< Job 28 >
1 Nítòótọ́, koto fàdákà ń bẹ, àti ibi tí wọ́n ti máa ń da wúrà.
“Nĩ kũrĩ handũ harĩa betha yenjagwo o na nĩ harĩ handũ harĩa thahabu ĩtheragĩrio.
2 Nínú ilẹ̀ ni à ń gbé ń wa irin, bàbà ni a sì ń dà láti inú òkúta wá.
Kĩgera kĩrutagwo kuuma tĩĩri-inĩ, nakĩo gĩcango kĩrutagwo mahiga-inĩ gĩgatwekio.
3 Ènìyàn ni ó fi òpin si òkùnkùn, ó sì ṣe àwárí ìṣúra láti inú òjìji ikú sí ìhà gbogbo.
Mũndũ nĩkũniina aniinaga nduma; acaragia mahiga macio nginya kũrĩa kũriku mũno, o kũu nduma ĩrĩ ndumanu mũno.
4 Wọ́n wa ihò ilẹ̀ tí ó jì sí àwọn tí ń gbé òkè, àwọn tí ẹsẹ̀ ènìyàn gbàgbé wọ́n rọ́ sí ìsàlẹ̀, wọ́n rọ́ sí ìsàlẹ̀ jìnnà sí àwọn ènìyàn.
Mũndũ atũrĩkagia irima thĩ kũraya na kũrĩa andũ matũũraga, agakinya kũndũ kũrĩa mũndũ aariganĩirwo nĩgũthiiaga; kũu kũraihanĩrĩirie na andũ nĩkuo acunjuuraga akĩereeraga.
5 Bí ó ṣe ti ilẹ̀ ni, nínú rẹ̀ ni oúnjẹ ti ń jáde wá, àti ohun tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ni ó yí padà bi iná;
Thĩ nĩkuo kuumaga irio, no na kũu thĩinĩ mũhuro kũgarũrũkĩte gũkahaana ta gũcinĩtwo na mwaki;
6 òkúta ibẹ̀ ni ibi òkúta safire, o sì ní erùpẹ̀ wúrà.
mahiga-inĩ ma thĩ nĩkuo kuumaga yakuti ĩrĩa ya bururu, na mũthanga wayo ũkoragwo na ngũmba cia thahabu.
7 Ipa ọ̀nà náà ni ẹyẹ kò mọ̀, àti ojú gúnnugún kò rí i rí.
Gũtirĩ nyoni ndĩa-nyama yũĩ gacĩra kau kahithe, na gatirĩ konwo nĩ riitho rĩa hũngũ.
8 Àwọn ẹranko agbéraga kò rìn ibẹ̀ rí, bẹ́ẹ̀ ni kìnnìún tí ń ké ramúramù kò kọjá níbẹ̀ rí.
Nyamũ iria ciĩtĩĩaga itirĩ ciagathiĩra, o na gũtirĩ mũrũũthi ũkageragĩra.
9 Ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé akọ òkúta, ó yí òkè ńlá po láti ìdí rẹ̀ wá.
Guoko kwa mũndũ gũtharĩkagĩra gũkanyiita ihiga rĩa nyaigĩ, na gũkaguũria itina cia irĩma.
10 Ó sì la ipa odò ṣíṣàn nínú àpáta, ojú inú rẹ̀ sì rí ohun iyebíye gbogbo.
Enjaga mungu ũgatũrĩkia rwaro rwa ihiga; maitho make makĩonaga igĩĩna ciaruo ciothe.
11 Ó sì ṣe ìṣàn odò kí ó má ṣe kún àkúnya, ó sì mú ohun tí ó pamọ́ hàn jáde wá sí ìmọ́lẹ̀.
Ethaga itwe cia njũũĩ, na indo iria hithe agaciumĩria ũtheri-inĩ.
12 Ṣùgbọ́n níbo ni á ó gbé wá ọgbọ́n rí, níbo sì ni òye ń gbe?
“No ũũgĩ-rĩ, ũngĩoneka kũ? Ũmenyo ũtũũraga kũ?
13 Ènìyàn kò mọ iye rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni a kò le è rí i ní ilẹ̀ àwọn alààyè.
Mũndũ ndangĩmenya thogora wa ũũgĩ; ndũngĩoneka bũrũri wa arĩa marĩ muoyo.
14 Ọ̀gbun wí pé, “Kò sí nínú mi”; omi òkun sì wí pé, “Kò si nínú mi.”
Kũrĩa kũriku mũno kuugaga atĩrĩ, ‘Ndũrĩ thĩinĩ wakwa’; narĩo iria rĩkoiga atĩrĩ, ‘Ndũrĩ gũkũ gwakwa.’
15 A kò le è fi wúrà rà á, bẹ́ẹ̀ ni a kò le è fi òsùwọ̀n wọn fàdákà ní iye rẹ̀.
Ndũngĩgũrĩka na thahabu ĩrĩa therie mũno, kana thogora waguo ũthimwo na betha.
16 A kò le è fi wúrà Ofiri, tàbí òkúta óníkìsì iyebíye, tàbí òkúta safire díye lé e.
Ndũngĩgũrĩka na thahabu ya Ofiri, kana ũgũrĩke na onigithi ĩrĩa ĩrĩ goro mũno, o na kana yakuti ĩrĩa ya bururu.
17 Wúrà àti òkúta kristali kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni a kò le è fi ohun èlò wúrà ṣe pàṣípàrọ̀ rẹ̀.
Thahabu kana icicio-rĩ, itingĩhota kũgerekanio naguo; o na kana ũkũũranio na mathaga ma thahabu.
18 A kò lè dárúkọ iyùn tàbí òkúta jasperi; iye ọgbọ́n sì ju iyùn lọ.
Maricani kana ngenyekenyi iria cia goro itiagĩrĩire kũgwetanio naguo; thogora wa ũũgĩ ũkĩrĩte wa ruru ĩrĩa ndune.
19 Òkúta topasi ti Kuṣi kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni a kò le fi wúrà dáradára díwọ̀n iye rẹ̀.
Yakuti ya Kushi ndĩngĩigananio naguo; o na ndũngĩgũrĩka na thahabu ĩrĩa therie mũno.
20 Níbo ha ni ọgbọ́n ti jáde wá? Tàbí níbo ni òye ń gbé?
“Hakĩrĩ ũguo-rĩ, ũũgĩ ũngĩkiuma nakũ? Ũmenyo ũtũũraga kũ?
21 A rí i pé, ó fi ara sinko kúrò ní ojú àwọn alààyè gbogbo, ó sì fi ara sin fún ẹyẹ ojú ọ̀run.
Nĩmũhithe kũrĩ maitho ma ciũmbe ciothe iria itũũraga muoyo, ũkahithwo o na nyoni cia rĩera-inĩ.
22 Ibi ìparun àti ikú wí pé, àwa ti fi etí wa gbúròó rẹ̀.
Mwanangĩko na gĩkuũ ciugaga atĩrĩ, ‘No mũhuhu waguo ũkinyĩte matũ-inĩ maitũ.’
23 Ọlọ́run ni ó mọ òye ipa ọ̀nà rẹ̀, òun ni ó sì mọ ibi tí ó ń gbé.
Ngai nĩooĩ njĩra ya gũthiĩ kũrĩa ũrĩ, na nowe wiki ũũĩ kũrĩa ũtũũraga,
24 Nítorí pé ó wòye dé òpin ayé, ó sì rí gbogbo ìsàlẹ̀ ọ̀run,
nĩgũkorwo nĩonaga mũthia wa thĩ, na nĩonaga maũndũ marĩa mothe marĩ rungu rwa igũrũ.
25 láti dà òsùwọ̀n fún afẹ́fẹ́, ó sì fi òsùwọ̀n wọ́n omi.
Rĩrĩa aathimĩire rũhuho nditi yaruo, o na agĩthima maaĩ-rĩ,
26 Nígbà tí ó pàṣẹ fún òjò, tí ó sì la ọ̀nà fún mọ̀nàmọ́ná àrá,
rĩrĩa aarutĩire mbura watho ĩrũmagĩrĩre, na agĩtemera rũheni na marurumĩ njĩra-rĩ,
27 nígbà náà ni ó rí i, ó sì sọ ọ́ jáde; ó pèsè rẹ̀ sílẹ̀, ó sì ṣe ìwádìí rẹ̀ rí.
nake nĩonire ũũgĩ na akĩũthima; aũrũmirie na akĩũthuthuuria.
28 Àti fún ènìyàn ni ó wí pé, “Kíyèsi i, ẹ̀rù Olúwa èyí ni ọgbọ́n, àti láti jáde kúrò nínú ìwà búburú èyí ni òye.”
Agĩcooka akĩĩra andũ atĩrĩ, ‘Gwĩtigĩra Mwathani-rĩ, ũcio nĩguo ũũgĩ, Nakuo gũtheemaga ũũru nĩ ũmenyo.’”