< Jeremiah 9 >
1 Háà! Orí ìbá jẹ́ orísun omi kí ojú mi sì jẹ́ orísun omijé! Èmi yóò sì sọkún tọ̀sán tòru nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.
Oe ka lû heh tuikhu lah awm haw pawiteh, ka mit roi heh mitphi tuiphuek lah awm haw pawiteh, ka tami ka canunaw thei lah ao dawkvah, khohmo khodai ka ka yawkaw han toe.
2 Háà, èmi ìbá ní ni aginjù ilé àgbàwọ̀ fún àwọn arìnrìn-àjò, kí n ba à lè fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀ kí n sì lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn: nítorí gbogbo wọn jẹ́ panṣágà àjọ aláìṣòótọ́ ènìyàn.
Oe ahnimouh koehoi cei vaiteh, ka taminaw ka ceitakhai thai nahanlah, imyinnaw hanlah roenae hmuen hah kingdinae koe tawn hanlah ka ngai. Bangkongtetpawiteh, abuemlahoi ka uicuk e, dumyen hoi kamkhueng e lah ao awh.
3 Wọ́n ti pèsè ahọ́n wọn sílẹ̀ bí ọfà láti fi pa irọ́; kì í ṣe nípa òtítọ́ ni wọ́n fi borí ní ilẹ̀ náà. Wọ́n ń lọ láti inú ẹ̀ṣẹ̀ kan sí òmíràn; wọn kò sì náání mi, ní Olúwa wí.
Laithoe dei awh nahanlah, a lainaw hah pala patetlah sut a pho awh. Lawk katang hoi ram thung vah roung awh hoeh. A yonnae buet touh koe hoi buet touh patuen a cei awh, kai heh banglah hai na ngai awh hoeh, telah BAWIPA ni a ti.
4 “Ṣọ́ra fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ; má ṣe gbẹ́kẹ̀lé àwọn arákùnrin rẹ. Nítorí pé oníkálùkù arákùnrin jẹ́ atannijẹ, oníkálùkù ọ̀rẹ́ sì jẹ́ abanijẹ́.
Na huinaw hah kâhruetcuet awh, na hmaunawnghanaw hai kâuep awh hanh. Bangkongtetpawiteh, hmaunawngha abuemlah kadumyennaw lah ao awh teh, a hui pueng hai tamthoe ka dei seng doeh.
5 Ọ̀rẹ́ ń dalẹ̀ ọ̀rẹ́. Kò sì ṣí ẹni tó sọ òtítọ́, wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn láti máa purọ́. Wọ́n sọ ara wọn di onírẹ̀wẹ̀sì pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀
Hui hoi hui a kâdoun awh, apinihai lawkkatang dei awh hoeh. A lai heh laithoe deinae lai lah a pâtu awh teh, yonnae hoi amahoima tha a tawn sak awh.
6 Ó ń gbé ní àárín ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti mọ̀ mí nínú ẹ̀tàn wọn,” ni Olúwa wí.
Laithoe dawk na kangdue awh teh, a laithoenae ni kai panue hanlah ngai awh hoeh, telah BAWIPA ni a ti.
7 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Wò ó, èmi dán wọn wo; nítorí pé kí ni èmi tún le è ṣe? Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi?
Hatdawkvah, ransahu BAWIPA ni hettelah a dei, khenhaw! ahnimouh teh atui lah kamyawt sak vaiteh, ka tanouk han, ka tami lah kaawm e ka canu heh bangtelamaw ka ti han.
8 Ahọ́n wọn dàbí ọfà olóró; ó ń sọ ẹ̀tàn. Oníkálùkù sì ń fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ àlàáfíà sí aládùúgbò rẹ̀, ní inú ọkàn rẹ̀, ó dẹ tàkúté sílẹ̀.
Ahnimae a lai teh duenae pala lah ao teh, laithoe lawk a dei awh. A pahni hoi imrinaw koe kâponae lawk a dei awh ei, a lung thung hoi teh, sut a pawp awh.
9 Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n nítorí èyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò ha gbẹ̀san ara mi lórí irú orílẹ̀-èdè yìí bí?”
Hatdawkvah, rek hoe laipalah ka o han na maw, telah BAWIPA ni ati. Hettelah kaawm e lathueng vah kama hoi kama moipathung laipalah ka o han maw.
10 Èmi yóò sì sọkún, pohùnréré ẹkún fún àwọn òkè àti ẹkún ìrora lórí pápá oko aginjù wọ̀n-ọn-nì. Nítorí wọ́n di ahoro, wọn kò sì kọjá ní ibẹ̀. A kò sì gbọ́ igbe ẹran ọ̀sìn. Àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ti sálọ, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ẹranko sì ti lọ.
Monnaw hanlah lungpataw hoi ka ka vaiteh, kahrawng e phovainaw ka khui han. Hotnaw teh sut a ke awh teh, apinihai pâtam hoe toe. Saringnaw lawk hai thai hoe toe. Lathueng tavanaw hai koung a poung awh teh, kahrawng moithangnaw hai awm hoeh toe.
11 “Èmi yóò sì sọ Jerusalẹmu di òkìtì àlàpà àti ihò àwọn ìkookò. Èmi ó sì sọ ìlú Juda di ahoro tí ẹnikẹ́ni kò sì ní le è gbé.”
Jerusalem teh songnawngbom lah ka hruek vaiteh, kahrawnguinaw onae hmuen lah ka ta han, Judah khonaw hai kingdi sak vaiteh, api buet touh hai awm mahoeh.
12 Ta ni ẹni náà tí ó ní ọgbọ́n láti mòye nǹkan wọ̀nyí? Ta ni Olúwa ti sọ èyí fún, tí ó sì lè ṣàlàyé rẹ̀? Èéṣe tí ilẹ̀ náà fi ṣègbé bí aginjù, tí ẹnìkankan kò sì le là á kọjá?
Hete hno panue thai nahan a lungkaang e apimaw. BAWIPA ni apimaw a cangkhai teh hete hno heh kacaicalah ka dei thai. Apinihai a pâtam hoeh e thingyei patetlah a ram hah he a kak.
13 Olúwa sì wí pé, nítorí pé wọ́n ti kọ òfin mi sílẹ̀, èyí tí mo gbé kalẹ̀ níwájú wọn, wọn ṣe àìgbọ́ràn sí wọn, wọn kò sì rìn nínú òfin mi.
BAWIPA ni a dei e teh, ahnimouh hmalah ka ta pouh e, kaie kâlawk hah a pahnawt awh teh, ka lawk ngai awh hoeh, cangkhainae lawk hai tarawi awh hoeh.
14 Dípò èyí, wọ́n ti tẹ̀lé agídí ọkàn wọn, wọ́n ti tẹ̀lé Baali gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe kọ́ wọn.
Amamae lung a patanae lamthung hah a tarawi awh, a napanaw ni a cangkhai awh e patetlah Baal hnuk a kâbang awh.
15 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí, “Wò ó, Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ oúnjẹ kíkorò àti láti mu omi májèlé.
Hatdawkvah, ransahu BAWIPA Isarel Cathut ni hettelah a dei, khenhaw! hete taminaw heh rawca kakhat ka ca sak vaiteh, kakhat e tui hah ka nei sak han.
16 Èmi yóò sì tú wọn ká láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, nínú èyí tí àwọn tàbí àwọn baba wọn kò mọ̀. Èmi yóò sì lépa wọn pẹ̀lú idà títí èmi yóò fi pa wọ́n run.”
Ahnimouh hoi a napanaw ni a panue boihoeh e miphunnaw koe kâkayeisak vaiteh, ahnimanaw be raphoe hoehroukrak tahloi ka pâlei sak han.
17 Èyí sì ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí: “Sá à wò ó nísinsin yìí! Ké sí obìnrin ti ń ṣọ̀fọ̀ nì kí ó wá; sì ránṣẹ́ pe àwọn tí ó mòye nínú wọn.
Ransahu BAWIPA ni hettelah a dei, atu kahawicalah pouk awh haw, ka kap thai e napuinaw hah tho hanlah kaw awh leih, ahnimouh imthung dawk hai kalung kathoumpoungnaw hah lawk thui awh.
18 Jẹ́ kí wọn wá kíákíá, kí wọn wá pohùnréré ẹkún lé wa lórí títí ojú wa yóò fi sàn fún omijé tí omi yóò sì máa sàn àwọn ìpéǹpéjú wa.
Ahnimanaw hah karang tho sak nateh, mamae mitphi a lawng teh, mamae mitsum dawk hoi tui a phuek hoehroukrak, maimouh na kapkhai lawiseh.
19 A gbọ́ igbe ìpohùnréré ẹkún ní Sioni: ‘Àwa ti ṣègbé tó! A gbọdọ̀ fi ilẹ̀ wa sílẹ̀, nítorí pé àwọn ilé wa ti parun.’”
Kanae lawk heh Zion hoi thai thai lah ao. Banghloimaw rawk awh tangngak toe. Yeiraipo awh katang toe. Na imlawnaw a ro katang toung dawkvah, ram teh ka ceitakhai awh toe.
20 Nísinsin yìí, ẹ̀yin obìnrin ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa; ṣí etí yín sí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ. Kọ́ àwọn ọmọbìnrin yín ní ìpohùnréré ẹkún, kí ẹ sì kọ́ ara yín ní arò.
Atuvah, Oe napuinaw, BAWIPA e lawk heh thaihaw, a pahni dawk e lawk koe lah hnâpakeng haw, na canunaw bangtelamaw a ka awh han tie hah cangkhai awh. Kalungla buet touh hoi buet touh kâcangkhai awh.
21 Ikú ti gba ojú fèrèsé wa wọlé ó sì ti wọ odi alágbára wa ó ti ké àwọn ọmọ kúrò ní àdúgbò àti àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò ní gbọ̀ngàn ìta gbangba.
Duenae teh hlalangaw koehoi a kâen teh, im thung vah a kâen, lamthung dawk e camonaw a takhoe teh lamlawng e nawsainaw a pâlei toe.
22 Sọ pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubú bí ààtàn ní oko gbangba àti bí ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórè láìsí ẹnìkankan láti kó wọn jọ.’”
BAWIPA ni hettelah a dei, tami kadoutnaw e ro teh laikawk dawk e vaipuen patetlah thoseh, cang ka a naw ni cabong a pâhma awh e patetlah thoseh, apinihai ahnimouh teh bout kuem awh mahoeh toe, telah dei pouh.
23 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Má ṣe jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n yangàn nítorí agbára ọgbọ́n rẹ̀, tàbí alágbára nítorí agbára rẹ̀, tàbí ọlọ́rọ̀ nítorí ọrọ̀ rẹ̀.
BAWIPA ni hettelah a dei, tami lungkaang ni lungangnae dawk kâoup hanh naseh, thakasai ni thasainae dawk kâoup hanh naseh, bawi ni hai a bawinae dawk kâoup hanh naseh.
24 Ẹ jẹ́ kí ẹni tí ń ṣògo nípa èyí nì wí pé: òun ní òye, òun sì mọ̀ mí wí pé, Èmi ni Olúwa tí ń ṣe òtítọ́, ìdájọ́ àti òdodo ní ayé, nínú èyí ni mo ní inú dídùn sí,” Olúwa wí.
Hatei, apipatet hai kâoup ngai pawiteh, het dawk kâoup naseh, kai na ka nout hoi na ka panuek e hah teh BAWIPA lungpatawnae, ka thuem hoi lannae talai van kasakkung doeh, hete hninaw heh ka lunghawinae doeh, telah BAWIPA ni a ti.
25 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí a kọ ilà fún nínú ara nìkan.
Takthai dawk dueng vah vuensom ka a e taminaw pueng rek nahane atueng teh a pha toe, telah BAWIPA ni a ti.
26 Ejibiti, Juda, Edomu, Ammoni, Moabu àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní ọ̀nà jíjìn réré ní aginjù. Nítorí pé gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jẹ́ aláìkọlà gbogbo àwọn ará ilé Israẹli sì jẹ́ aláìkọlà ọkàn.”
Izip, Judah, Edom, Ammon, Moab, hoi thingyei ram ahlanae koe kaawm e tami pueng hai, hote miphunnaw pueng teh vuensom ka a hoeh e taminaw lah ao awh. Isarel imthung buemlah hoi lungthin lahoi vuensom ka a hoeh e seng doeh, telah BAWIPA ni a dei.