< Job 2 >

1 Ó sì tún di ọjọ́ kan nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run wá síwájú Olúwa, Satani sì wá pẹ̀lú wọn láti pe níwájú Olúwa.
І сталося одно́го дня, і поприхо́дили Божі сини, щоб стати перед Господом; і прийшов також сатана́ поміж ними, щоб стати перед Господом.
2 Olúwa sì bi Satani pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?” Satani sì dá Olúwa lóhùn pé, “Láti lọ síwá sẹ́yìn lórí ilẹ̀ ayé àti ní ìrìnkèrindò nínú rẹ̀.”
І сказав Господь до сатани́: „Звідки ти йдеш?“А сатана́ відповів Господе́ві й сказав: „Я мандрував по землі та й перейшов її“.
3 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Ìwọ ha kíyèsi Jobu ìránṣẹ́ mi, pé, kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ̀ ní ayé, ọkùnrin tí ń ṣe olóòtítọ́ tí ó sì dúró ṣinṣin, ẹni tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run, tí ó sì kórìíra ìwà búburú, bẹ́ẹ̀ ni ó sì di ìwà òtítọ́ rẹ̀ mu ṣinṣin, bí ìwọ tilẹ̀ ti dẹ mí sí i láti run ún láìnídìí.”
І сказав Господь до сатани́: „Чи звернув ти увагу на раба Мого Йо́ва? Бо немає такого, як він, на землі: муж він невинний та праведний, який Бога боїться, а від злого втікає. І він ще тримається міцно в своїй невинності, а ти намовляв був Мене на нього, щоб без при́воду його зруйнувати“.
4 Satani sì dá Olúwa lóhùn wí pé, “Awọ fún awọ; àní ohun gbogbo tí ènìyàn ní, òun ni yóò fi ra ẹ̀mí rẹ̀.
І відповів сатана Господе́ві й сказав: „Шкіра за шкіру, і все, що хто має, віддасть він за душу свою.
5 Ṣùgbọ́n nawọ́ rẹ nísinsin yìí, kí ó tọ́ egungun rẹ̀ àti ara rẹ̀, bí kì yóò sì bọ́hùn ní ojú rẹ.”
Але простягни но Ти руку Свою, і доторкнись до косте́й його та до тіла його, — чи він не зневажить Тебе перед лицем Твоїм?“
6 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Wò ó, ó ń bẹ ní ìkáwọ́ rẹ, ṣùgbọ́n dá ẹ̀mí rẹ̀ sí.”
І сказав Господь до сатани: „Ось він у руці твоїй, — тільки душу його бережи!“
7 Bẹ́ẹ̀ ni Satani jáde lọ kúrò níwájú Olúwa, ó sì sọ Jobu ní oówo kíkankíkan láti àtẹ́lẹsẹ̀ títí dé àtàrí rẹ̀.
І вийшов сатана від лиця Господнього, та й ударив Йова злим гнояко́м від стопи́ ноги́ його аж до його че́репа.
8 Ó sì mú àpáàdì, ó fi ń họ ara rẹ̀, ó sì jókòó nínú eérú. (questioned)
А той узяв собі черепка́, щоб шкре́бти себе. І він сидів серед по́пелу.
9 Nígbà náà ni aya rẹ̀ wí fún un pé, “Ìwọ di ìwà òtítọ́ mú síbẹ̀! Bú Ọlọ́run, kí ó sì kú!”
І сказала йому його жінка: „Ти ще міцно тримаєшся в невинності своїй? Прокляни Бога — і помреш!“
10 Ṣùgbọ́n ó dá a lóhùn pé, “Ìwọ sọ̀rọ̀ bí ọ̀kan lára àwọn aṣiwèrè obìnrin ti í sọ̀rọ̀; há bà! Àwa yóò ha gba ìre lọ́wọ́ Ọlọ́run, kí a má sì gba ibi?” Nínú gbogbo èyí, Jobu kò fi ètè rẹ̀ ṣẹ̀.
А він до неї відказав: „Ти гово́риш отак, як гово́рить яка з божеві́льних! Чи ж ми бу́дем приймати від Бога добре, а злого не при́ймем?“При всьому тому Йов не згрішив своїми устами.
11 Nígbà tí àwọn ọ̀rẹ́ Jobu mẹ́ta gbúròó gbogbo ibi tí ó bá a, wọ́n wá, olúkúlùkù láti ibùjókòó rẹ̀; Elifasi, ara Temani àti Bilidadi, ará Ṣuhi, àti Sofari, ará Naama: nítorí pé wọ́n ti dájọ́ ìpàdé pọ̀ láti bá a ṣọ̀fọ̀, àti láti ṣìpẹ̀ fún un.
I почули троє при́ятелів Йо́вових про все те нещастя, що прийшло на нього, і поприхо́дили кожен з місця свого: теманя́нин Еліфа́з, шух'я́нин Бідда́д та наама́тянин Цофа́р. І вмовилися вони прийти ра́зом, щоб похитати головою над ним та поті́шити його.
12 Nígbà tí wọ́n gbójú wọn wò ní òkèrè réré, tí wọ́n kò sì mọ̀ ọ́n, wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún: olúkúlùkù sì fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya, wọ́n sì ku erùpẹ̀ sí ojú ọ̀run, wọ́n sì tẹ́ orí gbà á.
І звели́ вони зда́лека очі свої, — і не пізна́ли його. І підне́сли вони голос свій, та й заголоси́ли, і розде́рли кожен одежу свою, і кидали по́рох над своїми головами аж до неба.
13 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n jókòó tì í ní inú erùpẹ̀ ní ọjọ́ méje ti ọ̀sán ti òru, ẹnikẹ́ni kò sì bá a sọ ọ̀rọ̀ kan, nítorí tí wọ́n ti rí i pé ìbànújẹ́ rẹ̀ pọ̀ jọjọ.
І сиділи вони з ним на землі сім день та сім ноче́й, і ніхто не промо́вив до нього ні слова, бо вони ба́чили, що біль його ве́льми великий

< Job 2 >