< Jeremiah 8 >
1 “‘Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, wọn yóò mú egungun àwọn ọba Juda àti egungun àwọn ìjòyè, egungun àwọn àlùfáà àti egungun àwọn wòlíì àti egungun àwọn olùgbé Jerusalẹmu kúrò nínú ibojì.
“‘Jehova ekuuga atĩ ihinda rĩu, mahĩndĩ ma athamaki na ma anene a Juda, na mahĩndĩ ma athĩnjĩri-Ngai na ma anabii, o na mahĩndĩ ma andũ a Jerusalemu nĩmakarutwo mbĩrĩra-inĩ ciao.
2 A ó yọ wọ́n síta fún oòrùn àti òṣùpá àti gbogbo àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run tí wọ́n ti fẹ́ràn tí wọ́n sì ti sìn, àti àwọn tí wọ́n ti tọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti wá tí wọ́n sì ti foríbalẹ̀ fún. Kì yóò ṣà wọ́n jọ tàbí sìn wọ́n, wọn yóò dàbí ìdọ̀tí tó wà lórí ilẹ̀.
Makaanĩkĩrwo riũa, na mweri, na njata ciothe cia igũrũ, icio mendete na magacitungatĩra, o icio maarũmĩrĩire, na magatuĩria kĩrĩra harĩ cio, na magacihooya. Mahĩndĩ macio matikoonganio kana mathikwo, no magaatuĩka ta rũrua rũharaganĩtio gũkũ thĩ.
3 Níbikíbi tí mo bá lé wọn lọ, gbogbo àwọn ìyókù wọn yóò fẹ́ ikú ju ìyè lọ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.’
Kũrĩa guothe ngaamathaamĩria, matigari mothe ma rũrĩrĩ rũrũ rwaganu, makeeriragĩria gũkua handũ ha gũtũũra muoyo, ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga.’
4 “Wí fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Bí ènìyàn bá ṣubú lulẹ̀, wọn kì í padà dìde bí? Nígbà tí ènìyàn bá yà kúrò ní ọ̀nà rẹ, kì í yí padà bí?
“Meere atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo Jehova ekuuga, “‘Andũ mangĩgũa thĩ-rĩ, githĩ maticookaga gũũkĩra? Mũndũ angĩhĩtia njĩra-rĩ, githĩ ndamĩcookagĩrĩra?
5 Èéṣe nígbà náà àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi yà kúrò lọ́nà rẹ̀? Kí ló dé tí Jerusalẹmu fi yà kúrò ní gbogbo ìgbà? Wọ́n rọ̀ mọ́ ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti yípadà.
Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte andũ aya mathiĩ na mbere kũũhutatĩra? Andũ a Jerusalemu maahutatagĩra nĩkĩ? Matũũrĩte marũmĩtie maũndũ ma maheeni, makarega gũcooka.
6 Mo ti fetísílẹ̀ dáradára, wọn kò sọ ohun tí ó tọ́. Kò sí ẹnìkan tó ronúpìwàdà nínú ìwà búburú rẹ̀, kí ó wí pé, “Kí ni mo ṣe?” Olúkúlùkù ń tọ ọ̀nà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹṣin tó ń lọ sójú ogun.
Nĩndĩmathikĩrĩirie wega mũno, no matiaragia ũndũ ũrĩa wagĩrĩire. Gũtirĩ o na ũmwe wao wĩriraga waganu wake, akoiga atĩrĩ, “Njĩkĩte ũguo nĩkĩ?” O mũndũ wao arũmagĩrĩra njĩra yake o ta mbarathi ĩtengʼerete ĩtoonye mbaara-inĩ.
7 Kódà, ẹyẹ àkọ̀ ojú ọ̀run mọ ìgbà tirẹ̀, àdàbà, alápáǹdẹ̀dẹ̀ àti lékèélékèé mọ àkókò ìṣípò padà wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kò mọ ohun tí Olúwa wọn fẹ́.
Mũrũaru ũrĩ rĩera-inĩ nĩũmenyaga mahinda maguo ma gũcooka, o nacio ndirahũgĩ, na thũngũrũrũ, na nyamĩndigi nĩcimenyaga mahinda ma cio ma gũcooka. No andũ akwa matiũĩ maũndũ marĩa Jehova endaga mekwo.
8 “‘Báwo ni ẹ̀yin ṣe lè wí pé, “Àwa gbọ́n, nítorí a ní òfin Olúwa,” nígbà tí ó jẹ́ pé kálámù èké àwọn akọ̀wé ti àwọn sọ ọ́ di ẹ̀tàn.
“‘Mwakĩhota atĩa kuuga atĩrĩ, “Tũrĩ oogĩ, nĩ ũndũ tũrĩ na watho wa Jehova,” o rĩrĩa karamu ka maheeni ka aandĩki-marũa kaũgarũrĩte gakaũtua wa maheeni?
9 Ojú yóò ti àwọn ọlọ́gbọ́n, a ó dà wọ́n láàmú, wọn yóò sì kó sí ìgbèkùn. Nítorí wọ́n ti kọ ọ̀rọ̀ Olúwa, irú ọgbọ́n wo ló kù tí wọ́n ní?
Andũ arĩa oogĩ nĩmagaconorithio; nĩmakagega na magwatio nĩ mũtego. Kuona atĩ nĩmareganĩte na ndũmĩrĩri ya Jehova, ũũgĩ ũrĩa makĩrĩ naguo nĩ ũrĩkũ?
10 Nítorí náà, èmi yóò fi ìyàwó wọn fún àwọn ọkùnrin mìíràn àti ilẹ̀ wọn fún àwọn ẹlòmíràn. Láti èyí tó kéré jù dé èyí tó dàgbà jù, gbogbo wọn ni èrè àjẹjù ń jẹ lógún; àwọn wòlíì àti àwọn àlùfáà pẹ̀lú ń hùwà ẹ̀tàn.
Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, atumia ao nĩngamaheana kũrĩ arũme angĩ, nayo mĩgũnda yao ndĩmĩheane kũrĩ andũ ageni. Kuuma ũrĩa mũnini nginya ũrĩa mũnene, othe nĩmakoroketio nĩ kwenda kwĩguna; anabii o hamwe na athĩnjĩri-Ngai, othe nĩmaheenanagia.
11 Wọ́n tọ́jú ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bí èyí tí kò jinlẹ̀. “Àlàáfíà, àlàáfíà,” ni wọ́n ń wí, nígbà tí kò sí àlàáfíà.
Mohaga kĩronda kĩa andũ akwa taarĩ kĩronda kĩa andũ matagurarĩtio mũno. Moigaga atĩrĩ, “Gwĩ thayũ, gwĩ thayũ,” o rĩrĩa gũtarĩ thayũ.
12 Ǹjẹ́ wọ́n tijú fún ìṣe ìríra wọn? Bẹ́ẹ̀ kọ́, wọn kò ní ìtìjú rárá; wọn kò tilẹ̀ mọ bí wọ́n ti ṣe ń tì jú. Nítorí náà wọn yóò ṣubú pẹ̀lú àwọn tó ti ṣubú, a ó sì wó wọ́n lulẹ̀ nígbà tí a bá bẹ̀ wọ́n wò, ni Olúwa wí.
Hihi nĩmaconokaga nĩ mũtugo ũcio wao ũrĩ magigi? Aca, maticonokaga o na hanini; o na matirĩ rũkobe. Nĩ ũndũ ũcio o nao makaagũanĩra na arĩa makaagũa; nĩmakarũndwo rĩrĩa makaaherithio, ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
13 “‘Èmi yóò mú ìkórè wọn kúrò, ni Olúwa wí. Kì yóò sí èso lórí igi àjàrà. Kì yóò sí ọ̀pọ̀tọ́ lórí igi, ewé wọn yóò sì rẹ̀ sílẹ̀. Ohun tí mo ti fi fún wọn ni à ó gbà kúrò.’”
“‘Jehova ekuuga atĩrĩ, nĩnganina magetha mao, mĩthabibũ ndĩgaakorwo ĩrĩ na thabibũ. Gũtikagĩa na ngũyũ mĩkũyũ-inĩ, namo mathangũ mayo nĩmakahooha. Kĩndũ kĩrĩa gĩothe ndĩmaheete nĩmagatunywo.’”
14 “Èéṣe tí àwa fi jókòó ní ibí yìí? A kó ara wa jọ! Jẹ́ kí a sálọ sí ìlú olódi kí a sì ṣègbé síbẹ̀. Nítorí tí Olúwa Ọlọ́run wa ti pinnu pé a ó ṣègbé. Yóò sì fún wa ní omi onímájèlé mu, nítorí àwa ti ṣẹ̀ sí i.
“Tũikarĩte haha nĩkĩ? Cookanĩrĩrai hamwe! Nĩtũũrei, tũtoonye matũũra marĩa mairigĩirwo na hinya tũgakuĩre kuo! Nĩgũkorwo Jehova Ngai witũ nĩwe ũtwathĩrĩirie gĩkuũ, agatũhe maaĩ maroge tũnyue, nĩ ũndũ nĩtũmwĩhĩirie.
15 Àwa ń retí àlàáfíà kò sí ìre kan, tí ó wá ní ìgbà ìmúláradá bí kò ṣe ìpayà nìkan.
Tũtũũrĩte twĩrĩgĩrĩire atĩ nĩgũkũgĩa thayũ, no gũtirĩ ũndũ mwega ũtũkorete, tũkerĩgĩrĩra ihinda rĩa kũhonio, no rĩrĩ, no kĩmako kĩonekaga.
16 Ìró ìfọn imú ẹṣin àwọn ọlọ̀tẹ̀ là ń gbọ́ láti Dani, yíyan àwọn akọ ẹṣin mú gbogbo ilẹ̀ wárìrì. Wọ́n wá láti pa ilẹ̀ náà run, gbogbo ohun tó wà níbẹ̀, ìlú náà àti gbogbo olùgbé ibẹ̀.
Mũtiihĩre wa mbarathi cia thũ ũraiguuo kuuma Dani; mbarathi ciao cia njamba iraania bũrũri wothe ũkainaina. Mookĩte kũrĩa bũrũri na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ kuo, na marĩe itũũra inene na arĩa othe matũũraga kuo.”
17 “Wò ó, èmi yóò rán àwọn ejò olóró sí àárín yín, paramọ́lẹ̀ tí ẹ kò lè pa oró wọn, yóò sì bù yín jẹ,” ni Olúwa wí.
“Atĩrĩrĩ, nĩngamũrehithĩria nyoka irĩ thumu gatagatĩ kanyu, ndĩmũrehithĩrie nduĩra iria itangĩhoorereka, nacio nĩikamũrũma,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
18 Olùtùnú mi, nígbà tí ìbànújẹ́ ọkàn mi, rẹ̀wẹ̀sì nínú mi.
Wee ũũhooreragia rĩrĩa ndĩ na kĩeha-rĩ, ngoro yakwa nĩĩringĩkĩte.
19 Fetí sí ẹkún àwọn ènìyàn mi láti ilẹ̀ jíjìnnà wá: “Olúwa kò ha sí ní Sioni bí? Ọba rẹ̀ kò sí níbẹ̀ mọ́ ni?” “Èéṣe tí wọ́n fi mú mi bínú pẹ̀lú ère wọn, pẹ̀lú àwọn òrìṣà àjèjì tí wọn kò níláárí?”
Ta thikĩrĩria kĩrĩro kĩa andũ akwa marĩ bũrũri wa kũraya: “Atĩrĩrĩ, githĩ Jehova ndarĩ kũu Zayuni? Mũthamaki wakuo-rĩ, kaĩ atatũũraga kuo?” “Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte maathirĩkie nĩguo ndaakare na ũndũ wa mĩhianano ĩyo yao methondekeire, makandakaria na mĩhianano ĩyo yao ya kũngĩ ĩtarĩ kĩene?”
20 “Ìkórè ti rékọjá, ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn ti parí, síbẹ̀ a kò gbà wá là.”
“Ihinda rĩa magetha nĩrĩhĩtũku, nayo hĩndĩ ya riũa ĩgathira, na tũtihonoketio.”
21 Níwọ́n ìgbà tí a pa àwọn ènìyàn mi run, èmi náà run pẹ̀lú, èmi ṣọ̀fọ̀, ìrora sì mú mi káká.
Kuona atĩ andũ akwa nĩmahehenjetwo-rĩ, o na niĩ ndĩmũhehenje; nĩndĩracaaya na nĩnyiitĩtwo nĩ kĩmako kĩnene.
22 Kò ha sí ìkunra ní Gileadi bí? Kò ha sí àwọn oníṣègùn níbẹ̀? Kí ló ha dé tí kò fi sí ìwòsàn fún ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi?
Kaĩ gũtarĩ ndawa kũu Gileadi? Gũtirĩ mũthondekani kuo? Ironda cia andũ akwa cikĩagĩte kũhona nĩkĩ?