< Jeremiah 8 >

1 “‘Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, wọn yóò mú egungun àwọn ọba Juda àti egungun àwọn ìjòyè, egungun àwọn àlùfáà àti egungun àwọn wòlíì àti egungun àwọn olùgbé Jerusalẹmu kúrò nínú ibojì.
Te tue vaengkah BOEIPA olphong loh Judah manghai rhoek kah a rhuh neh a mangpa rhoek kah a rhuh, khosoih rhoek kah a rhuh neh tonghma rhoek kah a rhuh khaw, Jerusalem khosa rhoek kah a rhuh te a phuel lamloh a khuen rhoe a khuen uh ni.
2 A ó yọ wọ́n síta fún oòrùn àti òṣùpá àti gbogbo àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run tí wọ́n ti fẹ́ràn tí wọ́n sì ti sìn, àti àwọn tí wọ́n ti tọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti wá tí wọ́n sì ti foríbalẹ̀ fún. Kì yóò ṣà wọ́n jọ tàbí sìn wọ́n, wọn yóò dàbí ìdọ̀tí tó wà lórí ilẹ̀.
Te vaengah khomik neh, hla neh, vaan caempuei boeih taengah a yaal uh ni. Te ni a lungnah uh tih a thothueng thil uh. Te te a hnukah a pongpa uh tih te te a toem uh, a bawk uh. Tedae hloem uh pawt vetih up uh mahpawh, diklai hman ah aek bangla om ni.
3 Níbikíbi tí mo bá lé wọn lọ, gbogbo àwọn ìyókù wọn yóò fẹ́ ikú ju ìyè lọ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.’
Aka coih cako lamkah a meet boeih loh hingnah lakah dueknah te a tuek ni. Hmuen takuem kah boethae neh aka sueng rhoek he ka heh ni. Caempuei BOEIPA kah olphong ni.
4 “Wí fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Bí ènìyàn bá ṣubú lulẹ̀, wọn kì í padà dìde bí? Nígbà tí ènìyàn bá yà kúrò ní ọ̀nà rẹ, kì í yí padà bí?
Te phoeiah amih te thui pah. BOEIPA loh he ni a thui. A cungku uh atah thoo uh pawt nim? A mael atah ha mael mahpawt nim?
5 Èéṣe nígbà náà àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi yà kúrò lọ́nà rẹ̀? Kí ló dé tí Jerusalẹmu fi yà kúrò ní gbogbo ìgbà? Wọ́n rọ̀ mọ́ ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti yípadà.
Pilnam he balae tih a mael? Jerusalem tah hnuknong la a mawt tih a huep te a ngaitoeih uh dongah ha mael ham a aal uh.
6 Mo ti fetísílẹ̀ dáradára, wọn kò sọ ohun tí ó tọ́. Kò sí ẹnìkan tó ronúpìwàdà nínú ìwà búburú rẹ̀, kí ó wí pé, “Kí ni mo ṣe?” Olúkúlùkù ń tọ ọ̀nà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹṣin tó ń lọ sójú ogun.
Ka hnatung tih ka hnatun a thuem la a thui uh moenih. A saii boeih te balae ti ham khaw a thae dongah dam aka ti hlang a om moenih. A yong a yong doeah caemtloek la aka vikvuek marhang bangla mael.
7 Kódà, ẹyẹ àkọ̀ ojú ọ̀run mọ ìgbà tirẹ̀, àdàbà, alápáǹdẹ̀dẹ̀ àti lékèélékèé mọ àkókò ìṣípò padà wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kò mọ ohun tí Olúwa wọn fẹ́.
Vaan kah bungrho long khaw a tingtunnah a ming tih vahui neh marhang, marhang neh langloep loh a rhaai tue a ngaithuen. Tedae ka pilnam loh BOEIPA kah laitloeknah te ming uh pawh.
8 “‘Báwo ni ẹ̀yin ṣe lè wí pé, “Àwa gbọ́n, nítorí a ní òfin Olúwa,” nígbà tí ó jẹ́ pé kálámù èké àwọn akọ̀wé ti àwọn sọ ọ́ di ẹ̀tàn.
Metlam lae kaimih taengah BOEIPA kah olkhueng om tih ka cueih na ti uh. Tedae cadaek rhoek kah laithae cacung a muk te laithae rhoe la he.
9 Ojú yóò ti àwọn ọlọ́gbọ́n, a ó dà wọ́n láàmú, wọn yóò sì kó sí ìgbèkùn. Nítorí wọ́n ti kọ ọ̀rọ̀ Olúwa, irú ọgbọ́n wo ló kù tí wọ́n ní?
Aka cueih rhoek te yak uh vetih rhihyawp dongah man uh ni. BOEIPA kah olka a hnawt uh dongah amih ham mebang cueihnah nim aka om te?
10 Nítorí náà, èmi yóò fi ìyàwó wọn fún àwọn ọkùnrin mìíràn àti ilẹ̀ wọn fún àwọn ẹlòmíràn. Láti èyí tó kéré jù dé èyí tó dàgbà jù, gbogbo wọn ni èrè àjẹjù ń jẹ lógún; àwọn wòlíì àti àwọn àlùfáà pẹ̀lú ń hùwà ẹ̀tàn.
Te dongah a yuu rhoek te a tloe taengla, a khohmuen te aka pang taengla ka paek tangloeng pawn ni. Tanoe lamloh kangham hil a mueluemnah ham boeih a mueluem. Tonghma lamkah khosoih hil a pum la laithae a saii.
11 Wọ́n tọ́jú ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bí èyí tí kò jinlẹ̀. “Àlàáfíà, àlàáfíà,” ni wọ́n ń wí, nígbà tí kò sí àlàáfíà.
Ka pilnam canu kah pocinah te vapsa la a toi uh. Rhoepnah rhoepnah a ti ham vaengah rhoepnah om pawh.
12 Ǹjẹ́ wọ́n tijú fún ìṣe ìríra wọn? Bẹ́ẹ̀ kọ́, wọn kò ní ìtìjú rárá; wọn kò tilẹ̀ mọ bí wọ́n ti ṣe ń tì jú. Nítorí náà wọn yóò ṣubú pẹ̀lú àwọn tó ti ṣubú, a ó sì wó wọ́n lulẹ̀ nígbà tí a bá bẹ̀ wọ́n wò, ni Olúwa wí.
A yah ham tueilaehkoi la a saii vaengah a yah ham om dae yak pawt tih hmaithae khaw ming uh pawh. Te dongah amih cawhnah tue ah aka cungku lakli ah cungku uh van vetih paloe uh ni.
13 “‘Èmi yóò mú ìkórè wọn kúrò, ni Olúwa wí. Kì yóò sí èso lórí igi àjàrà. Kì yóò sí ọ̀pọ̀tọ́ lórí igi, ewé wọn yóò sì rẹ̀ sílẹ̀. Ohun tí mo ti fi fún wọn ni à ó gbà kúrò.’”
Amih te boeih ka coi vetih ka thup ni. BOEIPA kah olphong ni. Misur dongah misurthaih om mahpawh. Thaibu dongah thaibu thaih om pawt vetih a hnah khaw hoo ni. Amih aka paan te amih taengla ka paek ni.
14 “Èéṣe tí àwa fi jókòó ní ibí yìí? A kó ara wa jọ! Jẹ́ kí a sálọ sí ìlú olódi kí a sì ṣègbé síbẹ̀. Nítorí tí Olúwa Ọlọ́run wa ti pinnu pé a ó ṣègbé. Yóò sì fún wa ní omi onímájèlé mu, nítorí àwa ti ṣẹ̀ sí i.
Balae tih mamih n'ngol sut. Tingtun uh sih lamtah hmuencak khopuei la ael uh sih. Mamih kah BOEIPA Pathen loh mamih n'kuemsuem sak dongah pahoi kuemsuem uh sih. BOEIPA taengah n'tholh uh dongah sue tui ni mamih n'tul coeng.
15 Àwa ń retí àlàáfíà kò sí ìre kan, tí ó wá ní ìgbà ìmúláradá bí kò ṣe ìpayà nìkan.
Sading ham lamtawn dae a then om pawh, hoeihnah tue ham vaengah letnah la poeh he.
16 Ìró ìfọn imú ẹṣin àwọn ọlọ̀tẹ̀ là ń gbọ́ láti Dani, yíyan àwọn akọ ẹṣin mú gbogbo ilẹ̀ wárìrì. Wọ́n wá láti pa ilẹ̀ náà run, gbogbo ohun tó wà níbẹ̀, ìlú náà àti gbogbo olùgbé ibẹ̀.
A marhang a phit te Dan lamloh a yaak, a lueng kah a kawk ol ah diklai tom hinghuen. Ha pawk uh vaengah khohmuen neh a khopuei boeih, a khuikah khosa boeih te a yoop.
17 “Wò ó, èmi yóò rán àwọn ejò olóró sí àárín yín, paramọ́lẹ̀ tí ẹ kò lè pa oró wọn, yóò sì bù yín jẹ,” ni Olúwa wí.
Rhulthae rhul te nangmih taengah kan tueih coeng he. Te rhoek te calthai nen khaw a coeng pawt dongah nangmih n'tuk ni.
18 Olùtùnú mi, nígbà tí ìbànújẹ́ ọkàn mi, rẹ̀wẹ̀sì nínú mi.
Ka mongnah khaw ka khuikah kothaenah dongah ka lungbuei tah hal coeng.
19 Fetí sí ẹkún àwọn ènìyàn mi láti ilẹ̀ jíjìnnà wá: “Olúwa kò ha sí ní Sioni bí? Ọba rẹ̀ kò sí níbẹ̀ mọ́ ni?” “Èéṣe tí wọ́n fi mú mi bínú pẹ̀lú ère wọn, pẹ̀lú àwọn òrìṣà àjèjì tí wọn kò níláárí?”
khohla bangsang kho lamkah ka pilnam nu kah a pang ol la ke. Zion ah BOEIPA a om moenih a? A manghai khaw a khuiah a om moenih a? Balae tih kholong kah a mueidaep neh a honghi la kai m'veet uh.
20 “Ìkórè ti rékọjá, ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn ti parí, síbẹ̀ a kò gbà wá là.”
Cangah a poeng tih khohal khaw bawt coeng dae mamih tah n'khang moenih.
21 Níwọ́n ìgbà tí a pa àwọn ènìyàn mi run, èmi náà run pẹ̀lú, èmi ṣọ̀fọ̀, ìrora sì mú mi káká.
Ka pilnam nu pocinah dongah kopang neh ka paep tih imsuep bangla kai n'kolek.
22 Kò ha sí ìkunra ní Gileadi bí? Kò ha sí àwọn oníṣègùn níbẹ̀? Kí ló ha dé tí kò fi sí ìwòsàn fún ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi?
Gilead ah thingpi a om moenih a? Te ah te aka hoeih sak khaw om tangloeng pawh. Balae tih ka pilnam nu kah sadingnah loh ha pawk pawh.

< Jeremiah 8 >