< Jeremiah 51 >
1 Ohùn ti Olúwa wí nìyìí: “Wò ó èmi yóò ru afẹ́fẹ́ apanirun sókè sí Babeli àti àwọn ènìyàn Lebikamai,
Аша ворбеште Домнул: „Ятэ, ридик ымпотрива Бабилонулуй ши ымпотрива локуиторилор Халдеей ун вынт нимичитор.
2 Èmi yóò rán àwọn àjèjì ènìyàn sí Babeli láti fẹ́ ẹ, tí yóò sì sọ ilẹ̀ rẹ̀ di òfo; wọn yóò takò ó ní gbogbo ọ̀nà ní ọjọ́ ìparun rẹ̀.
Тримит ымпотрива Бабилонулуй ниште вынтурэторь каре-л вор вынтура ши-й вор голи цара. Вор вени дин тоате пэрциле асупра луй ын зиуа ненорочирий.
3 Má ṣe jẹ́ kí tafàtafà yọ ọfà rẹ̀, jáde tàbí kí ó di ìhámọ́ra rẹ̀. Má ṣe dá àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin sí; pátápátá ni kí o pa àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.
Сэ се ынтиндэ аркул ымпотрива челуй че ышь ынтинде аркул, ымпотрива челуй че се мындреште ын платоша луй! Ну круцаць пе тинерий луй! Нимичиць ку десэвыршире тоатэ оштиря луй!
4 Gbogbo wọn ni yóò ṣubú ní Babeli, tí wọn yóò sì fi ara pa yánnayànna ní òpópónà.
Сэ кадэ учишь ын цара халдеенилор, стрэпуншь де ловитурь пе улицеле Бабилонулуй!
5 Nítorí pé Juda àti Israẹli ni Ọlọ́run wọn tí í ṣe Olúwa àwọn ọmọ-ogun, kò gbàgbọ́ bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ilé wọn kún fún kìkì ẹ̀bi níwájú ẹni mímọ́ Israẹli.
Кэч Исраелул ши Иуда ну сунт пэрэсиць де Думнезеул лор, де Домнул оштирилор, ши цара халдеенилор есте плинэ де нелеӂюирь ымпотрива Сфынтулуй луй Исраел.”
6 “Sá kúrò ní Babeli! Sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ! Má ṣe ṣègbé torí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ. Àsìkò àti gbẹ̀san Olúwa ni èyí; yóò sán fún òun gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́.
Фуӂиць дин Бабилон ши фиекаре сэ-шь скапе вяца, ка ну кумва сэ периць ын пеиря луй! Кэч ачаста есте о време де рэзбунаре пентру Домнул! Ел ый ва рэсплэти дупэ фаптеле луй.
7 Ife wúrà ni Babeli ní ọwọ́ Olúwa; ó sọ gbogbo ayé di ọ̀mùtí. Gbogbo orílẹ̀-èdè mu ọtí rẹ̀, wọ́n sì ti ya òmùgọ̀ kalẹ̀.
Бабилонул ера ын мына Домнулуй ун потир де аур, каре ымбэта тот пэмынтул; нямуриле ау бэут дин винул луй, де ачея ау фост нямуриле ка ынтр-о небуние.
8 Babeli yóò ṣubú lójijì, yóò sì fọ́. Ẹ hu fun un! Ẹ mú ìkunra fún ìrora rẹ, bóyá yóò le wo ọ́ sàn.
Деодатэ каде Бабилонул ши есте здробит! Вэитаци-л, адучець ляк алинэтор пентру рана луй; поате кэ се ва виндека! –
9 “‘À bá ti wo Babeli sàn, ṣùgbọ́n kò lè sàn, ẹ jẹ́ kí a fi sílẹ̀, kí oníkálùkù lọ sí ilẹ̀ rẹ̀ torí ìdájọ́ rẹ̀ tó gòkè, ó ga àní títí dé òfúrufú.’
Ам воит сэ виндекэм Бабилонул, дар ну с-а виндекат! Пэрэсици-л ши хайдем фиекаре ын цара ноастрэ, кэч педяпса луй а ажунс пынэ ла черурь ши се ыналцэ пынэ ла норь. –
10 “‘Olúwa ti dá wa láre, wá jẹ́ kí a sọ ọ́ ní Sioni ohun tí Olúwa Ọlọ́run wa ti ṣe.’
Домнул скоате ла луминэ дрептатя причиний ноастре: вениць сэ историсим ын Сион лукраря Домнулуй Думнезеулуй ностру.
11 “Ṣe ọfà rẹ ní mímú, mú àpáta! Olúwa ti ru ọba Media sókè, nítorí pé ète rẹ̀ ni láti pa Babeli run. Olúwa yóò gbẹ̀san, àní ẹ̀san fún tẹmpili rẹ̀.
Аскуциць сэӂециле, приндець скутуриле! Домнул а ацыцат духул ымпэрацилор Медией, пентру кэ вря сэ нимичяскэ Бабилонул, кэч ачаста есте рэзбунаря Домнулуй, рэзбунаря пентру Темплул Сэу.
12 Gbé àsíá sókè sí odi Babeli! Ẹ ṣe àwọn ọmọ-ogun gírí, ẹ pín àwọn olùṣọ́ káàkiri, ẹ ṣètò àwọn tí yóò sá pamọ́ Olúwa! Yóò gbé ète rẹ̀ jáde, òfin rẹ̀ sí àwọn ará Babeli.
Ынэлцаць ун стяг ымпотрива зидурилор Бабилонулуй! Ынтэрици-й стрэжиле, пунець карауле, ынтиндець курсе! Кэч Домнул а луат о хотэрыре ши адуче ла ындеплинире че а ростит ымпотрива локуиторилор Бабилонулуй.
13 Ìwọ tí o gbé lẹ́bàá odò púpọ̀, tí o sì ni ọ̀rọ̀ púpọ̀; ìgbẹ̀yìn rẹ ti dé, àní àsìkò láti ké ọ kúrò!
Цие, каре локуешть лынгэ апе марь ши каре ай вистиерий немэрӂините, ць-а венит сфыршитул, ши лэкомия та а ажунс ла капэт!
14 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra fún ara rẹ̀, Èmi yóò fún ọ ní ènìyàn gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ eṣú, wọn yóò yọ ayọ̀, ìṣẹ́gun lórí rẹ.
Домнул оштирилор а журат пе Сине Ынсушь: „Да, те вой умпле де оамень ка де ниште лэкусте ши вор скоате стригэте де рэзбой ымпотрива та.”
15 “Ó dá ilẹ̀ nípa agbára rẹ̀, o dá ilẹ̀ ayé pẹ̀lú ọgbọ́n rẹ̀, o sì tẹ́ ọ̀run pẹ̀lú ìmọ̀ rẹ̀.
Ел а фэкут пэмынтул ку путеря Луй, а ынтемеят лумя ку ынцелепчуня Луй, а ынтинс черуриле ку причеперя Луй.
16 Nígbà tí ará omi ọ̀run hó ó mú kí òfúrufú ru sókè láti ìpẹ̀kun ayé. Ó rán mọ̀nàmọ́ná pẹ̀lú òjò, ó sì mú afẹ́fẹ́ jáde láti ilé ìṣúra rẹ̀.
Де гласул Луй, урлэ апеле ын черурь; Ел ридикэ норий де ла марӂиниле пэмынтулуй, дэ наштере ла фулӂере ши плоае ши скоате вынтул дин кэмэриле луй.
17 “Olúkúlùkù ènìyàn ni kò lọ́pọlọ tí kò sì ní ìmọ̀, olúkúlùkù alágbẹ̀dẹ ni a kó ìtìjú bá nípa òrìṣà rẹ̀. Àwọn ère rẹ jẹ́ ẹ̀tàn; wọn kò ní èémí nínú.
Атунч, орьче ом се веде кыт есте де прост ку штиинца луй, орьче арӂинтар рэмыне рушинат де кипуриле луй чоплите, кэч идолий луй ну сунт декыт минчунэ ши н-ау ничо суфларе ын ей!
18 Asán ni wọ́n, àti iṣẹ́ ìsìnà, nígbà ìbẹ̀wò wọn, wọn ó ṣègbé.
Сунт о нимика тоатэ ши о лукраре де рыс: кынд ле вине педяпса, пер ку десэвыршире!
19 Ẹni tí ó jẹ́ ìpín Jakọbu kó rí bí ìwọ̀nyí; nítorí òun ni ó dá ohun gbogbo, àti gbogbo àwọn ẹ̀yà ajogún, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
Дар Чел че есте партя луй Иаков ну есте ка ей, кэч Ел а ынтокмит тотул, ши Исраел есте семинция моштенирий Луй: Домнул оштирилор есте Нумеле Луй.
20 “Ìwọ ni kùmọ̀ ogun ohun èlò ogun mi, ohun èlò ìjà mi, pẹ̀lú rẹ èmi ó fọ́ orílẹ̀-èdè túútúú, èmi ó bà àwọn ilé ọba jẹ́.
„Ту Мь-ай фост ун чокан ши о унялтэ де рэзбой. Ам здробит нямурь прин тине, ам нимичит ымпэрэций прин тине.
21 Pẹ̀lú rẹ, èmi ó pa ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún pẹ̀lú rẹ̀; èmi ó ba kẹ̀kẹ́ ogun jẹ́ pẹ̀lú èmi ó pa awakọ̀,
Прин тине ам сфэрымат пе кал ши пе кэлэрецул луй;
22 pẹ̀lú rẹ, mo pa ọkùnrin àti obìnrin, pẹ̀lú rẹ, mo pa àgbàlagbà àti ọmọdé, pẹ̀lú rẹ, mo pa ọ̀dọ́mọkùnrin àti ọ̀dọ́mọbìnrin.
прин тине ам сфэрымат карул ши пе чел че шедя ын ел. Прин тине ам сфэрымат пе бэрбат ши пе фемее; прин тине ам сфэрымат пе бэтрын ши пе копил; прин тине ам сфэрымат пе тынэр ши пе фатэ.
23 Èmi yóò sì fi ọ́ fọ́ olùṣọ́-àgùntàn, àti agbo àgùntàn rẹ̀ túútúú, èmi yóò sì fi ọ́ fọ́ àgbẹ̀ àti àjàgà màlúù túútúú, èmi yóò sì fi ọ́ fọ́ baálẹ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀ túútúú.
Прин тине ам сфэрымат пе пэстор ши турма луй; прин тине ам сфэрымат пе плугар ши боий луй; прин тине ам сфэрымат пе кырмуиторь ши пе кэпетенииле луй.
24 “Ní ojú rẹ, èmi yóò san án fún Babeli àti gbogbo àwọn olùgbé inú rẹ̀ fún gbogbo ibi tí wọ́n ti ṣe ní Sioni,” ni Olúwa wí.
Дар акум, вой рэсплэти Бабилонулуй ши тутурор локуиторилор Халдеей тот рэул пе каре л-ау фэкут Сионулуй суб окий воштри”, зиче Домнул.
25 “Mo lòdì sí ọ, ìwọ òkè apanirun ìwọ ti ba gbogbo ayé jẹ́,” ni Olúwa wí. “Èmi ó na ọwọ́ mi sí ọ, èmi yóò yí ọ kúrò lórí àpáta, Èmi yóò sọ ọ́ dàbí òkè tí a ti jó.
„Ятэ, ам неказ пе тине, мунте нимичитор”, зиче Домнул, „пе тине, каре нимичяй тот пэмынтул! Ымь вой ынтинде мына песте тине, те вой прэвэли де ла ынэлцимя стынчилор ши те вой префаче ынтр-ун мунте апринс.
26 A kò ní mú òkúta kankan láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ lò gẹ́gẹ́ bí igun ilé tàbí fún ìpínlẹ̀ nítorí pé ìwọ yóò di ahoro títí ayé,” ní Olúwa wí.
Ну се вор май скоате дин тине нич петре дин капул унгюлуй клэдирий, нич петре пентру темелий, кэч вей фи о дэрымэтурэ вешникэ”, зиче Домнул…
27 “Gbé àsíá sókè ní ilẹ̀ náà! Fọn ìpè láàrín àwọn orílẹ̀-èdè! Sọ àwọn orílẹ̀-èdè di mímọ́ sórí rẹ̀, pe àwọn ìjọba yìí láti dojúkọ ọ́: Ararati, Minini àti Aṣkenasi. Yan olùdarí ogun láti kọlù ú, rán àwọn ẹṣin sí i bí ọ̀pọ̀ eṣú.
Ынэлцаць ун стяг пе пэмынт! Сунаць дин трымбицэ принтре нямурь! Прегэтиць нямуриле ымпотрива луй, кемаць ымпотрива луй ымпэрэцииле Араратулуй, Миниулуй ши Ашкеназулуй! Пунець кэпетений де оасте ымпотрива луй! Фачець сэ ынаинтезе каий ка ниште лэкусте збырлите!
28 Sọ àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀lú àwọn ọba Media di mímọ́ sórí rẹ̀, àwọn baálẹ̀ rẹ̀, àti gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀, àti gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọ́n jẹ ọba lé lórí.
Прегэтиць ымпотрива луй пе нямурь, пе ымпэраций Медией, пе кырмуиторий луй ши пе тоате кэпетенииле луй ши тоатэ цара де суб стэпыниря лор!
29 Ilẹ̀ wárìrì síyìn-ín sọ́hùn-ún, nítorí pé ète Olúwa, sí Babeli dúró, láti ba ilẹ̀ Babeli jẹ́ lọ́nà tí ẹnikẹ́ni kò ní lè gbé inú rẹ̀ mọ́.
Се клатинэ пэмынтул, се кутремурэ, кэч планул Домнулуй ымпотрива Бабилонулуй се ымплинеште ши Ел ва фаче дин цара Бабилонулуй ун пустиу нелокуит.
30 Gbogbo àwọn jagunjagun Babeli tó dáwọ́ ìjà dúró sínú àgọ́ wọn. Agbára wọn ti tán, wọ́n ti dàbí obìnrin. Ibùgbé rẹ̀ ni a ti dáná sun, gbogbo irin ẹnu-ọ̀nà wọn ti di fífọ́.
Витежий Бабилонулуй ну май луптэ, чи стау ын четэцуй; путеря ле есте слеитэ ши ау ажунс ка ниште фемей. Врэжмаший пун фок локуинцелор лор ши ле сфэрымэ зэвоареле!
31 Ìránṣẹ́ kan ń tẹ̀lé òmíràn láti sọ fún ọba Babeli pé gbogbo ìlú rẹ̀ ni a ti kó ní ìgbèkùn.
Се ынтылнеск алергэторий, се ынкручишязэ солий ка сэ вестяскэ ымпэратулуй Бабилонулуй кэ четатя луй есте луатэ дин тоате пэрциле,
32 Odò tí ó sàn kọjá kò sàn mọ́ ilẹ̀ àbàtà gbiná, àwọn jagunjagun sì wárìrì.”
кэ трекэториле сунт луате, бэлциле ку трестие сунт ускате де фок ши оамений де рэзбой, ынгрозиць.
33 Ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli sọ nìyìí: “Ọmọbìnrin Babeli dàbí ìpakà àsìkò láti kórè rẹ̀ kò ní pẹ́ dé mọ́.”
Кэч аша ворбеште Домнул оштирилор, Думнезеул луй Исраел: „Фийка Бабилонулуй есте ка о арие пе время кынд есте кэлкатэ ку пичоареле: ынкэ о клипэ, ши ва вени пентру еа время сечеришулуй.”
34 “Nebukadnessari ọba Babeli tó jẹ wá run, ó ti mú kí ìdààmú bá wa, ó ti sọ wá di àgbá òfìfo. Gẹ́gẹ́ bí ejò, ó ti gbé wa mì. Ó fi oúnjẹ àdídùn wa kún inú rẹ̀, lẹ́yìn náà ni ó pọ̀ wá jáde.
„Небукаднецар, ымпэратул Бабилонулуй, м-а мынкат, м-а нимичит; м-а фэкут ка ун вас гол; м-а ынгицит ка ун балаур, шь-а умплут пынтечеле ку че авям май скумп ши м-а изгонит.
35 Kí gbogbo ìparun tí ó ṣe sí ẹran-ara wa wà lórí Babeli,” èyí tí àwọn ibùgbé Sioni wí. “Kí ẹ̀jẹ̀ wa wà lórí gbogbo àwọn tí ń gbé Babeli,” ni Jerusalẹmu wí.
Силничия фэкутэ фацэ де мине ши фацэ де карня мя сфышиятэ сэ се ынтоаркэ асупра Бабилонулуй”, зиче локуитоаря Сионулуй. „Сынӂеле меу сэ кадэ асупра локуиторилор Халдеей”, зиче Иерусалимул.
36 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí: “Wò ó, èmi yóò tì ọ́ lẹ́yìn lórí ohun tí o fẹ́ ṣe. Èmi ó sì gbẹ̀san, èmi yóò mú kí omi Òkun rẹ̀ àti orísun omi rẹ̀ gbẹ.
Де ачея, аша ворбеште Домнул: „Ятэ, ыць вой апэра причина ши те вой рэзбуна! Вой сека маря Бабилонулуй ши-й вой уска изворул.
37 Babeli yóò parun pátápátá, yóò sì di ihò àwọn akátá, ohun ẹ̀rù àti àbùkù, ibi tí ènìyàn kò gbé.
Бабилонул ва ажунӂе ун морман де дэрымэтурь, о визуинэ де шакаль, ун пустиу ши о батжокурэ ши ну ва май авя локуиторь.
38 Àwọn ènìyàn inú rẹ̀ bú ramúramù bí ọmọ kìnnìún.
Вор рэкни ымпреунэ ка ниште лей, вор ципа ка ниште пуй де лей.
39 Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkàn wọn bá ru sókè, èmi yóò ṣe àsè fún wọn, èmi yóò jẹ́ kí wọn mutí yó tí wọn yóò máa kọ fun ẹ̀rín, lẹ́yìn náà, wọn yóò sun oorun, wọn kì yóò jí,” ni Olúwa wí.
Кынд вор фи ынкэлзиць де вин, ле вой да сэ бя ши-й вой ымбэта, ка сэ се веселяскэ ши апой сэ адоармэ сомнул чел де вечь, ка сэ ну се май скоале”, зиче Домнул.
40 “Èmi yóò fà wọ́n lọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́-àgùntàn tí a fẹ́ pa, gẹ́gẹ́ bí àgbò àti ewúrẹ́.
„Ый вой коборы ка пе ниште мей ла тэере, ка пе ниште бербечь ши ниште цапь.
41 “Báwo ni Ṣeṣaki yóò ṣe dí mímú, ìfọ́nnu gbogbo àgbáyé. Irú ìpayà wo ni yóò bá Babeli láàrín àwọn orílẹ̀-èdè!
Кум с-а луат Шешакул! Кум а фост кучерит ачела а кэруй славэ умпля тот пэмынтул! Кум а фост нимичит Бабилонул дин мижлокул нямурилор!
42 Òkun yóò ru borí Babeli, gbogbo rírú rẹ̀ yóò borí Babeli.
Маря с-а ынэлцат песте Бабилон; Бабилонул а фост акоперит де мулцимя валурилор сале.
43 Àwọn ìlú rẹ̀ yóò di ahoro, ilẹ̀ tí ó gbẹ, ilẹ̀ tí ènìyàn kò gbé tí ènìyàn kò sì rin ìrìnàjò.
Четэциле луй ау ажунс ун пустиу; ун пэмынт фэрэ апэ ши пустиу, о царэ унде нимень ну локуеште ши пе унде ничун ом ну трече.
44 Èmi yóò fi ìyà jẹ Beli ti Babeli àti pé èmi yóò jẹ́ kí ó pọ gbogbo àwọn ohun tí ó gbé mì. Àwọn orílẹ̀-èdè kì yóò jùmọ̀ sàn lọ pọ̀ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ mọ́. Ní òótọ́ odi Babeli yóò sì wó.
Вой педепси пе Бел ын Бабилон, ый вой смулӂе дин гурэ че а ынгицит, ши нямуриле ну се вор май ынгрэмэди ын ел: кяр ши зидул Бабилонулуй ва кэдя!
45 “Ẹ jáde kúrò nínú rẹ̀ ẹ̀yin ènìyàn mi! Sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ! Sá fún ìbínú ńlá Olúwa.
Ешиць дин мижлокул луй, попорул Меу, ши фиекаре сэ-шь скапе вяца, скэпынд де мыния апринсэ а Домнулуй!
46 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ dàrú tàbí kí o bẹ̀rù nígbà tí a bá gbọ́ àhesọ ọ̀rọ̀ ní ilẹ̀ wa; àhesọ ọ̀rọ̀ kan wá ní ọdún yìí, òmíràn ní ọdún mìíràn àhesọ ọ̀rọ̀ ni ti ìwà ipá ní ilẹ̀ náà àti tí aláṣẹ kan sí aláṣẹ kejì.
Сэ ну ви се тулбуре инима ши ну вэ ынспэймынтаць де звонуриле каре се рэспындеск ын царэ, кэч анул ачеста ва вени ун звон, яр анул урмэтор, ун алт звон; ын царэ ва домни силничия ши ун стэпынитор се ва ридика ымпотрива алтуй стэпынитор.
47 Nítorí ìgbà náà yóò wá dandan nígbà tí èmi yóò fi ìyà jẹ àwọn òrìṣà Babeli; gbogbo ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó dójútì gbogbo àwọn tí a pa yóò sì ṣubú ní àárín rẹ̀.
Де ачея, ятэ, вин зиле кынд вой педепси идолий Бабилонулуй. Атунч тоатэ цара луй ва фи акоперитэ де рушине ши тоць морций луй вор кэдя ын мижлокул луй.
48 Ọ̀run àti ayé àti gbogbo ohun tí ó wà nínú wọn, yóò sì kọrin lórí Babeli: nítorí àwọn afiniṣèjẹ yóò wá sórí rẹ̀ láti àríwá,” ni Olúwa wí.
Черуриле ши пэмынтул, ку тот че купринд еле, вор стрига де букурие асупра Бабилонулуй, кэч пустииторий се вор арунка де ла мязэноапте асупра луй”, зиче Домнул.
49 “Babiloni gbọdọ̀ ṣubú nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni Israẹli, gẹ́gẹ́ bí àwọn ti a pa ní gbogbo ayé nítorí Babeli.
Кяр ши Бабилонул ва кэдя, о, морць ай луй Исраел, кум а фэкут ши ел сэ кадэ морций дин тоатэ цара.
50 Ẹ̀yin tí ó ti bọ́ lọ́wọ́ idà, ẹ lọ, ẹ má dúró. Ẹ rántí Olúwa ní òkèrè, ẹ sì jẹ́ kí Jerusalẹmu wá sí ọkàn yín.”
Чей каре аць скэпат де сабие, плекаць, ну зэбовиць! Чей дин пэмынтул депэртат, гындици-вэ ла Домнул, ши Иерусалимул сэ фие ын инимиле воастре!
51 “Ojú tì wá, nítorí pé àwa ti gbọ́ ẹ̀gàn: ìtìjú ti bò wá lójú nítorí àwọn àjèjì wá sórí ohun mímọ́ ilé Olúwa.”
Не рушинам кынд аузям окара; не аскундям фецеле де рушине кынд ау венит ниште стрэинь ын Сфынтул Локаш ал Касей Домнулуй.
52 “Nítorí náà, wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí èmi yóò ṣe ìbẹ̀wò lórí àwọn ère fínfín rẹ̀, àti àwọn tí ó gbọgbẹ́ yóò sì máa kérora já gbogbo ilẹ̀ rẹ̀.
„Де ачея, ятэ, вин зиле”, зиче Домнул, „кынд ый вой педепси идолий, ши ын тоатэ цара луй вор ӂеме рэниций.
53 Bí Babeli tilẹ̀ gòkè lọ sí ọ̀run, bí ó sì ṣe ìlú olódi ní òkè agbára rẹ, síbẹ̀ àwọn afiniṣèjẹ yóò ti ọ̀dọ̀ mi tọ̀ ọ́ wá,” ní Olúwa wí.
Кяр дакэ Бабилонул с-ар ынэлца пынэ ла черурь, кяр дакэ ар фаче ку непутинцэ де ажунс четэцуиле луй челе ыналте, тот вой тримите пе пустииторь ымпотрива луй”, зиче Домнул…
54 “Ìró igbe láti Babeli, àti ìparun láti ilẹ̀ àwọn ará Kaldea!
Рэсунэ стригэте дин Бабилон ши ун маре прэпэд ын цара халдеенилор.
55 Nítorí pé Olúwa ti ṣe Babeli ní ìjẹ, ó sì ti pa ohun ńlá run kúrò nínú rẹ̀; àwọn ọ̀tá wọn sì ń hó bi omi púpọ̀, a gbọ́ ariwo ohùn wọn.
Кэч Домнул пустиеште Бабилонул ши фаче сэ-й ынчетезе зарва чя маре. Валуриле пустииторилор урлэ ка ниште апе марь, ал кэрор вует тулбурат се ауде.
56 Nítorí pé afiniṣèjẹ dé sórí rẹ̀, àní sórí Babeli; a mú àwọn akọni rẹ̀, a ṣẹ́ gbogbo ọrun wọn: nítorí Ọlọ́run ẹ̀san ni Olúwa, yóò san án nítòótọ́.
Да, пустииторул се арункэ асупра луй, асупра Бабилонулуй; витежий Бабилонулуй сунт приншь ши ли се сфэрымэ аркуриле. Кэч Домнул есте ун Думнезеу каре рэсплэтеште! Ел ва да негрешит фиекэруя плата кувенитэ луй!
57 Èmi ó sì mú kí àwọn ìjòyè rẹ̀ yó bí ọ̀mùtí, àti àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀ àti àwọn baálẹ̀ rẹ̀, àti àwọn akọni rẹ̀, wọn ó sì sun oorun láéláé, wọn kì ó sì jí mọ́,” ní ọba wí, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
„Ши ануме, вой ымбэта пе воевозий ши ынцелепций луй, пе кырмуиторий, пе кэпетенииле ши витежий луй; вор адорми сомнул чел де вечь ши ну се вор май трези”, зиче Ымпэратул, ал кэруй Нуме есте Домнул оштирилор.
58 Báyìí ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Odi Babeli gbígbòòrò ní a ó wó lulẹ̀ pátápátá, ẹnu-bodè gíga rẹ̀ ní a ó sì fi iná sun: tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ènìyàn ti ṣiṣẹ́ lásán, àti àwọn orílẹ̀-èdè ti ṣiṣẹ́ fún iná, tí àárẹ̀ sì mú wọn.”
Аша ворбеште Домнул оштирилор: „Зидуриле челе ларӂь але Бабилонулуй вор фи сурпате ши порциле луй челе ыналте вор фи арсе ку фок. Астфел, попоареле мунческ деӂяба ши нямуриле се трудеск пентру фок!”
59 Ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì pàṣẹ fún Seraiah, ọmọ Neriah, ọmọ Maseiah, nígbà tí o ń lọ ni ti Sedekiah, ọba Juda, sí Babeli ní ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀. Seraiah yìí sì ní ìjòyè ibùdó.
Ятэ порунка датэ де пророкул Иеремия луй Серая, фиул луй Нерия, фиул луй Махсея, кынд с-а дус ла Бабилон ку Зедекия, ымпэратул луй Иуда, ын ал патруля ан ал домнией луй Зедекия. Серая ера чел май маре кэмэраш.
60 Jeremiah sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ ibi tí yóò wá sórí Babeli sínú ìwé kan, àní gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tí a kọ sí Babeli.
Иеремия а скрис ынтр-о карте тоате ненорочириле каре авяу сэ винэ асупра Бабилонулуй, тоате кувинтеле ачестя скрисе асупра Бабилонулуй.
61 Jeremiah sì sọ fún Seraiah pé, “Nígbà tí ìwọ bá dé Babeli, kí ìwọ kí ó sì wò, kí ìwọ kí ó sì ka gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.
Иеремия а зис луй Серая: „Кынд вей ажунӂе ла Бабилон, везь сэ читешть тоате кувинтеле ачестя
62 Kí ìwọ kí ó sì wí pé, ‘Olúwa ìwọ ti sọ̀rọ̀ sí ibí yí, láti ké e kúrò, kí ẹnikẹ́ni má ṣe gbé inú rẹ̀, àti ènìyàn àti ẹran, nítorí pé yóò di ahoro láéláé.’
ши сэ зичь: ‘Доамне, Ту ай спус кэ локул ачеста аре сэ фие нимичит ши кэ н-аре сэ май фие локуит нич де оамень, нич де добитоаче, чи аре сэ ажунгэ ун пустиу пентру тотдяуна.’
63 Yóò sì ṣe, nígbà tí ìwọ bá parí kíka ìwé yìí tán kí ìwọ kí ó di òkúta mọ́ ọn, kí ó sì sọ ọ́ sí àárín odò Eufurate.
Ши кынд вей испрэви читиря кэрций ачестея, сэ леӂь де еа о пятрэ ши с-о арунчь ын Еуфрат
64 Kí ìwọ sì wí pé, ‘Báyìí ní Babeli yóò rì, kí yóò sì tún dìde kúrò nínú ibi tí èmi ó mú wá sórí rẹ̀: àárẹ̀ yóò sì mú wọn.’” Títí dé ìhín ni ọ̀rọ̀ Jeremiah.
ши сэ зичь: ‘Аша ва фи ынекат Бабилонул ши ну се ва май ридика дин ненорочириле пе каре ле вой адуче асупра луй; вор кэдя слеиць де путерь!’” Пынэ аич сунт кувинтеле луй Иеремия.