< Job 22 >

1 Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani, dáhùn wí pé,
Nake Elifazu ũrĩa Mũtemaani agĩcookia atĩrĩ:
2 “Ènìyàn lè è ṣe rere fún Ọlọ́run? Bí ọlọ́gbọ́n ti í ṣe rere fún ara rẹ̀?
“Mũndũ aahota kũguna Mũrungu? O na mũndũ mũũgĩ-rĩ, akĩhota kũmũguna?
3 Ohun ayọ̀ ha ni fún Olódùmarè pé olódodo ni ìwọ? Tàbí èrè kí ni fún un ti ìwọ mú ọ̀nà rẹ̀ pé?
Nĩ gĩkeno kĩrĩkũ ũthingu waku ũngĩrehere Mwene-Hinya-Wothe? Nĩ uumithio ũrĩkũ angĩgĩa naguo angĩkorwo mĩthiĩre yaku ndĩrĩ ũcuuke?
4 “Yóò ha bá ọ wí bí, nítorí ìbẹ̀rù Ọlọ́run rẹ? Yóò ha bá ọ lọ sínú ìdájọ́ bí?
“Arakũrũithia na agagũthitanga nĩ ũndũ wa wĩtigĩri Ngai waku?
5 Ìwà búburú rẹ kò ha tóbi, àti ẹ̀ṣẹ̀ rẹ láìníye?
Githĩ waganu waku ti mũnene? Mehia maku-rĩ, makĩrĩ mũthia?
6 Nítòótọ́ ìwọ béèrè fún ààbò ni ọwọ́ arákùnrin rẹ láìnídìí, ìwọ sì tú oníhòhò ní aṣọ wọn.
Wetirie ũgitĩri kuuma kũrĩ ariũ a thoguo hatarĩ gĩtũmi; nĩwaũrire andũ nguo, ũkĩmatiga njaga.
7 Ìwọ kò fi omi fún aláàárẹ̀ mu, ìwọ sì háwọ́ oúnjẹ fún ẹni tí ebi ń pa.
Arĩa anogu ndwamaheire maaĩ, na nĩwaimire arĩa ahũtu irio,
8 Bí ó ṣe ti alágbára nì, òun ni ó ní ilẹ̀, ọlọ́lá sì tẹ̀dó sínú rẹ̀.
o na gũtuĩka warĩ mũndũ ũrĩ hinya, ũrĩ na mĩgũnda: mũndũ ũheetwo gĩtĩĩo, na watũũraga kuo.
9 Ìwọ ti rán àwọn opó padà lọ ní ọwọ́ òfo, apá àwọn ọmọ aláìní baba ti di ṣiṣẹ́.
Nĩwaingatire atumia a ndigwa matarĩ na kĩndũ, na ũkĩniina hinya wa arĩa matarĩ na maithe.
10 Nítorí náà ni ìdẹ̀kùn ṣe yí ọ káàkiri, àti ìbẹ̀rù òjijì ń yọ ọ́ lẹ́nu.
Nĩkĩo ũthiũrũrũkĩirio nĩ mĩtego, nĩkĩo thĩĩna wa narua ũkũmakagia,
11 Èéṣe tí òkùnkùn fi pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ kò fi lè ríran. Èéṣe tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi sì bò ọ́ mọ́lẹ̀.
nĩkĩo ũtumanĩirwo nĩ nduma, ũkaremwo nĩkuona, na nokĩo mũiyũro wa maaĩ ũkũhubanĩirie.
12 “Ọlọ́run kò ha jẹ́ ẹni gíga ọ̀run? Sá wo orí àwọn ìràwọ̀ bí wọ́n ti ga tó!
“Githĩ Ngai ndarĩ o kũu igũrũ o igũrũ? O na ta kĩone ũrĩa njata iria irĩ igũrũ mũno itũũgĩrĩte!
13 Ìwọ sì wí pé, Ọlọ́run ti ṣe mọ̀? Òun ha lè ṣe ìdájọ́ láti inú òkùnkùn wá bí?
No rĩrĩ, wee ũroiga atĩrĩ, ‘Mũrungu nĩ atĩa angĩmenya? No atuanĩre ciira nduma-inĩ ta ĩno?
14 Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ tí ó nípọn jẹ ìbora fún un, tí kò fi lè ríran; ó sì ń rìn nínú àyíká ọ̀run.
Matu matumanu nĩmamũhumbĩrĩte, nĩ ũndũ ũcio ndangĩtuona rĩrĩa egũceera kũu igũrũ gacũmbĩrĩ.’
15 Ǹjẹ́ ìwọ fẹ́ rin ipa ọ̀nà ìgbàanì tí àwọn ènìyàn búburú tí rìn?
Ũgũtũũra ũgeraga o njĩra ya tene ĩrĩa andũ aaganu managerera?
16 A ké wọn lulẹ̀ kúrò nínú ayé láìpé ọjọ́ wọn, ìpìlẹ̀ wọn ti da bí odò ṣíṣàn.
Nĩmahuririo ihinda rĩao rĩtanakinya, mĩthingi yao ĩgĩthererio nĩ mũiyũro wa maaĩ.
17 Àwọn ẹni tí ó wí fún Ọlọ́run pé, ‘Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa! Kí ni Olódùmarè yóò ṣe fún wọn?’
Nao meerire Mũrungu atĩrĩ, ‘Tigana na ithuĩ! Mwene-Hinya-Wothe-rĩ, angĩtwĩka atĩa?’
18 Síbẹ̀ ó fi ohun rere kún ilé wọn! Ṣùgbọ́n ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà sí mi!
No rĩrĩ, nĩwe waiyũririe nyũmba ciao na indo njega, nĩ ũndũ ũcio niĩ njikaraga haraaya na kĩrĩra kĩa andũ arĩa aaganu.
19 Àwọn olódodo rí ìparun wọn, wọ́n sì yọ̀, àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀ sì fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà pé,
“Andũ arĩa athingu nĩmeyonagĩra mwanangĩko wa acio aaganu, magakena; arĩa matarĩ na ũũru mekĩte mamanyũrũragia makiugaga atĩrĩ:
20 ‘Lóòtítọ́ àwọn ọ̀tá wa ni a ké kúrò, iná yóò sì jó oró wọn run.’
‘Ti-itherũ thũ ciitũ nĩnyanange, mwaki nĩũcinĩte ũtonga wao.’
21 “Fa ara rẹ súnmọ́ Ọlọ́run, ìwọ ó sì rí àlàáfíà; nípa èyí ni rere yóò wá bá ọ.
“Athĩkĩra Ngai ũikare ũrĩ na thayũ nake, ũndũ ũyũ nĩguo ũgaakũrehere ũgaacĩru.
22 Èmi bẹ̀ ọ́, gba òfin láti ẹnu rẹ̀ wá, kí o sì to ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí àyà rẹ.
Ĩtĩkĩra ũrutani wa kanua gake, na ũige ciugo ciake ngoro-inĩ yaku.
23 Bí ìwọ bá yípadà sọ́dọ̀ Olódùmarè, a sì gbé ọ ró. Bí ìwọ bá sì mú ẹ̀ṣẹ̀ jìnnà réré kúrò nínú àgọ́ rẹ,
Ũngĩcookerera ũcio Mwene-Hinya-Wothe, nĩegũkwamũkĩra; ũngĩeheria waganu kũraya na hema yaku,
24 tí ìwọ bá tẹ́ wúrà dáradára sílẹ̀, lórí erùpẹ̀ àti wúrà Ofiri lábẹ́ òkúta odò,
na ũte ngũmba ciaku cia thahabu rũkũngũ-inĩ, na thahabu yaku ya Ofiri ũmĩte na kũu ndwaro-inĩ cia mahiga kũu mũkuru-inĩ,
25 nígbà náà ní Olódùmarè yóò jẹ́ wúrà rẹ, àní yóò sì jẹ́ fàdákà fún ọ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
hĩndĩ ĩyo ũcio Mwene-Hinya-Wothe agaatuĩka thahabu yaku, na atuĩke betha ĩrĩa njega mũno harĩ we.
26 Lóòtítọ́ nígbà náà ní ìwọ ó ní inú dídùn nínú Olódùmarè, ìwọ ó sì gbé ojú rẹ sókè sọ́dọ̀ Ọlọ́run.
Ti-itherũ, hĩndĩ ĩyo nĩũkona gĩkeno thĩinĩ wa ũcio Mwene-Hinya-Wothe, na nĩũgatiirĩra Ngai ũthiũ waku.
27 Bí ìwọ bá gbàdúrà rẹ sọ́dọ̀ rẹ̀, yóò sì gbọ́ tìrẹ, ìwọ ó sì san ẹ̀jẹ́ rẹ.
Nĩũkamũhooya, nake nĩagakũigua, nawe nĩũkahingia mĩĩhĩtwa yaku.
28 Ìwọ ó sì gbìmọ̀ ohun kan pẹ̀lú, yóò sì fi ìdí múlẹ̀ fún ọ; ìmọ́lẹ̀ yóò sì mọ́ sípa ọ̀nà rẹ.
Ũrĩa watua wĩkwo nĩguo ũrĩkagwo, naguo ũtheri nĩ ũkaara njĩra-inĩ ciaku.
29 Nígbà tí ipa ọ̀nà rẹ bá lọ sísàlẹ̀, nígbà náà ni ìwọ o wí pé, ‘Ìgbésókè ń bẹ!’ Ọlọ́run yóò sì gba onírẹ̀lẹ̀ là!
Hĩndĩ ĩrĩa andũ angĩ manyiihio, nawe ũkoiga, ‘Nĩmatũũgĩrio!’ Hĩndĩ ĩyo nĩakahonokia arĩa makuĩte ngoro.
30 Yóò gba ẹni tí kì í ṣe aláìjẹ̀bi là, a ó sì gbà á nípa mímọ́ ọwọ́ rẹ̀.”
Nĩakahonokia o na ũrĩa ũrĩ na ũcuuke, ahonokio nĩ ũndũ wa ũtheru wa moko maku.”

< Job 22 >