< Jeremiah 9 >

1 Háà! Orí ìbá jẹ́ orísun omi kí ojú mi sì jẹ́ orísun omijé! Èmi yóò sì sọkún tọ̀sán tòru nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.
Aw kai kaminawk ih canu humhaih pongah, aqum athun ka qah, ka lu loe tui suih moe, ka mik loe tuibap ah oh boeh.
2 Háà, èmi ìbá ní ni aginjù ilé àgbàwọ̀ fún àwọn arìnrìn-àjò, kí n ba à lè fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀ kí n sì lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn: nítorí gbogbo wọn jẹ́ panṣágà àjọ aláìṣòótọ́ ènìyàn.
Aw nihcae loe zu sava nuiah zaehaih sah kami, oep kaom ai kami ah oh o pongah, kaimah ih kaminawk to ka caeh taak moe, praezaek ah ohhaih ahmuen pakrong han ka koeh boeh.
3 Wọ́n ti pèsè ahọ́n wọn sílẹ̀ bí ọfà láti fi pa irọ́; kì í ṣe nípa òtítọ́ ni wọ́n fi borí ní ilẹ̀ náà. Wọ́n ń lọ láti inú ẹ̀ṣẹ̀ kan sí òmíràn; wọn kò sì náání mi, ní Olúwa wí.
Nihcae loe amsawnlok thuih hanah palai to kalii baktiah anueng o coek boeh; toe nihcae loe long nuiah loktang lok hoi qoeng o ai; zaehaih maeto pacoeng maeto bangah caeh o moe, Kai hae panoek o ai, tiah Angraeng mah thuih.
4 “Ṣọ́ra fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ; má ṣe gbẹ́kẹ̀lé àwọn arákùnrin rẹ. Nítorí pé oníkálùkù arákùnrin jẹ́ atannijẹ, oníkálùkù ọ̀rẹ́ sì jẹ́ abanijẹ́.
Nam puinawk nuiah acoe oh; nam nawkamyanawk to oep o hmah; nawkamyanawk loe aling thaih kami ah oh o boih, ampuinawk doeh kasae thui thaih kami ah ni oh o.
5 Ọ̀rẹ́ ń dalẹ̀ ọ̀rẹ́. Kò sì ṣí ẹni tó sọ òtítọ́, wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn láti máa purọ́. Wọ́n sọ ara wọn di onírẹ̀wẹ̀sì pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀
Nihcae loe angmacae ampui to aling o, loktang to thui o ai; amsawnlok thuih hanah palai to patuk o; zaehaih sak o loiah angpho o boeh.
6 Ó ń gbé ní àárín ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti mọ̀ mí nínú ẹ̀tàn wọn,” ni Olúwa wí.
Nang loe alinghaih um ah na oh, alinghaih pongah kai panoek han koeh o ai, tiah Angraeng mah thuih.
7 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Wò ó, èmi dán wọn wo; nítorí pé kí ni èmi tún le è ṣe? Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi?
To pongah misatuh Angraeng mah hae tiah thuih; Khenah, nihcae to atui ah kam kawsak moe, Ka tanoek han; Kai kaminawk canu hanah kawbangmaw Ka sak pae han?
8 Ahọ́n wọn dàbí ọfà olóró; ó ń sọ ẹ̀tàn. Oníkálùkù sì ń fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ àlàáfíà sí aládùúgbò rẹ̀, ní inú ọkàn rẹ̀, ó dẹ tàkúté sílẹ̀.
Nihcae ih palai loe duekhaih palaa ah oh moe, alinghaih hoiah lok a thuih o; a imtaeng kami khaeah pakha hoiah angdaehhaih lok to thuih o, toe palung thung hoiah loe Anih han dongh patung pae o.
9 Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n nítorí èyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò ha gbẹ̀san ara mi lórí irú orílẹ̀-èdè yìí bí?”
Hae hmuennawk pongah thuitaek ai ah ka oh han maw? tiah Angraeng mah thuih; to baktih acaeng nuiah danpaek ai ah poek angphohaih hoiah maw Ka oh han?
10 Èmi yóò sì sọkún, pohùnréré ẹkún fún àwọn òkè àti ẹkún ìrora lórí pápá oko aginjù wọ̀n-ọn-nì. Nítorí wọ́n di ahoro, wọn kò sì kọjá ní ibẹ̀. A kò sì gbọ́ igbe ẹran ọ̀sìn. Àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ti sálọ, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ẹranko sì ti lọ.
Maenawk to ka qah haih moe, praezaek ih ohhaih ahmuennawk hanah doeh ka oi haih han; mi mah doeh caeh thaih han ai ah, hmai mah kangh boih boeh; kaminawk mah im ah pacah ih moi lok doeh thaih o ai boeh; van ih tavaanawk doeh angpoeng o boih boeh, moi kasannawk doeh cawnh o boih boeh moe, om o ai boeh.
11 “Èmi yóò sì sọ Jerusalẹmu di òkìtì àlàpà àti ihò àwọn ìkookò. Èmi ó sì sọ ìlú Juda di ahoro tí ẹnikẹ́ni kò sì ní le è gbé.”
Jerusalem loe anghnoeng tapophaih ahmuen, tasuinawk ohhaih ahmuen ah ka sak han; Judah vangpuinawk doeh, kami om ai ahmuen ah ka ohsak han.
12 Ta ni ẹni náà tí ó ní ọgbọ́n láti mòye nǹkan wọ̀nyí? Ta ni Olúwa ti sọ èyí fún, tí ó sì lè ṣàlàyé rẹ̀? Èéṣe tí ilẹ̀ náà fi ṣègbé bí aginjù, tí ẹnìkankan kò sì le là á kọjá?
Hae hmuen panoek thaih, palungha kami loe mi aa? Hae hmuen thuih thai hanah Angraeng mah lokthuih pae ih kami loe mi aa? Mi doeh caeh thaih han ai ah, prae loe amro boeh moe, praezaek baktiah hmai mah kang boih boeh.
13 Olúwa sì wí pé, nítorí pé wọ́n ti kọ òfin mi sílẹ̀, èyí tí mo gbé kalẹ̀ níwájú wọn, wọn ṣe àìgbọ́ràn sí wọn, wọn kò sì rìn nínú òfin mi.
Angraeng mah hae tiah thuih; Nihcae loe angmacae hmaa ah ka suek pae ih, ka patukhaih lok to pahnawt o, ka lok tahngai o ai moe, pazui doeh pazui o ai;
14 Dípò èyí, wọ́n ti tẹ̀lé agídí ọkàn wọn, wọ́n ti tẹ̀lé Baali gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe kọ́ wọn.
angmacae poekhaih loklam to pazui o moe, ampanawk mah patuk ih, Baalnawk hnukah bang o lat.
15 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí, “Wò ó, Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ oúnjẹ kíkorò àti láti mu omi májèlé.
To pongah misatuh Angraeng, Israel Sithaw mah hae tiah thuih; Khenah, hae kaminawk, nihcae loe kakhaa buh to ka pacah moe, kasoetui to ka naeksak han.
16 Èmi yóò sì tú wọn ká láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, nínú èyí tí àwọn tàbí àwọn baba wọn kò mọ̀. Èmi yóò sì lépa wọn pẹ̀lú idà títí èmi yóò fi pa wọ́n run.”
Angmacae hoi ampanawk mah panoek o vai ai ih, Sithaw panoek ai kaminawk salakah kam hetsak han; nihcae ka hum boih ai karoek to, sumsen ka patoeh han.
17 Èyí sì ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí: “Sá à wò ó nísinsin yìí! Ké sí obìnrin ti ń ṣọ̀fọ̀ nì kí ó wá; sì ránṣẹ́ pe àwọn tí ó mòye nínú wọn.
Misatuh Angraeng mah hae tiah thuih; Kho poek oh, qah thaih nongpatanawk angzoh hanah kawk oh; oi thaih nongpatanawk angzoh thai hanah patoeh oh.
18 Jẹ́ kí wọn wá kíákíá, kí wọn wá pohùnréré ẹkún lé wa lórí títí ojú wa yóò fi sàn fún omijé tí omi yóò sì máa sàn àwọn ìpéǹpéjú wa.
Kaminawk mah, aicae mikkhraetui long moe, mikkhraetui hoi mik koi ai karoek to ang qah o haih hanah, nihcae to karangah angzo o sak ah.
19 A gbọ́ igbe ìpohùnréré ẹkún ní Sioni: ‘Àwa ti ṣègbé tó! A gbọdọ̀ fi ilẹ̀ wa sílẹ̀, nítorí pé àwọn ilé wa ti parun.’”
Qahhaih lok loe Zion hoiah angthaih; aicae loe amro o tangtang boeh! Azathaih a tongh o boeh, minawk mah aicae ohhaih ahmuennawk to phraek boih boeh pongah, prae loe pahnawt sut han oh boeh.
20 Nísinsin yìí, ẹ̀yin obìnrin ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa; ṣí etí yín sí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ. Kọ́ àwọn ọmọbìnrin yín ní ìpohùnréré ẹkún, kí ẹ sì kọ́ ara yín ní arò.
Aw nongpatanawk, Angraeng ih lok to tahngai oh; anih pakha hoi tacawt lok pongah naa to patueng oh; na canunawk hanah qahhaih lok, a imtaeng kaminawk boih hanah oihaih lok to patuk oh.
21 Ikú ti gba ojú fèrèsé wa wọlé ó sì ti wọ odi alágbára wa ó ti ké àwọn ọmọ kúrò ní àdúgbò àti àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò ní gbọ̀ngàn ìta gbangba.
Duekhaih loe aicae ih thokbuem ah dawh tahang moe, tasa bang ih nawktanawk to hum moe, longhma ih thendoengnawk to hum hanah, aicae ohhaih ahmuen thungah akunh.
22 Sọ pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubú bí ààtàn ní oko gbangba àti bí ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórè láìsí ẹnìkankan láti kó wọn jọ.’”
Angraeng mah hae tiah thuih, tiah thui paeh; Kadueh qoknawk loe aek batiah azawn ah angsong o tih, cang aat kami mah tahmaih ih cangqui baktiah, mi mah doeh nihcae ih qok to pakuem mak ai.
23 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Má ṣe jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n yangàn nítorí agbára ọgbọ́n rẹ̀, tàbí alágbára nítorí agbára rẹ̀, tàbí ọlọ́rọ̀ nítorí ọrọ̀ rẹ̀.
Angraeng mah hae tiah thuih; Palungha kami loe palunghahaih pongah amoek o hmah nasoe, thacak kami doeh a thacakhaih pongah amoek hmah nasoe loe, angraeng kami doeh angraenghaih pongah amoek hmah nasoe:
24 Ẹ jẹ́ kí ẹni tí ń ṣògo nípa èyí nì wí pé: òun ní òye, òun sì mọ̀ mí wí pé, Èmi ni Olúwa tí ń ṣe òtítọ́, ìdájọ́ àti òdodo ní ayé, nínú èyí ni mo ní inú dídùn sí,” Olúwa wí.
amoek kami mah, Kai loe long nuiah tahmenhaih hoi amlunghaih, katoengah lokcaekhaih, toenghaih sahkung Angraeng ah oh, tiah kai panoekhaih bangah amoek o haih nasoe, tiah Angraeng mah thuih.
25 “Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí a kọ ilà fún nínú ara nìkan.
Khenah, takpum ah khue tangyat hin aat kaminawk thuitaekhaih aninawk to angzoh li boeh;
26 Ejibiti, Juda, Edomu, Ammoni, Moabu àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní ọ̀nà jíjìn réré ní aginjù. Nítorí pé gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jẹ́ aláìkọlà gbogbo àwọn ará ilé Israẹli sì jẹ́ aláìkọlà ọkàn.”
Izip, Judah, Edom, Ammon, Moab hoi praezaek hoi angthla parai ahmuen ah kaom kaminawk boih loe tangyat hin aat o ai, Israel imthung takoh boih doeh palungthin tangyat hin aat o ai, tiah Angraeng mah thuih.

< Jeremiah 9 >