< Job 16 >

1 Ìgbà náà ní Jobu dáhùn, ó sì wí pé,
Ningĩ Ayubu agĩcookia atĩrĩ:
2 “Èmi ti gbọ́ irú ohun púpọ̀ bẹ́ẹ̀ rí ayọnilẹ́nu onítùnú ènìyàn ní gbogbo yín.
“Nĩnjiguĩte maũndũ maingĩ ta macio; inyuothe mũrĩ ahoorerania a kũnyamarania!
3 Ọ̀rọ̀ asán lè ni òpin? Tàbí kí ni ó gbó ọ láyà tí ìwọ fi dáhùn?
Mĩario ĩyo yanyu mĩingĩ ya mũhũhũtĩko-rĩ, ndĩrĩĩthira? Nĩ kĩĩ kĩramũthĩĩnia, gĩgatũma mũtinde mũgĩkararania?
4 Èmi pẹ̀lú le sọ bí ẹ̀yin; bí ọkàn yín bá wà ní ipò ọkàn mi, èmi le sọ ọ̀rọ̀ dáradára púpọ̀ sí yín ní ọrùn, èmi a sì mi orí mi sí i yín.
O na niĩ no njarie ta inyuĩ, korwo nĩ inyuĩ mũrĩ harĩa ndĩ; niĩ no njarie mĩario mĩega ya kũmũciirithia na ndĩmũinainĩrie mũtwe.
5 Èmi ìbá fi ọ̀rọ̀ ẹnu mi gbà yín ni ìyànjú, àti ṣíṣí ètè mi ìbá sì tu ìbìnújẹ́ yín.
No rĩrĩ, kanua gakwa no kamũũmĩrĩrie; ũhoorerania uumĩte mĩromo-inĩ yakwa no ũmũhoorerie.
6 “Bí èmi tilẹ̀ sọ̀rọ̀, ìbìnújẹ́ mi kò lọ; bí mo sì tilẹ̀ dákẹ́, níbo ni ìtùnú mí ko kúrò?
“No o na ndaaria-rĩ, ruo rwakwa rũtirathira; o na ndegirĩrĩria kwaria-rĩ, rũtiranjeherera.
7 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó dá mi lágara; ìwọ Ọlọ́run mú gbogbo ẹgbẹ́ mi takété.
Ti-itherũ, Wee Ngai nĩũũnogeetie; nĩũharaganĩtie nyũmba yakwa yothe.
8 Ìwọ fi ìhunjọ kùn mí lára, èyí tí o jẹ́rìí tì mí; àti rírù tí ó hàn lára mi, ó jẹ́rìí tì mí ní ojú.
Wee nĩũnjoheete, naguo ũndũ ũcio ũgatuĩka ũira; ũhĩnju ũyũ ndĩ naguo nĩwambararĩte ũkaanyumbũra ũrĩa ndariĩ.
9 Ọlọ́run fi i ìbínú rẹ̀ fà mí ya, ó sì gbóguntì mí; ó pa eyín rẹ̀ keke sí mi, ọ̀tá mi sì gbójú rẹ̀ sí mi.
Ngai nĩandooretie na akandembũranga nĩ ũrĩa arakarĩte, akaahagaranĩria magego; ũcio thũ yakwa nĩangũũrĩire maitho.
10 Wọ́n ti fi ẹnu wọn yẹ̀yẹ́ mi; Wọ́n gbá mi ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ ni ìgbá ẹ̀gàn; wọ́n kó ara wọn pọ̀ sí mi.
Andũ nĩmathamĩtie tũnua twao maathekerere; mangũthaga rũthĩa makĩĩnyũrũragia, na makanyiitana hamwe manjũkĩrĩre.
11 Ọlọ́run ti fi mí lé ọwọ́ ẹni búburú, ó sì mú mi ṣubú sí ọwọ́ ènìyàn ìkà.
Mũrungu nĩandekereirie kũrĩ andũ arĩa ooru, na akanjikia mĩtego-inĩ ya arĩa aaganu.
12 Mo ti jókòó jẹ́ẹ́, ṣùgbọ́n ó fà mí já; ó sì dì mí ni ọrùn mú, ó sì gbọ̀n mí túútúú, ó sì gbé mi kalẹ̀ láti ṣe àmì ìtafàsí rẹ̀;
Niĩ ndaikarĩte wega, nowe agĩĩthethera; aanyiitire mũmero, akĩĩhehenja. We anduĩte cabaa wake wa kũrathagwo;
13 àwọn tafàtafà rẹ̀ dúró yí mi káàkiri. Ó là mí láyà pẹ̀rẹ̀, kò si dá sí, ó sì tú òróòro ara mi dà sílẹ̀.
aikia a mĩguĩ ake nĩmandigiicĩirie. Aratheeca higo ciakwa atarĩ na tha, na agaita maaĩ makwa ma nyongo thĩ.
14 Ìbàjẹ́ lórí ìbàjẹ́ ní ó fi bà mí jẹ́; ó súré kọlù mi bí jagunjagun.
Aatharĩkagĩra maita maingĩ maingĩ; anguthũkagĩra ta njamba ya ita.
15 “Mo rán aṣọ ọ̀fọ̀ bò ara mi, mo sì rẹ̀ ìwo mi sílẹ̀ nínú erùpẹ̀.
“Ndumĩire gĩkonde gĩakwa kĩa mwĩrĩ nguo ya ikũnia, na ngahitha thiithi wakwa rũkũngũ-inĩ.
16 Ojú mi ti pọ́n fún ẹkún, òjìji ikú sì ṣẹ́ sí ìpéǹpéjú mi.
Ũthiũ wakwa nĩũtunĩhĩte nĩkũrĩra, nduma nene ĩgakĩhumbĩra maitho makwa;
17 Kì í ṣe nítorí àìṣòótọ́ kan ní ọwọ́ mi; àdúrà mi sì mọ́ pẹ̀lú.
no rĩrĩ, moko makwa matirĩ ũndũ wa ũhinya mekĩte namo mahooya makwa nĩ matheru.
18 “Háà! Ilẹ̀ ayé, ìwọ má ṣe bò ẹ̀jẹ̀ mi, kí ẹkún mi má ṣe wà ní ipò kan.
“Wee thĩ-rĩ, ndũkahumbĩre thakame yakwa; kĩrĩro gĩakwa kĩroaga gũkaahuurũkio!
19 Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi i, ẹlẹ́rìí mi ń bẹ ní ọ̀run, ẹ̀rí mi sì ń bẹ lókè ọ̀run.
O na rĩu-rĩ, mũira wakwa arĩ igũrũ; ũcio mũnjiirĩrĩri arĩ o igũrũ.
20 Àwọn ọ̀rẹ́ mi ń fi mí ṣẹ̀sín, ṣùgbọ́n ojú mi ń da omijé sọ́dọ̀ Ọlọ́run,
Mũũthaithanĩrĩri nĩ mũrata wakwa rĩrĩa maitho makwa maraita maithori harĩ Ngai;
21 ìbá ṣe pé ẹnìkan le è máa ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì lọ́dọ̀ Ọlọ́run, bí ènìyàn kan ti í ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì rẹ̀.
nĩathaithanagĩrĩra mũndũ kũrĩ Ngai, o ta ũrĩa mũndũ athaithanagĩrĩra mũratawe.
22 “Nítorí nígbà tí iye ọdún díẹ̀ rékọjá tán, nígbà náà ni èmi ó lọ sí ibi tí èmi kì yóò padà bọ̀.”
“No mĩaka mĩnini ĩgũthira, thiĩ rũgendo rũrĩa mũndũ athiiaga na ndacooke.

< Job 16 >