< Job 12 >

1 Jobu sì dáhùn, ó sì wí pé,
Ningĩ Ayubu agĩcookia atĩrĩ:
2 “Kò sí àní àní níbẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ni àwọn ènìyàn náà, ọgbọ́n yóò sì kú pẹ̀lú yín!
“Hatirĩ nganja inyuĩ nĩ inyuĩ andũ, naguo ũũgĩ ũgaathiranĩra na inyuĩ rĩrĩa mũgaakua!
3 Ṣùgbọ́n èmi ní ìyè nínú gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin; èmi kò kéré sí i yín. Àní, ta ni kò mọ gbogbo nǹkan wọ̀nyí?
No rĩrĩ, ndĩ na ũmenyo o ta inyuĩ; mũtirĩ oogĩ kũngĩra. Nũũ ũtooĩ maũndũ macio mothe?
4 “Èmi dàbí ẹni tí a ń fi ṣe ẹlẹ́yà lọ́dọ̀ aládùúgbò rẹ̀, tí ó ké pe Ọlọ́run, tí ó sì dá a lóhùn, à ń fi olóòtítọ́ ẹni ìdúró ṣinṣin rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà!
“Nduĩkĩte mũndũ wa gũthekererwo nĩ arata akwa, o na gũtuĩka nĩndakaĩire Ngai nake akĩnjigua: niĩ nduĩkĩte mũndũ wa gũthekererwo, o na gũtuĩka ndĩ mũthingu na ndirĩ ũcuuke!
5 Ó rọrùn fún ènìyàn láti fi ìbànújẹ́ ẹlòmíràn ṣe ẹlẹ́yà gẹ́gẹ́ bí ìpín àwọn ẹni tí ẹsẹ̀ wọn ṣetán láti yọ̀.
Andũ arĩa maikaraga megangarĩte manyũrũragia mũtino, makona ta ũndũ ũcio ũkoraga o andũ arĩa magũrũ mao matenderũkaga.
6 Àgọ́ àwọn ìgárá ọlọ́ṣà wá láìní ìbẹ̀rù; àwọn tí ó sì ń mú Ọlọ́run bínú wà láìléwu, àwọn ẹni tí ó sì gbá òrìṣà mú ní ọwọ́ wọn.
Hema cia atunyani nĩcio ciikaraga igaacĩire, na andũ arĩa marakaragia Mũrungu nĩo maikaraga na thayũ, o acio makuuaga ngai yao na moko.
7 “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí bí àwọn ẹranko léèrè, wọn o kọ́ ọ ní ẹ̀kọ́, àti ẹyẹ ojú ọ̀run, wọn ó sì sọ fún ọ.
“No ta kĩũrie nyamũ, na nĩigũkũruta ũhoro, kana ũrie nyoni cia rĩera-inĩ, na nĩigũkwĩra;
8 Tàbí ba ilẹ̀ ayé sọ̀rọ̀, yóò sì kọ́ ọ, àwọn ẹja inú òkun yóò sì sọ fún ọ.
kana warĩrie thĩ, na nĩĩgũkũruta ũhoro, kana ũkĩarĩrie thamaki cia iria-inĩ, nacio nĩigũkũhe ũhoro.
9 Ta ni kò mọ̀ nínú gbogbo nǹkan wọ̀nyí pé, ọwọ́ Olúwa ni ó ṣe nǹkan yìí?
Nĩ irĩkũ cia icio ciothe itooĩ atĩ nĩ guoko kwa Jehova gwĩkĩte ũndũ ũyũ?
10 Ní ọwọ́ ẹni tí ẹ̀mí ohun alààyè gbogbo gbé wà, àti ẹ̀mí gbogbo aráyé.
Mĩoyo ya ciũmbe ciothe ĩrĩ guoko-inĩ gwake, o na mĩhũmũ ya andũ othe.
11 Etí kì í dán ọ̀rọ̀ wò bí tàbí adùn ẹnu kì í sì í tọ́ oúnjẹ rẹ̀ wò bí?
Githĩ gũtũ gũtithuuranagia ciugo o ta ũrĩa rũrĩmĩ rũcamaga irio?
12 Àwọn arúgbó ni ọgbọ́n wà fún, àti nínú gígùn ọjọ́ ni òye.
Githĩ ũũgĩ ndũkoragwo na andũ arĩa akũrũ? Githĩ gũtũũra mũno gũtirehaga ũmenyo?
13 “Ti Ọlọ́run ni ọgbọ́n àti agbára; òun ló ni ìmọ̀ àti òye.
“Ũũgĩ na hinya nĩ cia Ngai; mataaro na ũmenyo nĩ ciake.
14 Kíyèsi i, ó bì wó, a kò sì lè gbe ró mọ́; Ó sé ènìyàn mọ́, kò sì sí ìtúsílẹ̀ kan.
Kĩrĩa amomoraga gĩtingĩakwo rĩngĩ; mũndũ ũrĩa aahingĩra njeera gũtirĩ mũndũ ũngĩmuohora.
15 Kíyèsi i, ó dá àwọn omi dúró, wọ́n sì gbẹ; Ó sì rán wọn jáde, wọ́n sì ṣẹ̀ bo ilẹ̀ ayé yípo.
Ahingagĩrĩria maaĩ, gũkaaga mbura; ningĩ aamarekereria makaananga bũrũri.
16 Tìrẹ ni agbára àti ìṣẹ́gun; ẹni tí ń ṣìnà àti ẹni tí ń mú ni ṣìnà, tirẹ̀ ni wọ́n ń ṣe.
Hinya na ũtooria nĩ ciake; mũheenio na mũheenania eerĩ no ake.
17 Ó mú àwọn ìgbìmọ̀ lọ ní ìhòhò a sì sọ àwọn onídàájọ́ di òmùgọ̀.
Aheani kĩrĩra amatongoragia matarĩ nguo, na agatua aciirithania irimũ.
18 Ó tú ìdè ọba ó sì fi àmùrè gbà wọ́n ní ọ̀já.
Nĩohoraga mĩnyororo ĩrĩa athamaki moohaga andũ nayo, akamooha mũcibi njohero.
19 Ó mú àwọn àlùfáà lọ ní ìhòhò ó sì tẹ orí àwọn alágbára ba.
Athĩnjĩri-Ngai amatongoragia marutĩtwo nguo, na akangʼaũrania andũ arĩa mehaandire tene.
20 Ó mú ọ̀rọ̀ ẹnu ẹni ìgbẹ́kẹ̀lé kúrò ó sì ra àwọn àgbàgbà ní iyè.
Nĩakiragia mĩromo ya aheani kĩrĩra arĩa meehoketwo, nao athuuri akamatunya ũhoro wa gũkũũrana maũndũ.
21 Ó bu ẹ̀gàn lu àwọn ọmọ ọlọ́lá ó sì tú àmùrè àwọn alágbára.
We nĩagagĩra arĩa atĩĩku bata, nao arĩa marĩ na hinya nĩamatunyaga indo ciao cia mbaara.
22 Ó hú ìdí ohun ìjìnlẹ̀ jáde láti inú òkùnkùn wá ó sì mú òjìji ikú wá sínú ìmọ́lẹ̀.
Nĩaguũragia maũndũ marĩa mariku ma nduma, na nduma nene ya gĩkuũ akamiumĩria ũtheri-inĩ.
23 Òun a mú orílẹ̀-èdè bí sí i, a sì run wọ́n; òun a sọ orílẹ̀-èdè di ńlá, a sì tún ṣẹ̀ wọn kù.
Anenehagia ndũrĩrĩ, agacooka agaciananga; aingĩhagia ndũrĩrĩ, agacooka agacihurunja.
24 Òun a gba òye àwọn olórí àwọn ènìyàn aráyé, a sì máa mú wọn rin kiri nínú ijù níbi tí ọ̀nà kò sí.
Nĩagaagagia meciiria ma atongoria a gũkũ thĩ; akamaingata, morũũrage werũ-inĩ mũtheri ũtarĩ njĩra.
25 Wọn a máa fi ọwọ́ ta ilẹ̀ nínú òkùnkùn níbi tí kò sí ìmọ́lẹ̀; òun a sì máa mú ìrìn ìsìn wọn bí ọ̀mùtí.
Mahambaataga nduma-inĩ kũrĩa gũtarĩ ũtheri; ningĩ atũmaga matũgũũge ta mũndũ mũrĩĩu.

< Job 12 >