< Jeremiah 6 >

1 “Ẹ̀yin ènìyàn Benjamini, sá sí ibi ààbò! Ẹ sá kúrò ní Jerusalẹmu. Ẹ fọn fèrè ní Tekoa! Kí ẹ gbé àmì sókè lórí Beti-Hakeremu! Nítorí àjálù farahàn láti àríwá, àní ìparun tí ó lágbára.
Aw Benjamin kaminawk, Jerusalem hoi cawnh hanah amsak oh, Tekoa ah mongkah to ueng oh! Beth-Haccerem ah angmathaih hmai to paang oh; zit kaom amrohaih loe aluek bang hoiah angzoh boeh.
2 Èmi yóò pa ọmọbìnrin Sioni run, tí ó jẹ́ arẹwà àti ẹlẹgẹ́.
Kranghoih kanawk tuep Zion canu to kam rosak han.
3 Olùṣọ́-àgùntàn pẹ̀lú agbo wọn yóò gbóguntì wọ́n. Wọn yóò pa àgọ́ yí wọn ká, olúkúlùkù yóò máa jẹ ní ilé rẹ̀.”
Tuutoep kaminawk loe angmacae ih tuunawk hoiah nihcae khaeah caeh o ueloe, anih tuk hanah ataeng boih ah kahni imnawk to sah o thui tih, kami boih mah angmacae ih ahmuen ah tuu to pacah o tih.
4 “Ẹ ya ará yín sí mímọ́ láti bá a jagun! Dìde, kí a kọlù ú ní ìgbà ọ̀sán! Ṣùgbọ́n ó ṣe, nítorí ọjọ́ lọ tán, ọjọ́ alẹ́ náà sì gùn sí i.
Anih tuk hanah om o coek ah; angthawk oh athun ah caeh o si. Toe aicae loe khosak a bing o boeh! Niduem boeh, kho doeh ving boeh.
5 Nítorí náà, ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú ní àṣálẹ́ kí a sì ba odi alágbára rẹ̀ jẹ́.”
To pongah angthawk oh, khoving ah tuh o si loe, a oh o haih ahmuen to phrae pae o si.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ ké àwọn igi náà lulẹ̀ kí ẹ sì mọ odi ààbò yí Jerusalẹmu ká. Èyí ni ìlú títóbi tí a ó bẹ̀wò, nítorí pé ó kún fún ìninilára.
Misatuh Angraeng mah hae tiah thuih; thingnawk to pakhru oh loe, Jerusalem tuk hanah long to takae oh; hae vangpui loe thuitaek han oh; a thungah loe pacaekthlaekhaih hoiah koi boeh.
7 Gẹ́gẹ́ bí kànga ṣe ń da omi inú rẹ̀ sílẹ̀, náà ni ó ń tú ìwà búburú rẹ̀ jáde. Ìwà ipá àti ìparun ń tún pariwo nínú rẹ̀; nígbà gbogbo ni àìsàn àti ọgbẹ́ rẹ̀ ń wà níwájú mi.
Tuipuek mah tui tacawtsak baktih toengah, anih mah sethaih to tacawtsak boeh; a thungah athii longhaih hoi amrohaih lok to ka thaih; ka hmaa ah apet ai ah palungsethaih hoi ahma caakhaih to oh.
8 Ìwọ Jerusalẹmu, gba ìkìlọ̀, kí Èmi kí ó má ba à lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, kí n sì sọ ilẹ̀ rẹ di ahoro, tí kò ní ní olùgbé.”
Aw Jerusalem, thuitaekhaih to talawk ah; to tih ai nahaeloe nang khae hoiah ka hinghaih tacawt ving ueloe, prae to kami om ai ah kang pongsak sut moeng tih, tiah a thuih.
9 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Jẹ́ kí wọn pèsè ìyókù Israẹli ní tónítóní bí àjàrà; na ọwọ́ rẹ sí àwọn ẹ̀ka nì lẹ́ẹ̀kan sí i gẹ́gẹ́ bí ẹnìkan ti í kó èso àjàrà jọ.”
Misatuh Angraeng mah hae tiah thuih; kanghmat misur thaih pakhrik baktiah, kanghmat Israel to pakhrik o tih, misur thaih pakhrik kami mah benthang thungah ban tapawh baktiah, na ban to tapawh let ah, tiah a thuih.
10 Ta ni ẹni tí mo lè bá sọ̀rọ̀ àti tí mo lè fún ní ìmọ̀ràn? Ta ni yóò tẹ́tí sílẹ̀ sí mi? Etí wọn ti di, nítorí náà wọn kò lè gbọ́. Ọ̀rọ̀ Olúwa, jẹ́ ohun búburú sí wọn, wọn kò sì ní inú dídùn nínú rẹ̀.
Nihcae mah tahngaih o hanah, mi khaeah maw lok ka thuih moe, acoehaih to ka paek han? Khenah, nihcae loe naa tangyat aat o ai pongah, thaih o kop ai; khenah, Angraeng ih lok to a pahuep o kaak moe, thaih han koeh o ai.
11 Èmi kún fún ìbínú Olúwa, èmi kò sì le è pa á mọ́ra. “Tú u sí orí àwọn ọmọ ńigboro, àti sórí àwọn ọmọkùnrin tí wọn kó ra wọn jọ pọ̀, àti ọkọ àti aya ni a ò mú sínú rẹ̀, àti àwọn arúgbó tí ó ní ọjọ́ kíkún lórí.
To pongah kai loe Angraeng palungphuihaih hoiah koi boeh moe, ka pauep thai ai boeh; tasa bangah kaom nawktanawk hoi nawnto angpop thendoengnawk nuiah ka kraih han boeh; zu sava hoi saning kacoeh mitongnawk to ka lak ving han.
12 Ilé wọn o sì di ti ẹlòmíràn, oko wọn àti àwọn aya wọn, nígbà tí èmi bá na ọwọ́ mi sí àwọn olùgbé ilẹ̀ náà,” ni Olúwa wí.
Nihcae ih imnawk, lawk hoi a zunawk doeh, minawk khaeah ka paek moe, prae thungah kaom kaminawk nuiah ban ka payangh thuih han, tiah Angraeng mah thuih.
13 “Láti orí ẹni tí ó kéré sí orí ẹni tí ó tóbi ju, gbogbo wọn ni ó sì ní ojúkòkòrò fún èrè, àwọn wòlíì àti àlùfáà lápapọ̀ sì kún fún ẹ̀tàn.
Kathoeng koek hoi kalen koek khoek to kami boih kamthlai koeh hmoekhaih hoiah koi o; tahmaa hoi qaima doeh lah ai, lok amlai o boih.
14 Wọ́n sì ń wo ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi bí ẹni pé kò tó nǹkan. Wọ́n ń wí pé, ‘Àlàáfíà, Àlàáfíà,’ nígbà tí kò sì sí àlàáfíà.
Monghaih om ai to mah, monghaih, monghaih, tiah a thuih o moe, kai ih kami ah kaom canunawk ih ahma cakhaih loe nung parai ai, tiah a naa o.
15 Ojú ha a tì wọ́n nítorí ìwà ìríra wọn bí? Rárá, wọn kò ní ìtìjú mọ́, wọn kò tilẹ̀ ní oorun ìtìjú. Nítorí náà, wọn ó ṣubú láàrín àwọn tó ṣubú, a ó sì ké wọn lulẹ̀ nígbà tí mo bá bẹ̀ wọ́n wò,” ni Olúwa wí.
Nihcae mah panuet thok hmuennawk sak o naah azat o maw? Azat o ai, azathaih roe tawn o ai, mikhmai mataeng doeh sae o ai; to pongah nihcae loe kamtimh kaminawk salakah amtim o tih; nihcae ka thuitaekhaih atue phak naah loe, nihcae to atlim ah pakhrah o tih, tiah Angraeng mah thuih.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Ẹ dúró sí ìkóríta, kí ẹ sì wò, ẹ béèrè fún ọ̀nà àtijọ́, ẹ béèrè ọ̀nà dáradára nì, kí ẹ rìn nínú rẹ, ẹ̀yin yóò sì rí ìsinmi fún ọkàn yín. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, ‘Àwa kì yóò rìn nínú rẹ̀.’
Angraeng mah hae tiah thuih, Lamkrung ah angdoe ah loe khenah; canghnii ih loklamnawk to dueng oh, kahoih loklam to dueng oh loe, to loklam ah caeh oh, to tiah nahaeloe na pakhranawk mah anghakhaih to hnu o tih. Toe nihcae mah to ah ka caeh o mak ai, tiah thuih o.
17 Èmi yan olùṣọ́ fún un yín, mo sì wí pé: ‘Tẹ́tí sí dídún fèrè náà,’ ẹ̀yìn wí pé, ‘Àwa kì yóò tẹ́tí sílẹ̀.’
Mongkah lok to tahngai oh; nangcae toepkung kaminawk to kang suek pae, tiah ka naa. Toe nihcae mah, Ka tahngai o mak ai, tiah thuih o.
18 Nítorí náà, gbọ́ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè; kíyèsi, kí ẹ sì jẹ́ ẹlẹ́rìí, ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí wọn.
To pongah prae kaminawk boih, tahngai oh; Aw minawk salakah kaom kaminawk panoek oh.
19 Gbọ́, ìwọ ayé! Mò ń mú ìparun bọ̀ sórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, èso ìrò inú wọn, nítorí wọn kò fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, wọ́n sì ti kọ òfin mi sílẹ̀.
Aw long, tahngai ah; khenah, nihcae loe ka thuih ih loknawk to tahngai o ai, ka patuk ih lok doeh pazui o ai, pahnawt o sut pongah, angmacae poekhaih thingthai ah kaom, amrohaih to hae kaminawk nuiah ka phaksak han.
20 Èrè wo ni ó wà fún mi nínú tùràrí láti Ṣeba wá, tàbí èso dáradára láti ilẹ̀ jíjìn réré? Ẹbọ sísun yín kò ṣe ìtẹ́wọ́gbà, ọrẹ yín kò sì wù mí.”
Judah kaminawk tih hanah Sheba ih hmuihoih tui hoi angthla parai prae ih hmuihoih tui kai khaeah nang sin o loe? Na sak o ih hmai angbawnhaih to ka talawk mak ai; na sak o ih angbawnhaih hmuennawk mah kai palung anghoesak ai.
21 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Èmi yóò gbé ohun ìdènà síwájú àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Àwọn baba àti ọmọ yóò jùmọ̀ ṣubú lù wọ́n, àwọn aládùúgbò àti ọ̀rẹ́ yóò ṣègbé.”
To pongah Angraeng mah hae tiah thuih; khenah, hae kaminawk hmaa ah pakaakung ka suek pae han; ampanawk hoi a caanawk loe to ah nawnto amthaek o tih; imtaeng kami hoi angmah ih ampui doeh amro tih, tiah thuih.
22 Báyìí ni Olúwa wí: “Wò ó, àwọn ọmọ-ogun ń bọ̀ wá láti ilẹ̀ àríwá, a ó sì gbé orílẹ̀-èdè ńlá dìde láti òpin ayé wá.
Angraeng mah hae tiah thuih; Khenah, aluek bang hoiah acaeng maeto angzo tih; long boenghaih hoiah kalen parai acaeng to ka pahruek han.
23 Wọ́n sì dìmọ́ra pẹ̀lú ọrun àti ọ̀kọ̀, wọ́n jẹ́ ẹni ibi, wọn kò sì ní àánú. Wọ́n ń hó bí omi Òkun, bí wọ́n ti ṣe ń gun àwọn ẹṣin wọn lọ; wọ́n sì wá bí ọkùnrin tí yóò jà ọ́ lógun, ìwọ ọmọbìnrin Sioni.”
Nihcae loe kalii hoi tayae to sin o tih; nihcae loe hmawsaeng o moe, tahmenhaih tawn o ai; nihcae ih lok loe angthawk tuiphu tuen baktiah tuenh; Aw Zion canu, nihcae loe misatuh kaminawk baktiah amthoep o, hrang nuiah angthueng o moe, nang tuk hanah angzoh o boeh, tiah a thuih.
24 Àwa ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn, ọwọ́ wa sì di rírọ, ìrora sì mú wa bí obìnrin tí ń rọbí.
To naah kaminawk mah, nihcae ih tamthang ka thaih o naah, kaicae ih ban loe thazok sut; nongpata mah ca tapen tom naah tong ih kana baktiah, patangkhanghaih hoi raihaih to ka tong o, tiah thuih o.
25 Má ṣe jáde lọ sí orí pápá tàbí kí o máa rìn ní àwọn ojú ọ̀nà, nítorí ọ̀tá náà ní idà, ìpayà sì wà níbi gbogbo.
Sithaw mah, praezaek ah caeh o hmah, loklam ah doeh amkae o hmah, misa loe sumsen to sin moe, ahmuen kruekah amkaeh pongah zit han oh, tiah thuih.
26 Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀, kí ẹ sì sùn nínú eérú, ẹ ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ìpohùnréré ẹkún gẹ́gẹ́ bí i lórí ọmọkùnrin yín kan ṣoṣo nítorí pé lójijì ni àwọn apanirun yóò kọlù wá.
Aw kai kaminawk ih canu, kazii to angzaeng oh loe, maiphu pongah amlet oh; maeto khue a tawnh ih capa to duek naah qah baktiah qah oh loe palungsae oh; parokung loe akra ai ah aicae nuiah pha tih boeh.
27 “Èmi ti fi ẹ́ ṣe ẹni tí yóò máa yọ́ irú àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bi irin tútù, kí wọn kí ó lè ṣe àkíyèsí, kí ó sì dán ọ̀nà wọn wò.
Sithaw mah, kai ih kaminawk khosakhaih tuinuen to na panoek thai hanah, kai ih kaminawk tanoek kami hoi nihcae abuephaih ah kang suek boeh.
28 Ọlọ́tẹ̀ tí ọkàn rẹ̀ le ní gbogbo wọn. Wọ́n ń lọ káàkiri láti sọ̀rọ̀-òdì. Wọ́n jẹ́ idẹ àti irin, wọ́n sì kún fún ìwà ìbàjẹ́.
Nihcae loe palungthah kami, laisaep thaih kami ah oh o; sumkamling hoi sum baktiah a oh o moe, kamrosak thaih hmuen ah a oh o.
29 Ewìrì a fẹ́ná kíkankíkan, kí ó lè yọ́ òjé, ẹni tí ń yọ́ ọ ń yọ́ ọ lásán; a kò si ya ènìyàn búburú kúrò.
Hmai to cenh moe, hmai doeh angqong boeh, sum doeh amkaw boeh; toe atui pacii kami mah pacii ih atui loe azom pui ah ni oh; kasae kaminawk ih sethaih loe cing thai ai.
30 A pè wọ́n ní fàdákà tí a kọ̀sílẹ̀, nítorí Olúwa ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀.”
Angraeng mah nihcae to pahnawt sut boeh pongah, kaminawk mah nihcae loe pahnawt sut ih sumkanglung, tiah kawk o tih.

< Jeremiah 6 >