< Job 29 >
1 Pẹ̀lúpẹ̀lú, Jobu sì tún tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé,
Yoube da bu amane sia: i,
2 “Háà! ìbá ṣe pé èmi wà bí ìgbà oṣù tí ó kọjá, bí ọjọ́ tí Ọlọ́run pa mí mọ́,
Gode da musa: na esalusu noga: le ouligi. Na da bu agoane esalumu da defea galu.
3 nígbà tí fìtílà rẹ tàn sí mi ní orí, àti nípa ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ èmi rìn nínú òkùnkùn já.
Amo esoga, Gode da na mae fisili, ani ahoasu. Na da gasi ganodini ahoabeba: le, E da nama hadigi iasu.
4 Bí mo ti rí nígbà ọ̀dọ́ mi, nígbà tí ọ̀rẹ́ Ọlọ́run tímọ́tímọ́ bùkún ilé mi,
Amo esoga na da bagade gaguiwane ba: i. Gode da nama dogolegeiba: le, E da na diasu amola sosogo fi gaga: i.
5 nígbà tí Olódùmarè wà pẹ̀lú mi, nígbà tí àwọn ọmọ mi wà yí mi ká;
Gode Bagadedafa da ani esalu. Amola na mano huluane hahawane nini dafulili lelefulu.
6 nígbà tí èmi fi òrí-àmọ́ n wẹ ìṣísẹ̀ mi, àti tí àpáta ń tú ìṣàn òróró jáde fún mi wá.
Na bulamagau amola goudi, ilia da dodo maga: me bagade i. Amola na olife ifa ilia da igi galoase osobo da: iya noga: le heda: i.
7 “Nígbà tí mo jáde la àárín ìlú lọ sí ẹnu ibodè, nígbà tí mo tẹ́ ìtẹ́ mi ní ìgboro,
Na moilai bai bagade asigilai dunu da sia: sa: imusa: gilisilaloba, na amola da ilima gilisi.
8 nígbà náà ni àwọn ọmọkùnrin rí mi, wọ́n sì sá pamọ́, àwọn àgbà dìde dúró ní ẹsẹ̀ wọn,
Ayeligi dunu da na ba: le, gasigasu. Amola da: i hamoi dunu da nama yosia: musa: , wa: legadosu.
9 àwọn ọmọ-aládé dákẹ́ ọ̀rọ̀ sísọ, wọn a sì fi ọwọ́ wọn lé ẹnu.
Dunu fi ouligisu dunu da naba: le sia: ouiya: su.
10 Àwọn ọlọ́lá dákẹ́, ahọ́n wọn sì lẹ̀ mọ́ èrìgì ẹnu wọn.
Mimogodafa dunu da ouiya: le esalebe ba: su.
11 Nígbà tí etí gbọ́, ó sì súre fún mi, àti nígbà tí ojú sì rí mi, ó jẹ́rìí mi,
Dunu huluane da na hou ba: beba: le, o enoga amo hou nababeba: le, ilia da na hou amoma nodone sia: i.
12 nítorí mo gbà tálákà tí n fẹ́ ìrànlọ́wọ́, àti aláìní baba tí kò sí olùrànlọ́wọ́ fún un.
Hame gagui dunu da digini wele sia: beba: le, na da ili fidisu. Na da guluba: mano amo da fidisu dunu hamedafa gala, ili fidi.
13 Ẹni tí ó ń kìlọ̀ súre fún mi, èmi sì mú àyà opó kọrin fún ayọ̀.
Dunu amo da da: i dioi bagadedafa nabi, ilia da nama nodosu. Amola uda didalo gaga: iwane esaloma: ne, na fidisu.
14 Èmi sì mú òdodo wọ̀ bí aṣọ, ẹ̀tọ́ mi dàbí aṣọ ìgúnwà àti adé ọba.
Na da eso huluane moloidafa hou fawane hamonanu.
15 Mo ṣe ojú fún afọ́jú mo sì ṣe ẹsẹ̀ fún amúnkùn ún.
Na da fedege agoane, si dofoi dunu ilia si agoai galusu, amola emo gasuga: igi dunu ilia emo agoai galusu.
16 Mo ṣe baba fún tálákà; mo ṣe ìwádìí ọ̀ràn àjèjì tí èmi kò mọ̀ rí.
Na da hame gagui dunu ilia eda agoai galusu. Amola ga fi da bidi hamosu ba: loba, na da ilimagai galusu.
17 Mo sì ká eyín ẹ̀rẹ̀kẹ́ ènìyàn búburú, mo sì já ohun ọdẹ náà kúrò ní eyín rẹ̀.
Na da nimi bagade dodona: gi dunu ilia gasa wadela: lesi. Amola dunu amo da iliba: le se nabi, amo gaga: i.
18 “Nígbà náà ni mo rò pé, ‘Èmi yóò kú nínú ilé mi, èmi yóò sì mú ọjọ́ mi pọ̀ sí i bí iyanrìn.
Na da ode bagohame esalumu, amola hahawane na diasuga bogomu dawa: i galu.
19 Gbòǹgbò mi yóò ta kan omi, ìrì yóò sì sẹ̀ ní gbogbo òru sí ara ẹ̀ka mi.
Na da ifa amo ea difi da eso huluane hano defele naha, amola ea amoda amola lubi da eso huluane oubi baeyaga nanegasa, amo defele ba: su.
20 Ògo mi yóò wà ní ọ̀tún ní ọ̀dọ̀ mi, ọrun mi sì padà di tuntun ní ọwọ́ mi.’
Dunu huluane da na houba: le, nodonanusu. Na gasa da hamedafa dafamu agoai ba: su.
21 “Èmi ni ènìyàn ń dẹtí sílẹ̀ sí, wọn a sì dúró, wọn a sì dákẹ́ rọ́rọ́ ní ìmọ̀ràn mi.
Na da fada: i sia: sea, eno dunu da ouiya: lewane nabasu. Ilia da na sia: dawa: iwane nabasu.
22 Lẹ́yìn ọ̀rọ̀ mi, wọn kò tún sọ̀rọ̀ mọ́; ọ̀rọ̀ mi wọ̀ wọ́n ní etí ṣinṣin.
Na da sia: dagoloba, ilia eno sia: mu hamedei ba: su. Na sia: da gibu ea dabe agoai ba: su.
23 Wọn a sì dúró dè mí bí ẹni wí pé wọ́n dúró fún ọ̀wọ́ òjò; wọn a sì mu nínú ọ̀rọ̀ mi bí ẹní mu nínú òjò àrọ̀kúrò.
Ifabi ouligisu dunu da woufo oubi gibu yosia: be, amo defele, dunu huluane da na sia: hahawane nabasu.
24 Èmi sì rẹ́rìn-ín sí wọn nígbà tí wọn kò bá gbà á gbọ́; ìmọ́lẹ̀ ojú mi jẹ́ iyebíye sí wọn.
Ilia da dafawane hamoma: beyale dawa: su fisi dagoi galea, na da ilia dogo denesima: ne, ilima ohomogisu.
25 Mo la ọ̀nà sílẹ̀ fún wọn, mo sì jókòó bí olóyè wọn. Mo jókòó bí ọba ní àárín ológun rẹ, mo sì rí bí ẹni tí ń tu ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ nínú.
Na da ilima ouligisu hou hamone, ilegesu hamosu. Hina bagade da ea dadi gagui wa: i gegemusa: oule ahoabe defele, na da ili bisili oule ahoasu. Amola ilia da heawini da: i dione esalea, na da ilia dogo denesinisisu.