< Job 17 >

1 “Ẹ̀mí mi bàjẹ́, ọjọ́ mi ni a ti gé kúrú, isà òkú dúró dè mí.
Na esalusu fisimu eso da gadenesa. Na mifo heda: mu da gadenenewane gogolei. Na da liligi eno hamomu da hamedei, bogomusa: fawane esala.
2 Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi, ojú mi sì tẹ̀mọ́ ìmúnibínú wọn.
Na da ba: lala. Dunu huluane da na ha: giwane habosesesa.
3 “Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́; ta ni yóò le ṣe ààbò fún mi?
Gode! Na da dafawane sia: sa! Na sia: nabima! Na sia: be fuligala: su dunu eno da hame.
4 Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye; nítorí náà ìwọ kì yóò gbé wọn lékè.
Di da eno dunu ilia asigi dawa: su gogolelesibiba: le, ilia moloidafa hou hame dawa: Ilia da na mae hasalima: ne, ilia logo Dia hedofama.
5 Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè, òun ni ojú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò mú òfo.
Musa: malasu sia: amogai dunu afae da muni lamusa: , ea na: iyado hohonoi. Amola ea hamobeba: le, ea mano huluane da se nabi.
6 “Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn; níwájú wọn ni mo dàbí ẹni ìtutọ́ sí ní ojú.
Amola wali, dunu ilia amo malasu defele, na hamoi ilia sia: sa. Ilia da misini, na odagia defo adugagala: sa.
7 Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́, gbogbo ẹ̀yà ara mi sì dàbí òjìji.
Na da da: i dioiba: le, na si da wadela: mu gadenesa. Na lobo amola emo da geloga: le, baba agoai ba: sa.
8 Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí, ẹni aláìṣẹ̀ sì bínú sí àwọn àgàbàgebè.
Dunu mogili, ilia hou da moloidafa ilisu sia: sa, amo ilia na hou ba: beba: le fofogadigisa. Ilia da na da Gode Ea hou hamedafa dawa: sia: sa.
9 Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú, àti ọlọ́wọ́ mímọ́ yóò máa lera síwájú.
Dunu amo da ilia hou da noga: idafa ilisu sia: sa, ilia amola da na Gode Ea hou hame dawa: sia: sa. Amola ilia dawa: i da dafawane ilia dawa: sa.
10 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín, ẹ yípadà, kí ẹ si tún padà nísinsin yìí; èmi kò le rí ọlọ́gbọ́n kan nínú yín.
Be ilia huluane da na midadi misini aliligisia ganiaba, na da iliga dunu afae bagade dawa: su galebe hamedafa ba: la: loba.
11 Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá, àní ìrò ọkàn mi.
Na hamomu eso da baligi dagoi. Na hamomusa: ilegei da bugi. Na hobea misunu hou dafawane hamoma: beyale dawa: su da fisi dagoi.
12 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán; wọ́n ní, ìmọ́lẹ̀ súnmọ́ ibi tí òkùnkùn dé.
Be na na: iyado dunu ilia da gasi amo da hadigi sia: sa. Ilia da hadigi da gadenei sia: sa. Be na dawa: , na da gasi ganodini esala.
13 Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi; mo ti tẹ́ ibùsùn mi sínú òkùnkùn. (Sheol h7585)
Nama hobea misunu dafawane hamoma: beyale hou dawa: be da bogosu soge fawane dawa: sa. Amogawi na gasi ganodini dialumu. (Sheol h7585)
14 Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi, àti fún kòkòrò pé, ìwọ ni ìyá mi àti arábìnrin mi,
Na da bogoi uli dogoi amoma na da na ada dio asulimu. Amola daba: amo da na da: i nabe, amoma, “Na ame amola na dalusi,” na da sia: mu.
15 ìrètí mi ha dà nísinsin yìí? Bí ó ṣe ti ìrètí mi ni, ta ni yóò rí i?
Na hobea misunu hou dafawane hamoma: beyale dawa: su da habidili ganabela: ? Nowa da amo ba: sala: ?
16 Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú, nígbà tí a jùmọ̀ sinmi pọ̀ nínú erùpẹ̀ ilẹ̀?” (Sheol h7585)
Na da bogoi dunu ilia sogega gudu dasea, hobea misunu hou hahawane hamoma: beyale dawa: su da na gilisili hame masunu.” (Sheol h7585)

< Job 17 >