< Job 11 >

1 Ìgbà náà ni Sofari, ará Naama, dáhùn, ó sì wí pé,
Nake Zofaru ũrĩa Mũnaamathi agĩcookia, akĩũria atĩrĩ:
2 “A ha lè ṣe kí a máa dáhùn sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀rọ̀? A ha lè fi gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí da ènìyàn láre?
“Ciugo icio ciothe-rĩ, nĩcikwaga gũcookio? Mwaria ũyũ-rĩ, nĩegũgĩtuuo mwagĩrĩru?
3 Ṣé àmọ̀tán rẹ le mú ènìyàn pa ẹnu wọn mọ́ bí? Ṣé ẹnikẹ́ni kò ní bá ọ wí bí ìwọ bá yọ ṣùtì sí ni?
Mwĩraho ũcio waku-rĩ, nĩguo ũgũkiria andũ naguo? No kwage mũndũ ũngĩgũkaania rĩrĩa ũranyũrũrania?
4 Ìwọ sá à ti wí fún Ọlọ́run pé, ‘Ìṣe mi jẹ́ aláìléérí, èmi sì mọ́ ní ojú rẹ.’
Wee ũreera Ngai atĩrĩ, ‘Wĩtĩkio wakwa ndũrĩ ũcuuke, o na niĩ ndĩ mũtheru maitho-inĩ maku.’
5 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ìbá jẹ́ sọ̀rọ̀, kí ó sì ya ẹnu rẹ̀ sí ọ
Naarĩ korwo Ngai no aarie, atumũre mĩromo yake agũũkĩrĩre,
6 kí ó sì fi àṣírí ọgbọ́n hàn ọ́ pé, ó pọ̀ ju òye ènìyàn lọ, nítorí náà, mọ̀ pé Ọlọ́run ti gbàgbé àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ kan.
na akũguũrĩrie hitho cia ũũgĩ, nĩ ũndũ ũũgĩ ũrĩa wa ma nĩ wa mĩena ĩĩrĩ. Menya ũndũ ũyũ; atĩ Ngai ndakũherithĩtie kũringana na ũrĩa mehia maku maigana.
7 “Ìwọ ha le ṣe àwárí ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run bí? Ìwọ ha le ṣe àwárí ibi tí Olódùmarè dé bi?
“Wee no ũhote kũmenya maũndũ marĩa mahithe ma Ngai? Kana no ũhote gũtuĩria kũna maũndũ ma Mwene-Hinya-Wothe?
8 Ó ga ju àwọn ọ̀run lọ; kí ni ìwọ le è ṣe? Ó jìn ju jíjìn isà òkú lọ; kí ni ìwọ le mọ̀? (Sheol h7585)
Maũndũ make nĩmatũũgĩru gũkĩra igũrũ, wee nĩ atĩa ũngĩka? Nĩ mariku gũkĩra ũriku wa mbĩrĩra, wee nĩ atĩa ũngĩmenya? (Sheol h7585)
9 Ìwọ̀n rẹ̀ gùn ju ayé lọ, ó sì ní ibú ju òkun lọ.
Gĩthimo kĩamo nĩ kĩraihu gũkĩra thĩ na nĩ kĩaramu gũkĩra iria rĩrĩa inene.
10 “Bí òun bá rékọjá, tí ó sì sé ọnà tàbí tí ó sì mú ni wá sí ìdájọ́, ǹjẹ́, ta ni ó lè dí i lọ́wọ́?
“Angĩũka agũikie njeera-rĩ, acooke etane ciira-rĩ, nũũ ũngĩmũgiria?
11 Òun sá à mọ ẹlẹ́tàn ènìyàn; àti pé ṣé bí òun bá rí ohun búburú, ṣé òun kì i fi iyè sí i?
Ti-itherũ nĩoĩ andũ arĩa maheenanagia; na rĩrĩa oona ũndũ mũũru-rĩ, githĩ ndaũmenyaga?
12 Ṣùgbọ́n òmùgọ̀ ènìyàn ki yóò di ọlọ́gbọ́n bi ko ti rọrùn fún ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó láti bí ènìyàn.
No rĩrĩ, mũndũ ũtarĩ ũũgĩ ndangĩtuĩka mũũgĩ o na rĩ, o ta ũrĩa njaũ ya ndigiri ya gĩthaka ĩtarĩ hĩndĩ ĩngĩciarwo ĩrĩ mũndũ.
13 “Bí ìwọ bá fi ọkàn rẹ fún un, tí ìwọ sì na ọwọ́ rẹ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀,
“No rĩrĩ, ũngĩneana ngoro yaku kũrĩ Ngai, na ũtambũrũkie moko maku kũrĩ we,
14 bí ìwọ bá gbé ẹ̀ṣẹ̀ tí ń bẹ ní ọwọ́ rẹ jù sọnù tí ìwọ kò sì jẹ́ kí aburú gbé nínú àgọ́ rẹ,
ũngĩeheria mehia marĩa marĩ guoko-inĩ gwaku, na ũgirie ũũru ũikare thĩinĩ wa hema yaku-rĩ,
15 nígbà náà ni ìwọ ó gbé ojú rẹ sókè láìní àbàwọ́n, àní ìwọ yóò dúró ṣinṣin, ìwọ kì yóò sì bẹ̀rù.
hĩndĩ ĩyo no ũhote gũtiira ũthiũ waku na igũrũ ũtegũconoka; no ũrũgame wega ũtarĩ na guoya.
16 Nítorí pé ìwọ ó gbàgbé ìṣòro rẹ; ìwọ ó sì rántí rẹ̀ bí omi tí ó ti sàn kọjá lọ.
Ti-itherũ nĩũkariganĩrwo nĩ mathĩĩna maku, ũmaririkanage o ta maaĩ marĩkĩtie gũtherera.
17 Ọjọ́ ayé rẹ yóò sì mọ́lẹ̀ ju ọ̀sán gangan lọ, bí òkùnkùn tilẹ̀ bò ọ́ mọ́lẹ̀ nísinsin yìí, ìwọ ó dàbí òwúrọ̀.
Mũtũũrĩre waku nĩũgacangarara gũkĩra mũthenya barigici, nayo nduma ĩgaatuĩka o ta rũciinĩ.
18 Ìwọ ó sì wà láìléwu, nítorí pé ìrètí wà; àní ìwọ ó rin ilé rẹ wò, ìwọ ó sì sinmi ní àlàáfíà.
Ũgũtũũra ũrĩ na mwĩhoko tondũ ũrĩ na ũgitĩri, ũkehũgũraga harĩa ũrĩ, na ũkahurũka ũtarĩ na ũgwati.
19 Ìwọ ó sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú, kì yóò sì sí ẹni tí yóò dẹ́rùbà ọ́, àní ènìyàn yóò máa wá ojúrere rẹ.
Nĩũgakomaga, gũtarĩ na mũndũ ũngĩtũma wĩtigĩre, nao andũ aingĩ nĩmakeyendithagia harĩ we.
20 Ṣùgbọ́n ojú ìkà ènìyàn yóò mófo; gbogbo ọ̀nà àbáyọ ni yóò nù wọ́n, ìrètí wọn a sì dàbí ẹni tí ó jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀ lọ́wọ́.”
No rĩrĩ, maitho ma andũ arĩa aaganu nĩmakaaga kuona, na matikoona gwa kũũrĩra; naguo ũndũ ũrĩa meriragĩria ũgaatuĩka mũcaayo wa gĩkuũ.”

< Job 11 >