbà tí ń ràn, tàbí òṣùpá tí ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,
ingĩkorwo ndanarũmbũiya riũa rĩarĩte, kana mweri ũgĩthiĩ ũcangararĩte,
27 bí a bá tàn ọkàn mi jẹ láti fi ẹnu mi kò ọwọ́ mi,
na ngoro yakwa ĩkĩheenererio nĩcio na hitho, kana guoko gwakwa gũgĩcikinyĩria kĩmumunyano gĩa gũcitĩĩa-rĩ,
28 èyí pẹ̀lú ni ẹ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ ní láti bẹ̀wò, nítorí pé èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run tí ó wà lókè.
o na macio mangĩtuĩka mehia ma gũtuĩrwo ciira, nĩgũkorwo ingĩtuĩkĩte mũndũ ũtarĩ mwĩhokeku harĩ Mũrungu ũrĩa ũrĩ igũrũ.
29 “Bí ó bá ṣe pé mo yọ̀ sì ìparun ẹni tí ó kórìíra mi. Tàbí bí mo bá sì gbéraga sókè, nígbà tí ibi bá a.
“Ingĩkorwo ndaanakena nĩ thũ yakwa kuona mũtino, kana ngĩmĩthekerera rĩrĩa thĩĩna wamĩkora,
30 Bẹ́ẹ̀ èmi kò sì jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀ nípa fífẹ́ ègún sí ọkàn rẹ̀.
no niĩ ndirĩ ndetĩkĩra kanua gakwa keehie na ũndũ wa kũhoera muoyo wayo kĩrumi,
31 Bí àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi kò bá lè wí pé, ‘Ta ni kò ì tí ì jẹ ẹran rẹ̀ ní àjẹyó?’
kũngĩkorwo andũ a nyũmba yakwa matirĩ moiga atĩrĩ, ‘Nũũ ũtarĩ warĩa nyama cia Ayubu akahũũna?’
32 Àlejò kò wọ̀ ni ìgboro rí; èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.
no gũtirĩ mũgeni wanaraara njĩra-inĩ, nĩ ũndũ mũrango wa mũciĩ wakwa ũtũire ũhingũrĩirwo mũgendi,
33 Bí mo bá bò ẹ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ bí Adamu ni pápá, ẹ̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.
ingĩkorwo ndaanahitha mehia makwa, ta ũrĩa andũ meekaga, na ũndũ wa kũhitha mahĩtia ngoro-inĩ yakwa
34 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀rù bí? Tàbí ẹ̀gàn àwọn ìdílé ní ń bà mí ní ẹ̀rù? Tí mo fi pa ẹnu mọ́, tí èmí kò sì fi sọ̀rọ̀ jáde?
tondũ wa gwĩtigĩra kĩrĩndĩ, o na gwĩtigĩra kũmenwo nĩ mĩhĩrĩga ngagĩkira ki na ndiume nja-rĩ,
35 (“Ìbá ṣe pé ẹnìkan le gbọ́ ti èmí! Kíyèsi i, àmì mi, kí Olódùmarè kí ó dá mi lóhùn, kí èmí kí ó sì rí ìwé náà tí olùfisùn mi ti kọ.
(“Naarĩ korwo ndaarĩ na mũndũ wa kũnjigua! Rĩu nĩndekĩra rũũri rwa kwĩyarĩrĩria: reke Mwene-Hinya-Wothe anjookerie ũhoro; reke mũũthitangi andĩke marũa ma thitango yake.
36 Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi, èmi ìbá sì dé bí adé mọ́ orí mi.
Ti-itherũ marũa macio ingĩmaigĩrĩra kĩande, ndĩmehumbe taarĩ thũmbĩ.
37 Èmi ìbá sì sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un, bí ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀.)
Njooke ndĩmũhe ũhoro wakwa ikinya gwa ikinya; ndĩmũkuhĩrĩrie ta ndĩ mũnene.)
38 “Bí ilẹ̀ mi bá sì ké rara lòdì sí mi tí a sì fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.
“Korwo mũgũnda wakwa wakaya, ũnjũkĩrĩre, nayo mĩtaro yaguo yothe ĩkorwo ĩkĩrĩra maithori,
39 Bí mo bá jẹ èso oko mi láìsan owó tàbí tí mo sì mú ọkàn olúwa rẹ̀ fò lọ,
ingĩkorwo ndanarĩa maciaro maguo iteekũrĩha, kana ngoraga ngoro cia ene guo-rĩ,
40 kí ẹ̀gún òṣùṣú kí ó hù dípò alikama, àti èpò búburú dípò ọkà barle.” Ọ̀rọ̀ Jobu parí.
hĩndĩ ĩyo congʼe ũrokũra kuo handũ ha ngano, na riya handũ ha cairi.” Ndeto cia Ayubu nĩciathira.

< Job 31 >