< Jeremiah 50 >

1 Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa fi sẹ́nu wòlíì Jeremiah láti sọ fún ará ilẹ̀ Babeli:
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ĩrĩa Jehova aaririe na kanua ka Jeremia ũcio mũnabii, ũhoro ũkoniĩ Babuloni na andũ a bũrũri wa Babuloni:
2 “Ẹ sọ ọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ sì kéde, kí ẹ sì gbé àsíá sókè, ẹ kéde rẹ̀ ẹ má sì ṣe bò ó, wí pé, ‘A kó Babeli, ojú tí Beli, a fọ́ Merodaki túútúú, ojú ti àwọn ère rẹ̀, a fọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀ túútúú.’
“Anĩrĩrai na mũhunjanĩrie ũhoro ndũrĩrĩ-inĩ, haandai kĩbebero na mũhunjanĩrie ũhoro wakĩo; mũtikamahithe ũndũ, no mũmeere atĩrĩ, ‘Babuloni nĩgũgũtunyanwo; Beli nĩĩgũconorithio, nayo Merodaki ĩiyũrwo nĩ kĩmako. Mĩhianano yakuo nĩĩgaconorithio, na mĩhianano yao nĩĩkaiyũrwo nĩ guoya.’
3 Àwọn ìlú ní apá àríwá yóò sì máa gbóguntì wọ́n. Gbogbo àwọn ènìyàn àti ẹranko ni yóò sá kúrò ní ìlú yìí.
Tondũ rũrĩrĩ ruumĩte mwena wa gathigathini nĩrũkamũtharĩkĩra, na rwanange bũrũri wake. Gũtirĩ mũndũ ũgaatũũra kuo; andũ nĩmakoora o hamwe na nyamũ.
4 “Ní ọjọ́ wọ̀nyí àti ní àkókò náà,” ni Olúwa wí, “Àwọn ọmọ Israẹli yóò jùmọ̀ wá, àwọn, àti àwọn ọmọ Juda, wọn yóò lọ pẹ̀lú ẹkún láti ṣàfẹ́rí Olúwa Ọlọ́run wọn.
“Matukũ-inĩ macio, na ihinda-inĩ rĩu, andũ a Isiraeli na andũ a Juda hamwe nĩmagathiĩ macarie Jehova Ngai wao makĩrĩraga,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
5 Wọn ó máa béèrè ọ̀nà Sioni, ojú wọn yóò sì yí síhà ibẹ̀, wí pé ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a darapọ̀ mọ́ Olúwa ní májẹ̀mú ayérayé, tí a kì yóò gbàgbé.
“Nĩmakoorĩrĩria njĩra ya gũthiĩ Zayuni, na magarũrũke, merekeirie mothiũ mao kuo. Nĩmagooka meeohanie na Jehova, na marĩkanĩre kĩrĩkanĩro gĩa gũtũũra tene na tene kĩrĩa gĩtagacooka kũriganĩra.
6 “Àwọn ènìyàn mi ti jẹ́ àgùntàn tí ó sọnù, àwọn olùṣọ́-àgùntàn wọn ti jẹ́ kí wọn ṣìnà, wọ́n ti jẹ́ kí wọn rìn lórí òkè wọ́n ti lọ láti orí òkè ńlá dé òkè kékeré, wọn ti gbàgbé ibùsùn wọn.
“Andũ akwa makoretwo marĩ ngʼondu ciũrĩte; arĩithi ao nĩmamahĩtithĩtie njĩra, na magatũma morũũre irĩma igũrũ. Nao morũũrĩte kuuma kĩrĩma-inĩ nginya karĩma-inĩ, makariganĩrwo nĩ kũrĩa ũhurũko wao ũrĩ.
7 Gbogbo àwọn tí ó rí wọn, ti pa wọ́n jẹ àwọn ọ̀tá wọ́n sì wí pé, ‘Àwa kò jẹ̀bi nítorí pé wọ́n ti ṣẹ̀ sí Olúwa ibùgbé òdodo àti ìrètí àwọn baba wọn.’
Ũrĩa wothe wamoonire akĩmatambuura; thũ ciao ikiuga atĩrĩ, ‘Ithuĩ tũtirĩ na ihĩtia, nĩ ũndũ nĩmehĩirie Jehova, ũrĩa arĩ we ũrĩithio wao wa ma, o we Jehova, mwĩhoko wa maithe mao.’
8 “Jáde kúrò ní Babeli, ẹ fi ilẹ̀ àwọn ará Kaldea sílẹ̀, kí ẹ sì jẹ́ bí òbúkọ níwájú agbo ẹran.
“Mwĩtharei muume Babuloni; eherai bũrũri wa andũ a Babuloni, na mũtuĩke ta thenge iria itongoragia rũũru rwa mbũri.
9 Nítorí pé èmi yóò ru, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò gbé sókè sí Babeli àwọn orílẹ̀-èdè ńlá láti ilẹ̀ àríwá. Wọn yóò gba àyà wọn lẹ́gbẹ́ rẹ̀; láti àríwá wá, à ó sì mú ọ. Ọfà wọn yóò dàbí ọfà àwọn akọni akíkanjú tí wọn kì í wà lọ́wọ́ òfo.
Nĩgũkorwo nĩngarahũra ũiguano wa ndũrĩrĩ nene, ciumĩte bũrũri wa gathigathini ciũkĩrĩre Babuloni. Nĩikarũgama handũ ha cio irĩũkĩrĩre na igũtunyane, kuuma mwena ũcio wa gathigathini. Mĩguĩ yao ĩgaatuĩka ta ĩrĩa ya njamba njoorua, iria itacookaga moko matheri.
10 A ó dààmú Babeli, gbogbo àwọn tó dààmú rẹ yóò sì mú ìfẹ́ wọn ṣẹ,” ni Olúwa wí.
Nĩ ũndũ ũcio Babuloni nĩgũgatahwo; andũ othe arĩa magaagũtaha nĩmagakuua indo cia kũmaigana,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
11 “Nítorí pé inú yín dùn nítorí pé ẹ̀yìn yọ̀, ẹ̀yìn olè tí ó jí ìní mi, nítorí tí ẹ̀yìn fi ayọ̀ fò bí ẹgbọrọ abo màlúù sí koríko tútù, ẹ sì ń yan bí akọ ẹṣin.
“Tondũ nĩmũkenete na mũkarũũhia, inyuĩ arĩa mũtahaga igai rĩakwa, tondũ mũgũtũũha ta moori ĩkĩraanga ngano ĩkĩmĩhũũra, na mũkaania ta mbarathi cia njamba,
12 Ojú yóò ti ìyá rẹ, ẹni tí ó bí ọ yóò sì gba ìtìjú. Òun ni yóò jẹ́ kékeré jù nínú àwọn orílẹ̀-èdè, ilẹ̀ aṣálẹ̀ àti aginjù tí kò lọ́ràá.
nyina wanyu nĩagaconoka mũno; we ũcio wamũciarire nĩagaconorithio. Nĩwe ũgaakorwo arĩ mũnini mũno ndũrĩrĩ-inĩ, atuĩke ta werũ, na ta bũrũri mũngʼaru, o na ta werũ wa mũthanga.
13 Nítorí ìbínú Olúwa, kì yóò ní olùgbé; ẹnikẹ́ni kò sì ní gbé inú rẹ̀. Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá ni Babeli yóò fi ṣe yẹ̀yẹ́ nítorí ọgbẹ́ rẹ̀.
Tondũ wa marakara ma Jehova, bũrũri ũcio ndũgacooka gũtũũrwo nĩ andũ, no rĩrĩ, nĩgũkira gũgaakira ihooru biũ. Andũ arĩa othe makaagerera kũu Babuloni nĩmakamaka, na manyũrũrie kũndũ kũu tondũ wa ũrĩa gũgaakorwo kwanangĩtwo.
14 “Dúró sí ààyè rẹ ìwọ Babeli àti gbogbo ẹ̀yin tí ẹ n ta ọfà náà. Ẹ ta ọfà náà sí i, nítorí ó ti ṣẹ̀ sí Olúwa.
“Mwĩhaarĩrie mũthiũrũrũkĩrie Babuloni, inyuothe arĩa mũgeetaga ũta. Rĩrathei! Mũtigatigie mĩguĩ, nĩgũkorwo nĩrĩĩhĩirie Jehova.
15 Kígbe mọ́ ọn ní gbogbo ọ̀nà! Ó tẹríba, òpó rẹ̀ sì yẹ̀, níwọ̀n ìgbà tí ó ti jẹ́ wí pé èyí ni ìgbẹ̀san Olúwa, gbẹ̀san lára rẹ̀. Ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí àwọn ẹlòmíràn.
Riugĩrĩriei kuuma na mĩena yothe! Nĩrĩĩneanĩte rĩo rĩene, mĩthiringo yarĩo nĩĩgwĩte, na thingo ciarĩo nĩimomokete. Nĩgũkorwo rĩĩrĩ nĩrĩo irĩhĩria rĩa Jehova-rĩ, mwĩrĩhĩriei harĩ rĩo; rĩĩkei o ta ũrĩa rĩaneeka andũ arĩa angĩ.
16 Ké afúnrúgbìn kúrò ní Babeli, àti ẹni tí ń di dòjé mú ní igà ìkórè! Nítorí idà àwọn aninilára jẹ́ kí oníkálùkù padà sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀, kí oníkálùkù sì sá padà sí ilẹ̀ rẹ̀.
Eheriai ũrĩa ũhaandaga kũu Babuloni, na ũrĩa ũgethaga na rũhiũ rwake hĩndĩ ya magetha. Tondũ wa rũhiũ rũu rwa njora rwa mũhinyanĩrĩria-rĩ, o mũndũ nĩacooke kũrĩ andũ ao, o mũndũ nĩorĩre bũrũri wao kĩũmbe.
17 “Israẹli jẹ́ àgùntàn tí ó ṣìnà kiri, kìnnìún sì ti lé e lọ. Níṣàájú ọba Asiria pa á jẹ, àti níkẹyìn yìí Nebukadnessari ọba Babeli fa egungun rẹ̀ ya.”
“Isiraeli ahaana ta rũũru rũhurunjũkĩte, rũtengʼeretio nĩ mĩrũũthi. Mũthamaki wa Ashuri nĩwe warĩ wa mbere kũmũtambuura; wa kũrigĩrĩria kũmũhehenja mahĩndĩ-rĩ, aarĩ Nebukadinezaru, mũthamaki wa Babuloni.”
18 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí, “Ǹ ó fi ìyà jẹ ọba Babeli àti ilẹ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe fìyà jẹ ọba, Asiria.
Nĩ ũndũ ũcio, Jehova Mwene-Hinya-Wothe, Ngai wa Isiraeli, ekuuga atĩrĩ: “Nĩngaherithia mũthamaki wa Babuloni na bũrũri wake, o ta ũrĩa ndaaherithirie mũthamaki wa Ashuri.
19 Ṣùgbọ́n, èmi yóò mú Israẹli padà wá pápá oko tútù rẹ̀ òun yóò sì máa bọ́ ara rẹ̀ lórí Karmeli àti Baṣani, a ó sì tẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ́rùn ní òkè Efraimu àti ní Gileadi.
No nĩngacookia Isiraeli ũrĩithio-inĩ wake mwene, nake akaarĩithagĩria kũu Karimeli na Bashani; akaarĩĩaga akahũũna kũu irima-inĩ cia Efiraimu, na cia Gileadi.
20 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni Olúwa wí, “À ó wá àìṣedéédéé ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli, ṣùgbọ́n a ki yóò rí ohun; àti ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a ki yóò sì rí mọ kankan nítorí èmi yóò dáríjì àwọn tí ó ṣẹ́kù tí mo dá sí.
Matukũ-inĩ macio, o ihinda-inĩ rĩu-rĩ, ihĩtia rĩa Isiraeli nĩrĩgathuthuurio, no rĩtikoneka, o na mehia ma Juda mathuthuurio, no matikooneka, nĩgũkorwo matigari marĩa ngaahonokia nĩngamarekera,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
21 “Kọlu ilẹ̀ Merataimu àti àwọn tí ó ń gbé ní Pekodi. Lépa rẹ pa, kí o sì parun pátápátá,” ni Olúwa wí, “Ṣe gbogbo ohun tí mo pàṣẹ fún ọ.
“Tharĩkĩrai bũrũri wa Merathaimu, mũũkĩrĩre arĩa matũũraga Pekodi. Matengʼeriei, na mũmoorage, mũmaniine biũ,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “Ĩkai ũrĩa wothe ndĩmwathĩte.
22 Ariwo ogun wà ní ilẹ̀ náà ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ìparun ńlá.
Kũrĩ na mbugĩrĩrio ya mbaara bũrũri-inĩ ũcio, nayo nĩ mbugĩrĩrio ya kũniinanwo kũnene!
23 Báwo ni ó ṣe fọ́, tí ó sì pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ tó, lọ́wọ́ òòlù gbogbo ayé! Báwo ní Babeli ti di ahoro ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
Nyondo ĩrĩa ĩtũũrĩte ĩhũũraga thĩ yothe-rĩ, kaĩ nĩyunangĩtwo, ĩgathethereka-ĩ! Kaĩ Babuloni nĩgũkirĩte ihooru gatagatĩ-inĩ ka ndũrĩrĩ-ĩ!
24 Mo dẹ pàkúté sílẹ̀ fún ọ ìwọ Babeli, kí o sì tó mọ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀, o ti kó sínú rẹ̀. A mú ọ nítorí pé o tako Olúwa.
Ndaakwambĩire mũtego, wee Babuloni, nawe ũkĩgwatio nĩguo ũtekũmenya; wakorereirwo, ũkĩnyiitwo tondũ wa gũkararia Jehova.
25 Olúwa ti kó àwọn ohun èlò ìjà rẹ̀ jáde, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun ti ṣiṣẹ́ ní ilẹ̀ Babeli.
Jehova nĩahingũrĩte harĩa aigaga indo ciake cia mbaara, akaruta indo icio cia mbaara cia mangʼũrĩ make, nĩgũkorwo Mwathani Jehova Mwene-Hinya-Wothe arĩ na wĩra wa kũruta kũu bũrũri-inĩ wa andũ a Babuloni.
26 Ẹ wá sórí rẹ̀ láti òpin gbogbo, sí ilé ìṣúra rẹ̀ sílẹ̀, ẹ kó o jọ bí òkìtì ọkà, kí ẹ sì yà á sọ́tọ̀ fún ìparun, ẹ má ṣe fí yòókù sílẹ̀ fún un.
Ũkaai mũgũtharĩkĩre muumĩte kũndũ kũraya. Thariai makũmbĩ makuo; gũcookanĩrĩriei irũndo ta cia hĩba cia ngano. Kwanangei biũ, na mũtigatigie matigari kuo.
27 Pa gbogbo àwọn akọ màlúù rẹ, jẹ́ kí a kó wọn lọ ibi tí a ó ti pa wọ́n! Ègbé ní fún wọn! Nítorí ọjọ́ wọn dé, àkókò ìbẹ̀wò wọn.
Ũragai tũtegwa twakuo tuothe, tũikũrũkiei tũgathĩnjwo! Kaĩ marĩ na haaro-ĩ! Nĩgũkorwo mũthenya watuo nĩmũkinyu, ihinda rĩatuo rĩa kũherithio.
28 Gbọ́ ohùn àwọn tí ó sálọ, tí ó sì sálà láti Babeli wá, sì sọ ní Sioni, bí Olúwa Ọlọ́run wa ti gbẹ̀san, ẹ̀san fún tẹmpili rẹ̀.
Ta thikĩrĩriai mũigue arĩa moorĩte na arĩa metharĩte makoima bũrũri wa Babuloni, makiumbũra marĩ kũu Zayuni ũrĩa Jehova Ngai witũ erĩhĩirie, akerĩhĩria nĩ ũndũ wa hekarũ yake.
29 “Pe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní gbogbo tafàtafà, sórí Babeli, ẹ dó tí ì yíkákiri, ma jẹ́ ki ẹnikẹ́ni sálà. Sán fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí tí ó ti ṣe, ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ sí i, nítorí tí ó ti gbéraga sí Olúwa, sí Ẹni Mímọ́ Israẹli.
“Ĩtai aikia a mĩguĩ mokĩrĩre Babuloni, o arĩa othe mageetaga ũta. Ambaai hema mũgũthiũrũrũkĩirie; mũtikareke mũndũ o na ũmwe warĩo oore. Rĩrĩhei kũringana na ciĩko ciarĩo; o ta ũrĩa rĩaneeka andũ angĩ-rĩ, rĩĩkei o ta guo. Nĩgũkorwo nĩrĩngʼathĩirie Jehova, o we Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli.
30 Nítorí náà, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ yóò ṣubú ní ìgboro, a ó sì pa àwọn ológun lẹ́nu mọ́,” ní Olúwa wí.
Nĩ ũndũ ũcio, aanake aarĩo nĩmakaagũa njĩra-inĩ cia itũũra; thigari ciarĩo ciothe nĩigakirio ki mũthenya ũcio,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
31 “Wò ó, èmi yóò dojú kọ ọ́ ìwọ agbéraga,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “nítorí ọjọ́ rẹ ti dé, àkókò tí èmi ó bẹ̀ ọ wò.
“Atĩrĩrĩ, nĩngũũkĩrĩire, wee mwĩtĩĩi ũyũ, nĩgũkorwo mũthenya waku nĩmũkinyu, o rĩo ihinda rĩaku rĩa kũherithio,” ũguo nĩguo Mwathani, o we Jehova-Mwene-Hinya-Wothe, ekuuga.
32 Onígbèéraga yóò kọsẹ̀, yóò sì ṣubú, kì yóò sì ṣí ẹni tí yóò gbé dìde. Èmi yóò tan iná ní ìlú náà, èyí tí yóò sì jo run.”
“Mwĩtĩĩi ũcio nĩakahĩngwo agwe, na gũtirĩ mũndũ ũkaamũũkĩria; nĩngagwatia matũũra makuo mwaki, naguo nĩũgaacina arĩa othe mamũrigiicĩirie, maniinwo biũ.”
33 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “A pọ́n àwọn ènìyàn Israẹli lójú àti àwọn ènìyàn Juda pẹ̀lú. Gbogbo àwọn tí ó kó wọn nígbèkùn dì wọn mú ṣinṣin wọn kò sì jẹ́ kí ó sá àsálà.
Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, “Andũ a Isiraeli nĩmahinyĩrĩirio, o ũndũ ũmwe na andũ a Juda. Arĩa othe maamatahire nĩmamarũmĩtie mũno, makarega kũmarekia mathiĩ.
34 Síbẹ̀, Olùràpadà wọn, Alágbára, Olúwa Ọlọ́run Alágbára ni orúkọ rẹ̀. Yóò sì gbe ìjà wọn jà, kí ó ba à lè mú wọn wá sinmi ní ilẹ̀ náà; ṣùgbọ́n kò sí ìsinmi fún àwọn tí ó ń gbé Babeli.
No rĩrĩ, Mũkũũri wao arĩ na hinya; Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩrĩo rĩĩtwa rĩake. Nĩakamarũĩrĩra na kĩyo ciira-inĩ wao, nĩguo atũme bũrũri wao ũgĩe na ũhurũko, no aagithie arĩa matũũraga Babuloni ũhurũko.”
35 “Idà lórí àwọn Babeli!” ni Olúwa wí, “lòdì sí àwọn tó ń gbé ní Babeli, àwọn aláṣẹ àti àwọn amòye ọkùnrin.
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Harĩ na rũhiũ rwa njora rwa gũũkĩrĩra andũ a Babuloni, rũũkĩrĩre arĩa matũũraga Babuloni, na rũũkĩrĩre anene na andũ arĩa ogĩ akuo!
36 Idà lórí àwọn wòlíì èké wọn yóò di òmùgọ̀! Idà lórí àwọn jagunjagun, wọn yóò sì kún fún ẹ̀rù.
Rũhiũ rwa njora rũgookĩrĩra anabii akuo a maheeni, nao matuĩke irimũ. Ningĩ rũhiũ rwa njora nĩrũgookĩrĩra njamba ciakuo iria irĩ hinya, nacio nĩikaiyũrwo nĩ kĩmako kĩnene.
37 Idà lórí àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ àti àwọn àjèjì nínú ẹgbẹ́ rẹ̀. Wọn yóò di obìnrin. Idà lórí àwọn ohun ìṣúra rẹ̀!
Rũhiũ rwa njora rũgookĩrĩra mbarathi, na ngaari cia ita, na andũ a ndũrĩrĩ arĩa marĩ ita-inĩ rĩake, nao matuĩke ta andũ-a-nja. Ningĩ rũhiũ rwa njora nĩrũgookĩrĩra indo ciao iria cia bata ciigĩtwo igĩĩna-inĩ ciao, nacio nĩigatahwo.
38 Ilẹ̀ gbígbẹ lórí omi rẹ̀; yóò sì gbẹ. Nítorí pé ó jẹ́ ilẹ̀ àwọn ère, àwọn ère tí yóò ya òmùgọ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù.
Nĩgũkaara riũa rĩa kũhũithia maaĩ makuo! Namo nĩmakaahũa biũ. Nĩgũkorwo ũcio nĩ bũrũri ũiyũrĩte ngai cia mĩhianano, nao andũ akuo nĩmagũrũkĩtio nĩyo.
39 “Nítorí náà àwọn ẹranko ijù pẹ̀lú ọ̀wàwà ni yóò máa gbé ibẹ̀, abo ògòǹgò yóò sì máa gbé inú rẹ̀, a kì yóò sì gbé inú rẹ̀ mọ́, láéláé, bẹ́ẹ̀ ni a kì yóò ṣàtìpó nínú rẹ̀ láti ìrandíran.
“Nĩ ũndũ ũcio nyamũ cia werũ-inĩ na hiti nĩcio igaatũũraga Babuloni, na kũu no kuo gũgaatũũrwo nĩ ndundu. Gũtigacooka gũtũũrwo nĩ andũ o na kana gũikarwo nĩ andũ, nginya njiarwa na njiarwa.
40 Gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti gba ìjọba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú agbègbè wọn,” ni Olúwa wí, “torí náà kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé ibẹ̀; ènìyàn ki yóò gbé nínú rè.
O ta ũrĩa Ngai aangʼaũranirie Sodomu, na Gomora, o hamwe na matũũra marĩa maariganĩtie namo-rĩ, ũguo noguo gũtarĩ mũndũ ũgaatũũra kuo; gũtirĩ mũndũ ũgaikara kuo,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
41 “Wò ó! Ọ̀wọ́ ọmọ-ogun láti ìhà àríwá; orílẹ̀-èdè ńlá àti àwọn ọba púpọ̀ ni à ń gbé dìde láti òpin ilẹ̀ ayé.
“Atĩrĩrĩ, mbũtũ ya ita nĩ ĩrooka yumĩte mwena wa gathigathini; rũrĩrĩ rũnene, na athamaki aingĩ nĩmarahũrĩtwo kuuma ituri-inĩ cia thĩ.
42 Wọ́n sì di ìhámọ́ra ọ̀kọ̀ àti ọrun, wọ́n burú wọn kò sì ní àánú. Wọ́n n ké bí i rírú omi bí wọ́n ti ṣe ń gun ẹṣin wọn lọ. Wọ́n wá bí àkójọpọ̀ ogun láti kọlù ọ́, ìwọ ọmọbìnrin Babeli.
Marooka marĩ na mota na matimũ mao; nao nĩ andũ ooru, na matarĩ tha. Mũrurumo wao nĩ ta mũrurumo wa ndiihũ cia maaĩ ma iria, magĩũka mahaicĩte mbarathi ciao; mokĩte meyarĩire wega mbaara-inĩ nĩguo magũtharĩkĩre, wee Mwarĩ ũyũ wa Babuloni.
43 Ọba Babeli ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn, ọwọ́ wọn sì rọ, ìrora mú wọn bí obìnrin tí ó ń rọbí.
Mũthamaki wa Babuloni nĩaiguĩte ũhoro wao, namo moko make makoorwo nĩ hinya. Nĩanyiitĩtwo nĩ ruo rũnene ngoro-inĩ yake, na ruo ta rwa mũndũ-wa-nja akĩrũmwo.
44 Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Babeli kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
O ta mũrũũthi ũũkĩte kuuma ihinga-inĩ cia Jorodani ũgakinya ũrĩithio-inĩ ũrĩa mũnoru-rĩ, ũguo noguo ngaingata Babuloni, oime bũrũri-inĩ wake o rĩmwe. Nũũ ũcio ũthuurĩtwo wĩra ũcio nĩgeetha ndĩmũtue wa kũũrũgamĩrĩra? Nũũ ũngĩ ũhaana ta niĩ, ningĩ-rĩ, nũũ ũngĩhota kũngararia? Ningĩ nĩ mũrĩithi ũrĩkũ ũngĩhota kũregana na niĩ?”
45 Nítorí náà, gbọ́ ohun tí Olúwa sọ nípa Babeli, ẹni tí ó gbìmọ̀ lòdì sí Babeli: n ó sì pa agbo ẹran wọn run.
Nĩ ũndũ ũcio, thikĩrĩriai mũigue ũndũ ũrĩa Jehova athugundĩte wa gũũkĩrĩra bũrũri wa Babuloni, o na ũrĩa atuĩte gwĩka bũrũri wa andũ a Babuloni: Arĩa anini rũũru-inĩ magaakururio, matwarwo kũndũ kũraya; nĩakananga ũrĩithio wao ũthire biũ nĩ ũndũ wao.
46 Ní ohùn igbe ńlá pé; a kò Babeli, ilẹ̀ ayé yóò mì tìtì, a sì gbọ́ igbe náà láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.
Mũrurumo wa Babuloni gũgĩtahwo nĩũgathingithia thĩ; kayũ ga kĩrĩro gĩakuo nĩgakaiguuo ndũrĩrĩ-inĩ.

< Jeremiah 50 >