< Job 2 >
1 Ó sì tún di ọjọ́ kan nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run wá síwájú Olúwa, Satani sì wá pẹ̀lú wọn láti pe níwájú Olúwa.
Фиий луй Думнезеу ау венит ынтр-о зи де с-ау ынфэцишат ынаинтя Домнулуй. Ши а венит ши Сатана ын мижлокул лор ши с-а ынфэцишат ынаинтя Домнулуй.
2 Olúwa sì bi Satani pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?” Satani sì dá Olúwa lóhùn pé, “Láti lọ síwá sẹ́yìn lórí ilẹ̀ ayé àti ní ìrìnkèrindò nínú rẹ̀.”
Домнул а зис Сатаней: „Де унде вий?” Ши Сатана а рэспунс Домнулуй: „Де ла кутреераря пэмынтулуй ши де ла плимбаря пе каре ам фэкут-о пе ел.”
3 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Ìwọ ha kíyèsi Jobu ìránṣẹ́ mi, pé, kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ̀ ní ayé, ọkùnrin tí ń ṣe olóòtítọ́ tí ó sì dúró ṣinṣin, ẹni tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run, tí ó sì kórìíra ìwà búburú, bẹ́ẹ̀ ni ó sì di ìwà òtítọ́ rẹ̀ mu ṣinṣin, bí ìwọ tilẹ̀ ti dẹ mí sí i láti run ún láìnídìí.”
Домнул а зис Сатаней: „Ай вэзут пе робул Меу Йов? Ну есте нимень ка ел пе пэмынт. Есте ун ом фэрэ приханэ ши курат ла суфлет. Ел се теме де Думнезеу ши се абате де ла рэу. Ел се цине таре ын неприхэниря луй, ши ту Мэ ындемнь сэ-л перд фэрэ причинэ.”
4 Satani sì dá Olúwa lóhùn wí pé, “Awọ fún awọ; àní ohun gbogbo tí ènìyàn ní, òun ni yóò fi ra ẹ̀mí rẹ̀.
Ши Сатана а рэспунс Домнулуй: „Пеле пентру пеле! Омул дэ тот че аре пентру вяца луй.
5 Ṣùgbọ́n nawọ́ rẹ nísinsin yìí, kí ó tọ́ egungun rẹ̀ àti ara rẹ̀, bí kì yóò sì bọ́hùn ní ojú rẹ.”
Дар я ынтинде-Ць мына ши атинӂе-Те де оаселе ши де карня луй, ши сунт ынкрединцат кэ Те ва блестема ын фацэ.”
6 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Wò ó, ó ń bẹ ní ìkáwọ́ rẹ, ṣùgbọ́n dá ẹ̀mí rẹ̀ sí.”
Домнул а зис Сатаней: „Ятэ, ци-л дау пе мынэ: нумай круцэ-й вяца.”
7 Bẹ́ẹ̀ ni Satani jáde lọ kúrò níwájú Olúwa, ó sì sọ Jobu ní oówo kíkankíkan láti àtẹ́lẹsẹ̀ títí dé àtàrí rẹ̀.
Ши Сатана а плекат динаинтя Домнулуй. Апой а ловит пе Йов ку о бубэ ря, дин талпа пичорулуй пынэ ын крештетул капулуй.
8 Ó sì mú àpáàdì, ó fi ń họ ara rẹ̀, ó sì jókòó nínú eérú. ()
Ши Йов а луат ун чоб сэ се скарпине ши а шезут пе ченушэ.
9 Nígbà náà ni aya rẹ̀ wí fún un pé, “Ìwọ di ìwà òtítọ́ mú síbẹ̀! Bú Ọlọ́run, kí ó sì kú!”
Невастэ-са й-а зис: „Ту рэмый неклинтит ын неприхэниря та! Блестемэ пе Думнезеу ши морь!”
10 Ṣùgbọ́n ó dá a lóhùn pé, “Ìwọ sọ̀rọ̀ bí ọ̀kan lára àwọn aṣiwèrè obìnrin ti í sọ̀rọ̀; há bà! Àwa yóò ha gba ìre lọ́wọ́ Ọlọ́run, kí a má sì gba ibi?” Nínú gbogbo èyí, Jobu kò fi ètè rẹ̀ ṣẹ̀.
Дар Йов й-а рэспунс: „Ворбешть ка о фемее небунэ. Че, примим де ла Думнезеу бинеле ши сэ ну примим ши рэул?” Ын тоате ачестя, Йов н-а пэкэтуит делок ку бузеле луй.
11 Nígbà tí àwọn ọ̀rẹ́ Jobu mẹ́ta gbúròó gbogbo ibi tí ó bá a, wọ́n wá, olúkúlùkù láti ibùjókòó rẹ̀; Elifasi, ara Temani àti Bilidadi, ará Ṣuhi, àti Sofari, ará Naama: nítorí pé wọ́n ti dájọ́ ìpàdé pọ̀ láti bá a ṣọ̀fọ̀, àti láti ṣìpẹ̀ fún un.
Трей приетень ай луй Йов, Елифаз дин Теман, Билдад дин Шуах ши Цофар дин Наама, ау афлат де тоате ненорочириле каре-л ловисерэ. С-ау сфэтуит ши ау плекат де акасэ сэ се дукэ сэ-й плынгэ де милэ ши сэ-л мынгые.
12 Nígbà tí wọ́n gbójú wọn wò ní òkèrè réré, tí wọ́n kò sì mọ̀ ọ́n, wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún: olúkúlùkù sì fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya, wọ́n sì ku erùpẹ̀ sí ojú ọ̀run, wọ́n sì tẹ́ orí gbà á.
Ридикынду-шь окий де департе, ну л-ау май куноскут. Ши ау ридикат гласул ши ау плынс. Шь-ау сфышият манталеле ши ау арункат ку цэрынэ ын вэздух дясупра капетелор лор.
13 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n jókòó tì í ní inú erùpẹ̀ ní ọjọ́ méje ti ọ̀sán ti òru, ẹnikẹ́ni kò sì bá a sọ ọ̀rọ̀ kan, nítorí tí wọ́n ti rí i pé ìbànújẹ́ rẹ̀ pọ̀ jọjọ.
Ши ау шезут пе пэмынт, лынгэ ел, шапте зиле ши шапте нопць, фэрэ сэ-й спунэ о ворбэ, кэч ведяу кыт де маре ый есте дуреря.