< Jeremiah 5 >
1 “Lọ sókè àti sódò àwọn òpópó Jerusalẹmu, wò yíká, kí o sì mọ̀, kí o sì wá kiri. Bí o bá le è rí ẹnìkan, tí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo, n ó dáríjì ìlú yìí.
“Darasenyo a mapan kadagiti kalsada ti Jerusalem, kasta met nga agsukimatkayo kadagiti plasana. Ket kitaenyo ken panunotenyo daytoy: No makasarakkayo iti tao wenno siasinoman nga agtigtignay a sililinteg ken ikagkagumaanna nga agtignay a sipupudno, pakawanekto ti Jerusalem.
2 Bí wọ́n tilẹ̀ wí pé, ‘Bí Olúwa ti ń bẹ,’ síbẹ̀ wọ́n búra èké.”
Uray no kunada, 'Iti nagan ni Yahweh nga adda iti agnanayon,' inuulbod ti panagsapatada.”
3 Olúwa, ojú rẹ kò ha wà lára òtítọ́? Ìwọ lù wọ́n, kò dùn wọ́n; ìwọ bá wọn wí, wọ́n kọ̀ láti yípadà. Wọ́n mú ojú wọn le ju òkúta lọ, wọ́n sì kọ̀ láti yípadà.
O Yahweh, saan kadi a kinapudno ti sapsapulen dagiti matam? Dinangram dagiti tattao, ngem saanda a makarikna iti ut-ot. Pinarmekmo ida a naan-anay, ngem agkedkedda latta nga umawat iti panangiwanwan. Pagbalbalinenda a natangtangken pay ngem bato dagiti rupada, ta saanda a kayat nga agbabawi.
4 Èmi sì rò pé, “Tálákà ni àwọn yìí; wọn jẹ́ aṣiwèrè, nítorí pé wọn kò mọ ọ̀nà Olúwa, àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.
Isu a kinunak, “Awan duadua a napanglaw laeng dagitoy a tattao. Maagda, ta saanda nga ammo dagiti wagas ni Yahweh, uray pay dagiti paglintegan ti Diosda.
5 Nítorí náà, èmi yóò tọ àwọn adarí lọ, n ó sì bá wọn sọ̀rọ̀; ó dájú wí pé wọ́n mọ ọ̀nà Olúwa àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.” Ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìfìmọ̀ṣọ̀kan, wọ́n ti ba àjàgà jẹ́, wọ́n sì ti já ìdè.
Mapanakto kadagiti mabigbigbig a tattao ket ipakaamok kadakuada dagiti mensahe ti Dios, ta uray kaskasano, ammoda ti wagas ni Yahweh, dagiti paglintegan ti Diosda. Ngem aminda, tinukkolda a sangsangkamaysa ti sangolda; pinugsatda amin dagiti kawar a nangisinggalut kadakuada iti Dios.
6 Nítorí náà, kìnnìún láti inú igbó yóò kọlù wọ́n, ìkookò aginjù yóò sì pa wọ́n run, ẹkùn yóò máa ṣe ibùba sí ẹ̀bá ìlú yín ẹnikẹ́ni tí ó bá jáde ni yóò fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, nítorí àìgbọ́ràn yín pọ, ìpadàsẹ́yìn wọn sì pọ̀.
Isu a rautento ida ti leon nga aggapu iti kasamekan. Dadaelento ida iti atap nga aso nga aggapu idiay Araba. Umayto ti leopardo a maibusor kadagiti siudadda. Marangrangkayto ti siasinoman a rummuar iti siudadna. Ta kumarkarkaro ti panagsalungasingda. Awan panagpatingga ti panangtallikudda iti Dios.
7 “Kí ni ṣe tí èmi ó ṣe dáríjì ọ́? Àwọn ọmọ rẹ ti kọ̀ mí sílẹ̀ àti pé wọ́n ti fi ọlọ́run tí kì í ṣe Ọlọ́run búra. Mo pèsè fún gbogbo àìní wọn, síbẹ̀ wọ́n tún ń ṣe panṣágà wọ́n sì kórajọ sí ilé àwọn alágbèrè.
Apay koma a pakawanek dagitoy a tattao? Tinallikudandak dagiti annakyo a lallaki ken nagsapatada iti nagan dagiti saan a dios. Binussogko ida, ngem nakikamalalada ket napanda iti balay dagiti balangkantis.
8 Wọ́n jẹ́ akọ ẹṣin tí a bọ́ yó, tí ó lágbára, wọ́n sì ń sọkún sí aya arákùnrin wọn.
Kaslada la kadagiti kabalio a makataktakba. Aggarraigida gapu iti tarigagayda a tumakba. Tarigagayan ti tunggal lalaki ti asawa ti kaarrubana.
9 Èmi kì yóò ha ṣe ìbẹ̀wò nítorí nǹkan wọ̀nyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gba ẹ̀san fúnra mi lára irú orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
Isu a saan kadi a rumbeng laeng a dusaek ida- kastoy ti pakaammo ni Yahweh- saan kadi a rumbeng laeng nga agibalesak iti nasion a kas iti daytoy?
10 “Lọ sí ọgbà àjàrà rẹ̀, kí ẹ sì pa wọ́n run, ẹ má ṣe pa wọ́n run pátápátá. Ya ẹ̀ka rẹ̀ kúrò, nítorí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kì í ṣe ti Olúwa.
Sumang-atkayo kadagiti natukad-tukad a kaubasanna ket dadaelenyo dagitoy. Ngem saanyo a dadaelen a maminpinsan dagitoy. Putdenyo dagiti sangada, agsipud ta dagitoy a sanga ket saan a nagtaud kenni Yahweh.
11 Ilé Israẹli àti ilé Juda ti jẹ́ aláìṣòdodo sí mi,” ni Olúwa wí.
Ta liniputandak a naminpinsan dagiti balay ti Israel ken Juda- kastoy ti pakaammo ni Yahweh-
12 Wọ́n ti pa irọ́ mọ́ Olúwa; wọ́n wí pé, “Òun kì yóò ṣe ohun kan! Ibi kan kì yóò sì tọ̀ wá wá; àwa kì yóò sì rí idà tàbí ìyàn.
ken inlaksiddak. Kunada, 'Saan a pudno isuna. Awanto ti dakes a mapagtengtayo, ken saantayonto a makakita iti kampilan wenno agsagaba iti panagbisin.
13 Àwọn wòlíì wá dàbí afẹ́fẹ́, ọ̀rọ̀ kò sí nínú wọn. Nítorí náà, jẹ́ kí ohun tí wọ́n bá sọ ṣẹlẹ̀ sí wọn.”
Ta awanen iti serserbi dagiti profeta, maiyarigdan iti angin, ken awan a pulos ti mangipakpakaammo kadatayo iti mensahe ni Yahweh. Sagabaenda ngarud dagiti pangtada.”'
14 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí: “Nítorí tí àwọn ènìyàn ti sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí; Èmi yóò sọ ọ̀rọ̀ mi lẹ́nu wọn di iná, àti àwọn ènìyàn wọ̀nyí di igi tí yóò jórun.
Isu a kastoy ti kuna ni Yahweh a Manakabalin-amin, “Gapu ta imbagam daytoy, denggem, ngannganikon nga ikabil ti saok dita ngiwatmo. Kaslanto apuy daytoy, ket kaslanto kayo dagitoy a tattao! Ta uramennanto ida.
15 Háà, ẹ̀yin ilé Israẹli,” ni Olúwa wí, “Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè láti ọ̀nà jíjìn dìde sí i yín Orílẹ̀-èdè àtijọ́ àti alágbára nì àwọn ènìyàn tí ìwọ kò mọ èdè rẹ̀, tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò sì yé ọ.
Kitaem, umadanin ti panangiyegko iti maysa a nasion a maibusor kadakayo manipud iti adayo, balay ti Israel- kastoy ti pakaammo ni Yahweh- nabileg daytoy a nasion, nasion nga addan idi un-unana! Daytoy ket nasion a saanyo nga ammo ti pagsasaoda, wenno maawatan dagiti ibagada.
16 Apó-ọfà rẹ sì dàbí isà òkú tí a ṣí gbogbo wọn sì jẹ́ akọni ènìyàn.
Kasla silulukat a tanem ti pana daytoy. Soldadoda amin.
17 Wọn yóò jẹ ìkórè rẹ àti oúnjẹ rẹ, àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti obìnrin, wọn yóò sì jẹ agbo àti ẹran rẹ, wọn yóò jẹ àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ. Pẹ̀lú idà ni wọn ó run ìlú tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé.
Isu a maibusto dagiti apityo, kasta met dagiti annakyo a lallaki ken babbai, ken taraonyo. Kanendanto dagiti arban iti karnero ken bakbakayo; kanendanto dagiti bunga ti ubasyo ken dagiti kayo ti igos. Rebbaendanto babaen iti kampilan dagiti nasarikedkedan a siudadyo nga isu a pagtaltalkanyo.
18 “Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni Olúwa wí, “Èmi kì yóò pa yín run pátápátá.
Ngem uray kadagidiay nga al-aldaw- kastoy ti pakaammo ni Yahweh- saanko a panggep a dadaelenkayo a naan-anay.
19 Àti pé, nígbà tí àwọn ènìyàn bá sì béèrè wí pé, ‘Kí ni ìdí rẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run wa fi ṣe gbogbo èyí sí wa?’ Ìwọ yóò sì sọ fún wọn wí pé, ‘Ẹ̀yin ti kọ̀ mí sílẹ̀, ẹ sì ń sin ọlọ́run àjèjì ní ilẹ̀ yín. Nísinsin yìí, ẹ̀yin yóò máa sin àjèjì ní ilẹ̀ tí kì í ṣe tiyín.’
inton dakayo, Israel ken Juda, ket kunayo, 'Apay nga inaramid kadatayo ni Yahweh a Diostayo amin dagitoy a banbanag? Ket sika, Jeremias, kunaemto kadakuada, 'Kas iti panangtallikudyo kenni Yahweh ken nagrukbabkayo kadagiti gangannaet a dios iti dagayo, agserbikayonto met ngarud kadagiti gangannaet iti daga a saanyo a kukua.'
20 “Kéde èyí fún ilé Jakọbu, kí ẹ sì polongo rẹ̀ ní Juda.
Ipadamagmo daytoy iti balay ni Jacob ken ipangngegmo iti Juda. Kunaem,
21 Gbọ́ èyí, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìlọ́gbọ́n ènìyàn, tí ó lójú ti kò fi ríran tí ó létí ti kò fi gbọ́rọ̀.
'Dengngenyo daytoy, dakayo a maag a tattao nga awan pannakaawatna; addaan kadagiti mata, ngem saan a makakita. Addaanda kadagiti lapayag, ngem saan a makangngeg.
22 Kò ha yẹ kí ẹ bẹ̀rù mi?” ni Olúwa wí. “Kò ha yẹ kí ẹ̀yin ó wárìrì níwájú mi bí? Mo fi yanrìn pààlà òkun, èyí tí kò le è rékọjá rẹ̀ láéláé. Ìjì lè jà, kò le è borí rẹ̀; wọ́n le è bú, wọn kò le è rékọjá rẹ̀.
Saankayo kadi nga agbuteng kaniak- kastoy ti pakaammo ni Yahweh-wenno agpigerger iti sangoanak? Nangikabilak iti darat a kas pannakabeddeng ti baybay, maysa nga agnanayon a paglintegan a saanna a malabsing- uray pay agpangato ken agpababa ti baybay, kaskasdi a saanna a labsingen daytoy. Uray pay agdaranudor dagiti dalluyon daytoy, saanda a lumabes iti daytoy.
23 Ṣùgbọ́n, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ní ọkàn líle àti ọkàn ọ̀tẹ̀, wọ́n ti yípadà, wọ́n sì ti lọ.
Ngem addaan iti natangken a panagpuspuso dagitoy a tattao. Nagsukir ken pimmanawda.
24 Wọn kò sọ fún ara wọn pé, ‘Ẹ jẹ́ ká a bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni tí ó fún wa ní òjò àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò ní ìgbà rẹ̀, tí ó fi wá lọ́kàn balẹ̀ nípa ìkórè ọ̀sẹ̀ déédé.’
Ta saanda a kunaen kadagiti puspusoda, “Agbutengtayo kenni Yahweh a Diostayo, nga isu ti mangmangyeg iti tudo- ti umuna ken maudi a tudo- iti apag-isu a tiempoda, a mangipasigurado iti naituding a lawlawas a panagaapittayo.” Ti kinadakesyo ti nanglapped iti pannakapasamak dagitoy a banbanag.
25 Àìṣedéédéé yín mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí kúrò, ẹ̀ṣẹ̀ yín sì mú kí a fi nǹkan rere dù yín.
Dagiti basbasolyo ti nanglapped iti iyuumay ti naimbag kadakayo.
26 “Láàrín ènìyàn mi ni ìkà ènìyàn wà tí ó wà ní ibùba bí ẹni tí ó ń dẹ ẹyẹ, àti bí àwọn tí ó ń dẹ pàkúté láti mú ènìyàn.
Ta adda nadangkes a lallaki a nailaok kadagiti tattaok. Agbanbantayda a kas iti maysa nga agar-arudok nga agtiliw kadagiti billit; mangipakatda iti palab-og ken tiliwenda dagiti tattao.
27 Bí àgò tí ó kún fún ẹyẹ, ilé wọn sì kún fún ẹ̀tàn; wọ́n ti di ọlọ́lá àti alágbára,
Kas iti tangkal a napunno iti bilbillit, napnoan iti panangallilaw dagiti babbalayda. Isu a dimmakkel ken bimmaknangda.
28 wọ́n sanra wọ́n sì ń dán. Ìwà búburú wọn kò sì lópin; wọn kò bẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ àwọn aláìní baba láti borí rẹ̀. Wọn kò jà fún ẹ̀tọ́ àwọn tálákà.
Limmukmegda; uray la simmileng dagiti kudilda iti kinapintas ti panagbiagda. Limmabesda kadagiti amin a beddeng ti kinadakes. Saanda nga ipakaasi ti kalintegan dagiti tattao, wenno ikanawa dagiti ulila. Rumangrang-ayda uray no saanda nga inikkan iti kalintegan dagiti agkasapulan.
29 Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n fún èyí bí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gbẹ̀san ara mi lára orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
Saan kadi a nasken a dusaek ida gapu kadagitoy a banbanag- kastoy ti pakaammo ni Yahweh- ken saan kadi a rumbeng laeng a balsek ti nasion a kas iti daytoy?
30 “Nǹkan ìbànújẹ́ àti ohun ìtara ti ṣẹlẹ̀ ní ilẹ̀ náà.
Nakabutbuteng ken nakaal-alinggaget ti napasamak iti daga.
31 Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké, àwọn àlùfáà sì ń ṣe àkóso pẹ̀lú àṣẹ ara wọn, àwọn ènìyàn mi sì ní ìfẹ́ sí èyí, kí ni ẹ̀yin yóò ṣe ní òpin?
Nagipadto dagiti profeta iti inaallilaw, ken agturturay dagiti papadi iti bukodda a bileg. Kaykayat dagiti tattaok ti kastoy a wagas, ngem anianto ti mapasamak iti kamaudianan?