< Job 16 >
1 Ìgbà náà ní Jobu dáhùn, ó sì wí pé,
A LAILA olelo mai la o Ioba, i mai la,
2 “Èmi ti gbọ́ irú ohun púpọ̀ bẹ́ẹ̀ rí ayọnilẹ́nu onítùnú ènìyàn ní gbogbo yín.
He nui na mea like a'u i lohe ai: He poe hooluolu hoopilikia oukou a pau.
3 Ọ̀rọ̀ asán lè ni òpin? Tàbí kí ni ó gbó ọ láyà tí ìwọ fi dáhùn?
He hope anei no na huaolelo makani? Heaha ka mea hoala mai nei ia oe, i olelo mai ai oe?
4 Èmi pẹ̀lú le sọ bí ẹ̀yin; bí ọkàn yín bá wà ní ipò ọkàn mi, èmi le sọ ọ̀rọ̀ dáradára púpọ̀ sí yín ní ọrùn, èmi a sì mi orí mi sí i yín.
E hiki no ia'u ke olelo aku e like me ka oukou; Ina paha ua noho oukou ma ko'u wahi. E hiki no ia'u ke hookui i ka olelo ku e ia oukou; A e hooluliluli aku i ko'u poo ia oukou.
5 Èmi ìbá fi ọ̀rọ̀ ẹnu mi gbà yín ni ìyànjú, àti ṣíṣí ètè mi ìbá sì tu ìbìnújẹ́ yín.
Aka, e hookupaa no au ia oukou me kuu waha, A o ka hooluolu ana o kuu lehelehe, e hoopaa aku no ia.
6 “Bí èmi tilẹ̀ sọ̀rọ̀, ìbìnújẹ́ mi kò lọ; bí mo sì tilẹ̀ dákẹ́, níbo ni ìtùnú mí ko kúrò?
Ina e olelo aku au, aole e oluolu kuu eha; Ina e noho malie hoi au, pehea ia e haalele ai ia'u?
7 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó dá mi lágara; ìwọ Ọlọ́run mú gbogbo ẹgbẹ́ mi takété.
Aka, ano ua hooluhi mai ia ia'u; Ua luku mai oe i ko'u ohana a pau.
8 Ìwọ fi ìhunjọ kùn mí lára, èyí tí o jẹ́rìí tì mí; àti rírù tí ó hàn lára mi, ó jẹ́rìí tì mí ní ojú.
Ua hoopaa mai oe ia'u, i mea hoike; O kuu wiwi, ke ku mai no ia ia'u, A e hoike mai imua o kuu maka.
9 Ọlọ́run fi i ìbínú rẹ̀ fà mí ya, ó sì gbóguntì mí; ó pa eyín rẹ̀ keke sí mi, ọ̀tá mi sì gbójú rẹ̀ sí mi.
Ke haehae mai nei kona huhu, a ua inaina mai ia ia'u; Ke nau mai nei ia ia'u me kona mau niho; O kuu enemi, ke hookala nei ia i kona mau maka maluna o'u.
10 Wọ́n ti fi ẹnu wọn yẹ̀yẹ́ mi; Wọ́n gbá mi ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ ni ìgbá ẹ̀gàn; wọ́n kó ara wọn pọ̀ sí mi.
Ua hamama lakou maluna o'u me ko lakou waha; Ua papai lakou ia'u ma ka papalina me ka hoino: Ua hoakoakoaia lakou ma kahi hookahi e ku e ia'u.
11 Ọlọ́run ti fi mí lé ọwọ́ ẹni búburú, ó sì mú mi ṣubú sí ọwọ́ ènìyàn ìkà.
Ua hoolilo ke Akua ia'u i ka poe hewa, A ua haawi ia'u iloko o ka lima o ka poe aia.
12 Mo ti jókòó jẹ́ẹ́, ṣùgbọ́n ó fà mí já; ó sì dì mí ni ọrùn mú, ó sì gbọ̀n mí túútúú, ó sì gbé mi kalẹ̀ láti ṣe àmì ìtafàsí rẹ̀;
I noho maluhia la no wan, aka, ua ulupa mai nei ia ia'u; Ua lalau mai ia ma kuu a-i, a ulupa mai no ia ia'u, Ua hooku mai ia'u i hoailona nona.
13 àwọn tafàtafà rẹ̀ dúró yí mi káàkiri. Ó là mí láyà pẹ̀rẹ̀, kò si dá sí, ó sì tú òróòro ara mi dà sílẹ̀.
Ua hoopuni kona poe panapua ia'u, Ua wahi mai ia i na puupaa o'u, aole e hookuu ae; Ua ninini iho ia i kuu au ma ka honua.
14 Ìbàjẹ́ lórí ìbàjẹ́ ní ó fi bà mí jẹ́; ó súré kọlù mi bí jagunjagun.
Ua wawahi roai ia ia'u, me ka wahi ana mahope o ka wahi ana, Ua lele mai ia maluna o'u me he mea ikaika la.
15 “Mo rán aṣọ ọ̀fọ̀ bò ara mi, mo sì rẹ̀ ìwo mi sílẹ̀ nínú erùpẹ̀.
Ua humuhumu au i ke kapa ino maluna o kuu ili, Ua hoohaumia au i kuu pepeiaohao iloko o ka lepo.
16 Ojú mi ti pọ́n fún ẹkún, òjìji ikú sì ṣẹ́ sí ìpéǹpéjú mi.
Ua ulaula kuu maka i ka uwe ana, A maluna o ko'u mau lihilihi maka ke aka o ka make.
17 Kì í ṣe nítorí àìṣòótọ́ kan ní ọwọ́ mi; àdúrà mi sì mọ́ pẹ̀lú.
Aole no ka mea pono ole iloko o ko'u lima; A o ka'u pule, ua maemae hoi ia.
18 “Háà! Ilẹ̀ ayé, ìwọ má ṣe bò ẹ̀jẹ̀ mi, kí ẹkún mi má ṣe wà ní ipò kan.
E ka honua, mai uhi oe i ko'u koko, Aole hoi e haawi i wahi no kuu uwe ana.
19 Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi i, ẹlẹ́rìí mi ń bẹ ní ọ̀run, ẹ̀rí mi sì ń bẹ lókè ọ̀run.
Ano hoi, aia ma ka lani kuu mea ike maka, A o kuu mea hoike ma na wahi kiekie.
20 Àwọn ọ̀rẹ́ mi ń fi mí ṣẹ̀sín, ṣùgbọ́n ojú mi ń da omijé sọ́dọ̀ Ọlọ́run,
O kuu poe hoino, o ko'u mau makamaka no ia: Ke hu aku nei kuu maka i ke Akua.
21 ìbá ṣe pé ẹnìkan le è máa ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì lọ́dọ̀ Ọlọ́run, bí ènìyàn kan ti í ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì rẹ̀.
Ina he mea e uwao me ke Akua no ke kanaka, E like me ke kanaka no kona hoalauna!
22 “Nítorí nígbà tí iye ọdún díẹ̀ rékọjá tán, nígbà náà ni èmi ó lọ sí ibi tí èmi kì yóò padà bọ̀.”
A hala he hapa na makahiki, Alaila e hele aku au i ke ala aole au e hoi hou mai.