< Jeremiah 52 >

1 Sedekiah jẹ́ ọmọ ọdún mọ́kànlélógún nígbà tí ó jẹ ọba. Ọdún mọ́kànlá ló fi jẹ ọba ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Hamutali ọmọ Jeremiah; láti Libina ló ti wá.
Zedekia aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ũmwe rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka ikũmi na ũmwe. Nyina eetagwo Hamutali mwarĩ wa Jeremia; nake oimĩte Libina.
2 Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa gẹ́gẹ́ bí Jehoiakimu ti ṣe.
Nake agĩĩka maũndũ mooru maitho-inĩ ma Jehova, o ta ũrĩa Jehoiakimu eekĩte.
3 Nítorí ìbínú Olúwa ni gbogbo èyí ṣe ṣẹlẹ̀ sí Jerusalẹmu àti Juda àti ní ìkẹyìn. Ó sì gbà wọ́n gbọ́ ní iwájú rẹ̀. Sedekiah ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Babeli.
Na nĩ ũndũ wa marakara ma Jehova-rĩ, nĩkĩo maũndũ macio mothe meekĩkire kũu Jerusalemu na Juda, na mũthia-inĩ akĩmaingata mehere mbere yake. Na rĩrĩ, Zedekia akĩremera mũthamaki wa Babuloni, akĩaga gwathĩka.
4 Nígbà tí ó di ọdún kẹsànán ti Sedekiah tí ń ṣe ìjọba ní ọjọ́ kẹwàá, oṣù kẹwàá Nebukadnessari ọba Babeli sì lọ sí Jerusalẹmu pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, wọ́n pàgọ́ sí ẹ̀yìn odi ìlú náà; wọ́n sì mọ odi yíká rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio mwaka-inĩ wa kenda wa ũthamaki wa Zedekia, mũthenya wa ikũmi wa mweri wa ikũmi-rĩ, Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni agĩthiĩ kũhũũrana na Jerusalemu arĩ na ita rĩake rĩothe, nao makĩamba hema nja ya itũũra rĩu inene, na magĩaka ihumbu cia tĩĩri mĩena yothe yarĩo cia kũmateithia gũtharĩkĩra itũũra rĩu.
5 Ìlú náà sì wá lábẹ́ ìhámọ́ títí di ọdún kọkànlá ọba Sedekiah.
Narĩo itũũra rĩu inene rĩgĩikara rĩrĩ irigiicĩrie nginya mwaka wa ikũmi na ũmwe wa ũthamaki wa Zedekia.
6 Ní ọjọ́ kẹsànán, oṣù mẹ́rin ìyàn ìlú náà sì ti burú dé ibi pé kò sí oúnjẹ kankan mọ́ fún àwọn ènìyàn láti jẹ.
Na rĩrĩ, mũthenya wa kenda wa mweri wa kana, ngʼaragu ĩkĩneneha mũno kũu itũũra-inĩ, o nginya gũkĩaga irio cia kũrĩĩo nĩ andũ a bũrũri ũcio.
7 Bákan náà, odi ìlú náà ti ya àwọn ọmọ-ogun sì tí sálọ. Wọn fi ìlú náà sílẹ̀ ní òru nípa ojú ọ̀nà tó wà láàrín odi méjèèjì lẹ́bàá ọgbà ọba. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, àwọn ará Babeli yìí yí ìlú náà ká. Wọ́n sá gba aginjù lọ.
Hĩndĩ ĩyo rũthingo rwa itũũra rĩu inene rũkĩmomorwo, nacio mbũtũ ciothe cia ita ikĩũra. Moimire itũũra-inĩ ũtukũ magereire kĩhingo-inĩ kĩrĩa kĩarĩ gatagatĩ ga thingo cierĩ hakuhĩ na mũgũnda wa mũthamaki, o na gũtuĩka andũ a Babuloni nĩmarigiicĩirie itũũra rĩu inene rĩothe. Nao makĩũra merekeire Araba,
8 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ogun Babeli lépa ọba Sedekiah wọ́n sì le bá ni pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko. Gbogbo àwọn ọmọ-ogun sì pínyà, kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ wọ́n sì túká.
no mbũtũ ya ita ya Babuloni ĩgĩtengʼeria Mũthamaki Zedekia nginya ĩkĩmũkinyĩra werũ-inĩ ũrĩa mwaraganu wa Jeriko. Thigari ciake ciothe ikĩamũranio nake ikĩhurunjwo.
9 Wọ́n sì mu ní ìgbèkùn. Wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli, ní Ribla ní ilẹ̀ Hamati níbẹ̀ ni ó ti ṣe ìdájọ́ lórí rẹ̀.
Nayo mbũtũ ya ita ya Babuloni ĩkĩnyiita Mũthamaki Zedekia. Makĩmũtwara kũrĩ mũthamaki wa Babuloni ũrĩa warĩ kũu Ribila, bũrũri-inĩ wa Hamathu, na kũu nĩkuo aamũtuĩrĩire ciira.
10 Ní Ribla ni ọba Babeli ti pa ọmọkùnrin Sedekiah lójú rẹ̀; ó sì tún pa gbogbo àwọn aláṣẹ Juda.
Mũthamaki wa Babuloni arĩ kũu Ribila nĩoragithirie ariũ a Zedekia o hau maitho-inĩ ma ithe wao; agĩcooka akĩũragithia anene othe a Juda.
11 Lẹ́yìn náà, ọba Babeli yọ Sedekiah ní ojú, o sì fi ẹ̀wọ̀n dè é, ó sì gbe e lọ sí Babeli níbi tí ó ti fi sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.
Nĩacookire agĩkũũrithia Zedekia maitho, na akĩmuoha na bĩngũ cia gĩcango, akĩmũtwara Babuloni, na kũu akĩmũikia njeera nginya mũthenya ũrĩa aakuire.
12 Ní ọjọ́ kẹwàá oṣù karùn-ún, tí ó jẹ́ ọdún kọkàndínlógún Nebukadnessari ọba Babeli, ni Nebusaradani balógun ìṣọ́ wá sí Jerusalẹmu.
Mũthenya wa ikũmi wa mweri wa ĩtano, mwaka-inĩ wa ikũmi na kenda wa gũthamaka kwa Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni-rĩ, Nebuzaradani mũnene wa arangĩri a mũthamaki wa Babuloni, ũrĩa watungataga mũthamaki wa Babuloni, agĩũka Jerusalemu,
13 Ó dáná sun pẹpẹ Olúwa, ààfin ọba àti gbogbo àwọn ilé Jerusalẹmu. Ó sì dáná sun gbogbo àwọn ilé ńlá ńlá.
agĩcina hekarũ ya Jehova, na nyũmba ya ũthamaki, o na nyũmba ciothe cia Jerusalemu. Ningĩ agĩcina nyũmba o yothe yarĩ ya bata kuo.
14 Gbogbo àwọn ogun Babeli, tí ó wà lọ́dọ̀ olórí ẹ̀ṣọ́, wó ògiri tí ó yí Jerusalẹmu ká lulẹ̀.
Nayo mbũtũ yothe ya ita ya Babuloni, ĩtongoretio nĩ mũnene ũcio wa arangĩri a mũthamaki, ĩkĩmomora thingo ciothe iria ciathiũrũrũkĩirie Jerusalemu.
15 Nebusaradani balógun ìṣọ́ kó gbogbo àwọn tálákà àti gbogbo àwọn tí ó kù ní ìlú, ní ìgbèkùn lọ sí Babeli, pẹ̀lú àwọn tí ó ya lọ, tí ó sì ya tọ ọba Babeli lọ, àti ìyókù àwọn ènìyàn náà.
Nebuzaradani ũcio warĩ mũnene wa arangĩri a mũthamaki nĩatahire andũ amwe arĩa maarĩ athĩĩni mũno, na andũ arĩa maatigaire kũu itũũra-inĩ rĩu inene, hamwe na mabundi marĩa mangĩ, o na andũ arĩa metwarĩte o ene kũrĩ mũthamaki wa Babuloni.
16 Ṣùgbọ́n Nebusaradani, balógun ìṣọ́ fi àwọn tálákà tó kú ní ilẹ̀ náà sílẹ̀ láti máa ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà àti ro oko.
No Nebuzaradani nĩatigire andũ amwe arĩa maarĩ athĩĩni mũno a bũrũri ũcio kuo, nĩguo marutage wĩra mĩgũnda-inĩ ya mĩthabibũ na mĩgũnda-inĩ ĩrĩa ĩngĩ.
17 Àwọn ará Babeli fọ́ ọ̀wọ̀n idẹ wọ̀n-ọn-nì àti àwọn ìjókòó wọ̀n-ọn-nì, àti agbada idẹ títóbi wọ̀n-ọn-nì tí ń bẹ ní ilé Olúwa, àwọn ará Babeli fọ́ túútúú, wọ́n sì kó gbogbo idẹ náà lọ sí Babeli.
Andũ a Babuloni makiunanga itugĩ cia gĩcango, na metha cia kũigĩrĩrwo indo, na Karia karĩa kaarĩ ga gĩcango, iria ciarĩ thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova, magĩkuua gĩcango kĩu gĩothe magĩgĩtwara Babuloni.
18 Bákan náà, wọ́n tún kó àwọn ìkòkò wọ̀n-ọn-nì, ọkọ́ wọ̀n-ọn-nì àti ọ̀pá fìtílà wọ̀n-ọn-nì, àwọn ọpọ́n wọ̀n-ọn-nì, ṣíbí wọ̀n-ọn-nì àti gbogbo ohun èlò idẹ tí wọ́n ń lò níbi pẹpẹ lọ.
Ningĩ magĩkuua nyũngũ, na icakũri, na magathĩ ma gũtinia ndaambĩ, na mbakũri cia kũminjaminjĩria maaĩ, na thaani, o na indo ciothe cia gĩcango iria ciahũthagĩrwo wĩra-inĩ wa hekarũ, magĩthiĩ nacio.
19 Balógun ìṣọ́ náà kó àwokòtò wọ̀n-ọn-nì, ohun ìfọnná wọ̀n-ọn-nì, ọpọ́n wọ̀n-ọn-nì, ìkòkò wọ̀n-ọn-nì, ọ̀pá fìtílà wọ̀n-ọn-nì, ṣíbí wọ̀n-ọn-nì àti ago wáìnì wọ̀n-ọn-nì; èyí tí a fi wúrà àti fàdákà ṣe lọ.
Mũnene ũcio wa thigari cia mũthamaki nĩakuuire mbakũri iria nene, na Ngĩo, na mbakũri cia kũminjaminjĩria maaĩ, na nyũngũ, na mĩtĩ ya matawa, na thaani, o na mbakũri iria ciahũthagĩrwo na kũruta maruta ma kũnyuuo, iria ciothe ciathondeketwo na thahabu ĩrĩa therie kana betha.
20 Àwọn ọ̀wọ́n méjì, agbada ńlá kan àti àwọn màlúù idẹ méjìlá tí ó wà lábẹ́ ìjókòó alágbéká tí Solomoni ọba ṣe fún ilé Olúwa, idẹ ni gbogbo ohun èlò wọ̀nyí, ó ju èyí tí a lè wọ́n lọ.
Gĩcango kĩrĩa kĩarutirwo itugĩ-inĩ icio cierĩ, na Karia kau, na ndegwa iria ikũmi na igĩrĩ cia gĩcango iria ciarĩ rungu rwako, na metha, iria Mũthamaki Solomoni aathondekete cia hekarũ ya Jehova, gĩtingĩathimĩkire nĩ kũingĩha.
21 Ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọ̀wọ́n yìí ni ga ní ìwọ̀n ìgbọ̀nwọ́ méjìdínlógún; okùn ìgbọ̀nwọ́ méjìlá sì yí i ká. Ọ̀kọ̀ọ̀kan nípọn tó ìka mẹ́rin, wọ́n sì ní ihò nínú.
O gĩtugĩ kĩmwe gĩacio kĩarĩ kĩa mĩkono ikũmi na ĩnana kũraiha, na mĩkono ikũmi na ĩĩrĩ gũthiũrũrũka; na o kĩmwe gĩacio kĩarĩ na ũtungu wa ciara inya, na kĩarĩ na irima gatagatĩ.
22 Ọ̀nà orí idẹ kan tó ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ní gíga, wọ́n sì fi èso pomegiranate ṣe ọ̀ṣọ́ sí i lára yíká. Ọ̀wọ́n kejì sì wà pẹ̀lú èso pomegiranate tí ó jọra.
Kĩongo gĩa gĩcango kĩrĩa kĩarĩ hau gĩtugĩ-igũrũ, o kĩmwe kĩarĩ kĩa mĩkono ĩtano kũraiha, na gĩkagemio na rũgara rũrĩ na makomamanga ma gĩcango gũthiũrũrũkĩria. Gĩtugĩ kĩu kĩngĩ gĩa keerĩ, kĩrĩ na makomamanga makĩo nĩkĩahaanaine biũ na kĩu kĩngĩ kĩa mbere.
23 Pomegiranate mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn-ún ni ó wà ní àwọn ẹ̀gbẹ́ rẹ̀. Àpapọ̀ gbogbo pomegiranate sì jẹ́ ọgọ́rùn-ún kan.
Na haarĩ na makomamanga mĩrongo kenda na matandatũ maacuuhĩte mĩena-inĩ; makomamanga mothe marĩa maathiũrũrũkĩirie igũrũ wa magemio macio ma rũgara maarĩ igana rĩmwe.
24 Balógun àwọn ẹ̀ṣọ́ mu Seraiah olórí àwọn àlùfáà àti Sefaniah àlùfáà kejì àti àwọn olùṣọ́ ìloro mẹ́ta.
Mũnene ũcio wa arangĩri nĩanyiitire Seraia mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene, na Zefania mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa wa keerĩ harĩ we, o na andũ arĩa atatũ maarangagĩra mũrango.
25 Nínú àwọn tí ó kù ní ilẹ̀ náà, ó mú ìwẹ̀fà kan, tí ó wà ní ìtọ́jú àwọn ológun, àti àwọn olùdámọ̀ràn ọba méje. Bákan náà, ó tún mu akọ̀wé olórí ogun tí ó wà ní ìtọ́jú títo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti ọgọ́ta nínú àwọn ọkùnrin rẹ̀ tí wọ́n rí ní ìlú náà.
Harĩ andũ arĩa maatigaire kũu itũũra-inĩ inene, akĩnyiita mũnene ũrĩa warũgamĩrĩire andũ a mbaara, na akĩnyiita andũ mũgwanja arĩa maataaraga mũthamaki. Ningĩ akĩnyiita karani ũrĩa mũnene, ũrĩa wandĩkithagia andũ a gũthiĩ ita a bũrũri ũcio, na andũ ake mĩrongo ĩtandatũ arĩa maakorirwo itũũra-inĩ rĩu inene.
26 Nebusaradani, balógun ìṣọ́ kó gbogbo wọn, ó sì mú wọn tọ ọba Babeli wá ní Ribla.
Nebuzaradani ũcio mũnene wa arangĩri akĩmakuua othe, akĩmatwarĩra mũthamaki wa Babuloni kũu Ribila.
27 Ọba Babeli sì kọlù wọ́n, ó sì pa wọ́n ní Ribla ni ilẹ̀ Hamati. Báyìí ni a mú Juda kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.
Kũu Ribila, bũrũri-inĩ wa Hamathu, nĩkuo mũthamaki ũcio wa Babuloni aamoragithĩirie. Nĩ ũndũ ũcio andũ a Juda magĩtahwo, magĩtwarwo bũrũri ũngĩ, makĩrutwo bũrũri wao.
28 Èyí ni iye àwọn ènìyàn tí Nebukadnessari kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì. Ní ọdún keje ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó lé mẹ́tàlélógún ará Juda.
Ũyũ nĩguo mũigana wa andũ arĩa Nebukadinezaru aatahire akĩmatwara bũrũri ũngĩ: mwaka-inĩ wa mũgwanja aatahire Ayahudi 3,023;
29 Ní ọdún kejìdínlógún Nebukadnessari o kó ẹgbẹ̀rin ó lé méjìlélọ́gbọ̀n láti Jerusalẹmu.
naguo mwaka wa ikũmi na ĩnana wa ũthamaki wa Nebukadinezaru, agĩtaha andũ 832 kuuma Jerusalemu;
30 Ní ọdún kẹtàlélógún àwọn Júù tí Nebusaradani kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín márùn-ún. Gbogbo ènìyàn tí ó kó lápapọ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀tàlélógún.
o naguo mwaka-inĩ wake wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtatũ, agĩtaha Ayahudi 745 magĩtwarwo bũrũri ũngĩ nĩ Nebuzaradani ũcio mwathi wa arangĩri a mũthamaki. Andũ acio othe maarĩ 4,600.
31 Ní ọdún kẹtàdínlógójì ti Jehoiakini ọba Juda ni Efili-Merodaki di ọba Babeli. Ó gbé orí Jehoiakini ọba Juda sókè, ó sì tú sílẹ̀ nínú túbú ní ọjọ́ kẹẹdọ́gbọ̀n oṣù kejìlá.
Na gũgĩkinya atĩrĩ, mwaka-inĩ wa mĩrongo ĩtatũ na mũgwanja kuuma rĩrĩa Jekonia, mũthamaki wa Juda, aatwarirwo bũrũri ũngĩ, mwaka-inĩ ũrĩa Evili-Merodaki aatuĩkire mũthamaki wa Babuloni-rĩ, nĩohorithirie Jekonia mũthamaki wa Juda, akĩmũrekereria oime njeera mũthenya wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtano wa mweri wa ikũmi na ĩĩrĩ.
32 Ó ń sọ̀rọ̀ rere fún un, ó sì gbé ìtẹ́ rẹ̀ ga ju ìtẹ́ àwọn ọba tókù lọ tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ ní Babeli.
Nĩamwarĩirie na ũhooreri, na akĩmũhe gĩtĩ gĩa kũmũtũgĩria gũkĩra athamaki acio angĩ maarĩ nao kũu Babuloni.
33 Nítorí náà, Jehoiakini pàrọ̀ aṣọ túbú rẹ̀, ó sì ń jẹun ní gbogbo ìgbà ní iwájú rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Jekonia akĩruta nguo ciake cia njeera, na agĩtũũra arĩĩanagĩra irio na mũthamaki matukũ mothe marĩa aatũũrire muoyo.
34 Ní ojoojúmọ́ ni ọba Babeli ń fún Jehoiakini ní ìpín tirẹ̀ bí ó tí ń bẹ láààyè, títí di ọjọ́ kú rẹ̀.
Mũthamaki ũcio wa Babuloni nĩaheaga Jekonia indo cia kũmũteithia o mũthenya matukũ mothe marĩa aatũũrire muoyo, nginya mũthenya ũrĩa aakuire.

< Jeremiah 52 >