< Jeremiah 5 >

1 “Lọ sókè àti sódò àwọn òpópó Jerusalẹmu, wò yíká, kí o sì mọ̀, kí o sì wá kiri. Bí o bá le è rí ẹnìkan, tí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo, n ó dáríjì ìlú yìí.
Yelusaleme fi dunu! Dilia logoga hehenama! Ba: le gagama! Dilisu ba: ma! Bidi lasu soge amo ganodini hogoi helema! Dilia da moloidafa hamosu dunu afae ba: ma: bela: ? Dilia Godema mae hohonone moloidafa fa: no bobogesu dunu afae ba: ma: bela: ? Hame mabu! Be dilia agoaiwane dunu afae ba: sea, Hina Gode da Yelusaleme fi ilia wadela: i hou gogolema: ne olofomu.
2 Bí wọ́n tilẹ̀ wí pé, ‘Bí Olúwa ti ń bẹ,’ síbẹ̀ wọ́n búra èké.”
Dilia da Hina Godema nodone sia: ne gadosa, dilisu da sia: sa. Be dilia da ogogosa.
3 Olúwa, ojú rẹ kò ha wà lára òtítọ́? Ìwọ lù wọ́n, kò dùn wọ́n; ìwọ bá wọn wí, wọ́n kọ̀ láti yípadà. Wọ́n mú ojú wọn le ju òkúta lọ, wọ́n sì kọ̀ láti yípadà.
Hina Gode da mae hohonone moloidafa fa: no bobogesu hou hogosa. E da dili fai dagoi, be dilia amo hame dawa: i galu. E da dili goudale fasi, be dilia da amoba: le dilia hou hame hahamoi. Dilia da ga: nasi hamoiba: le, dilia wadela: i hou fisimusa: hame dawa: iou.
4 Èmi sì rò pé, “Tálákà ni àwọn yìí; wọn jẹ́ aṣiwèrè, nítorí pé wọn kò mọ ọ̀nà Olúwa, àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.
Amalalu, na da agoane dawa: i, “Amo da hame gagui amola hame dawa: su dunu fawane. Ilia da gagaoui agoane hamosa. Ilia Gode Ea hanai amo hame dawa:
5 Nítorí náà, èmi yóò tọ àwọn adarí lọ, n ó sì bá wọn sọ̀rọ̀; ó dájú wí pé wọ́n mọ ọ̀nà Olúwa àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.” Ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìfìmọ̀ṣọ̀kan, wọ́n ti ba àjàgà jẹ́, wọ́n sì ti já ìdè.
Amaiba: le, na da ouligisu hou gagui dunu ilima asili, ilima sia: mu. Na da agoane dawa: , ‘Ilia da Gode Ea hanai dawa: mu. Ilia hamoma: ne, Hina Gode Ea sia: i liligi ilia da dawa: mu.’ Be ilia huluane da Hina Gode Ea ouligisu hou amo higale yolesi dagoi. Ilia da Ea sia: nabimu higasa.
6 Nítorí náà, kìnnìún láti inú igbó yóò kọlù wọ́n, ìkookò aginjù yóò sì pa wọ́n run, ẹkùn yóò máa ṣe ibùba sí ẹ̀bá ìlú yín ẹnikẹ́ni tí ó bá jáde ni yóò fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, nítorí àìgbọ́ràn yín pọ, ìpadàsẹ́yìn wọn sì pọ̀.
Amaiba: le, iwilaga esalebe laione wa: me da ili medole legemu. Hafoga: i sogega esalebe ‘wufi’ wa: me da ili medole legele, dadalega: mu. Amola ‘lebade’ wa: me da ilia moilai amo ganodini wamowane manebe ba: mu. Amo dunu da ilia diasu gadili ahoasea, ilia da: i da gadelale fofonoboi dagoi ba: mu. Bai ilia wadela: i hou hamoi da bagohame. Amola eso huluane, mae fisili, ilia da Godema baligi fa: su.
7 “Kí ni ṣe tí èmi ó ṣe dáríjì ọ́? Àwọn ọmọ rẹ ti kọ̀ mí sílẹ̀ àti pé wọ́n ti fi ọlọ́run tí kì í ṣe Ọlọ́run búra. Mo pèsè fún gbogbo àìní wọn, síbẹ̀ wọ́n tún ń ṣe panṣágà wọ́n sì kórajọ sí ilé àwọn alágbèrè.
Hina Gode da amane adole ba: i, “Na da abuliba: le Na fi ilia wadela: i hou gogolema: ne olofoma: bela: ? Ilia da Na yolesili, ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu. Na fi dunu sadima: ne, Na da ha: i manu iligili i. Be ilia da inia uda adole lasu hou hamosu amola hina: da: i bidi lasu uda ilima fa: no bobogei.
8 Wọ́n jẹ́ akọ ẹṣin tí a bọ́ yó, tí ó lágbára, wọ́n sì ń sọkún sí aya arákùnrin wọn.
Ilia da hosi gawali amo da sadi dagoi amola aseme amoma fima: ne nimi bagade hamosa, amo defele gala. Ilia afae afae ea na: iyado idua amo lale, gilisili golamu hanai bagade.
9 Èmi kì yóò ha ṣe ìbẹ̀wò nítorí nǹkan wọ̀nyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gba ẹ̀san fúnra mi lára irú orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
Ilia da amo hou hamobeba: le, Na da ilima se imunu da defea. Agoaiwane fi ilima dabe imunu da defea.
10 “Lọ sí ọgbà àjàrà rẹ̀, kí ẹ sì pa wọ́n run, ẹ má ṣe pa wọ́n run pátápátá. Ya ẹ̀ka rẹ̀ kúrò, nítorí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kì í ṣe ti Olúwa.
Na da ha lai dunu amo Na fi dunu ilia waini sagai hedofama: ne asunasimu. Be amo da dafawane wadela: lesi ebelei dagoi hame ba: mu. Na da ha lai amoma, e da amoda huluane gole fasima: ne Na da sia: mu. Bai amo amoda da Na: hame.
11 Ilé Israẹli àti ilé Juda ti jẹ́ aláìṣòdodo sí mi,” ni Olúwa wí.
Isala: ili dunu amola Yuda dunu da Na dafawanedafa hohonoi. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
12 Wọ́n ti pa irọ́ mọ́ Olúwa; wọ́n wí pé, “Òun kì yóò ṣe ohun kan! Ibi kan kì yóò sì tọ̀ wá wá; àwa kì yóò sì rí idà tàbí ìyàn.
Hina Gode Ea fi dunu da E yolesi. Ilia da amane sia: sa, “Gode da ninima se hame imunu. Ninia da gasa bagade hou hame ba: mu. Ninia da gegesu amola ha: su hame ba: mu.”
13 Àwọn wòlíì wá dàbí afẹ́fẹ́, ọ̀rọ̀ kò sí nínú wọn. Nítorí náà, jẹ́ kí ohun tí wọ́n bá sọ ṣẹlẹ̀ sí wọn.”
14 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí: “Nítorí tí àwọn ènìyàn ti sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí; Èmi yóò sọ ọ̀rọ̀ mi lẹ́nu wọn di iná, àti àwọn ènìyàn wọ̀nyí di igi tí yóò jórun.
Ilia da amane sia: sa, “Balofede dunu ilia sia: da fo fawane. Ilia da Hina Gode Ea sia: hame gaguli maha.” Hina Gode Bagadedafa da nama amane sia: i, “Yelemaia! Amo dunu da agoane sia: beba: le, Na da sia: dia lafiga gala amo lalu agoane hamomu. Na fi dunu da lalu ifa agoane ba: mu, amola Na agoane sia: nanu ili da nei dagoi ba: mu.”
15 Háà, ẹ̀yin ilé Israẹli,” ni Olúwa wí, “Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè láti ọ̀nà jíjìn dìde sí i yín Orílẹ̀-èdè àtijọ́ àti alágbára nì àwọn ènìyàn tí ìwọ kò mọ èdè rẹ̀, tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò sì yé ọ.
Isala: ili dunu! Dilia! Hina Gode da fi sedagaga esalebe, amo dilima doaga: la: ma: ne, oule misunu. Amo fi da gasa bagade hemone fi amola dilia da ilia sia: hame dawa:
16 Apó-ọfà rẹ sì dàbí isà òkú tí a ṣí gbogbo wọn sì jẹ́ akọni ènìyàn.
Ilia dadi gagui dunu da gasa bagade. Ilia da mae asigili medole lelegelala.
17 Wọn yóò jẹ ìkórè rẹ àti oúnjẹ rẹ, àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti obìnrin, wọn yóò sì jẹ agbo àti ẹran rẹ, wọn yóò jẹ àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ. Pẹ̀lú idà ni wọn ó run ìlú tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé.
Ilia da dilia ha: i manu amola bugi huluane na dagomu. Ilia da dilia dunu mano amola uda mano huluane medole lelegemu. Ilia da dilia sibi amola bulamagau gilisisu medole legemu. Amola dilia waini efe amola figi ifa ilia da wadela: lesimu. Dilia gagili sali moilai da dili gaga: mu, dilia dawa: sa. Be ilia dadi gagui da amo huluane mugululi wadela: lesimu.”
18 “Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni Olúwa wí, “Èmi kì yóò pa yín run pátápátá.
Hina Gode da amane sia: sa, “Be amo se nabasu esoga, Na da Na fi dunu huluanedafa hame wadela: lesimu. Afae afae da esalebe ba: mu.
19 Àti pé, nígbà tí àwọn ènìyàn bá sì béèrè wí pé, ‘Kí ni ìdí rẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run wa fi ṣe gbogbo èyí sí wa?’ Ìwọ yóò sì sọ fún wọn wí pé, ‘Ẹ̀yin ti kọ̀ mí sílẹ̀, ẹ sì ń sin ọlọ́run àjèjì ní ilẹ̀ yín. Nísinsin yìí, ẹ̀yin yóò máa sin àjèjì ní ilẹ̀ tí kì í ṣe tiyín.’
Amola, Yelemaia, di! Ilia da Na da abuliba: le amo hou hamobela: le adole ba: sea, ilima bu adole ima, ‘Bai ilia da Na yolesili, ilia soge ganodini ga fi ogogosu ‘gode’ ilima hawa: hamosu, amo defele ilia da eno fi dunu ilia soge ganodini, amo ga fi dunu ilia se iasu hawa: hamosu hamonanumu.’”
20 “Kéde èyí fún ilé Jakọbu, kí ẹ sì polongo rẹ̀ ní Juda.
Hina Gode da amane sia: sa, “Ya: igobe egaga fi, amola Yuda fi dunu ilima amane sia: ma,
21 Gbọ́ èyí, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìlọ́gbọ́n ènìyàn, tí ó lójú ti kò fi ríran tí ó létí ti kò fi gbọ́rọ̀.
‘Dilia gagaoui amola hame dawa: su dunu! Dawa: ma: i! Dilia da si gala be ba: mu gogolei! Dilia da ge gala be hame naba!
22 Kò ha yẹ kí ẹ bẹ̀rù mi?” ni Olúwa wí. “Kò ha yẹ kí ẹ̀yin ó wárìrì níwájú mi bí? Mo fi yanrìn pààlà òkun, èyí tí kò le è rékọjá rẹ̀ láéláé. Ìjì lè jà, kò le è borí rẹ̀; wọ́n le è bú, wọn kò le è rékọjá rẹ̀.
Na da Hina Gode! Dilia abuliba: le Nama hame nodone beda: bela: ? Dilia da abuliba: le Na midadi hame yagugusala: ? Na da sa: iboso amo hano wayabo bagade ea alalo legei dagoi. Amo alalo legesu da eso huluane dialumu, amola hano bagade da amo baligimu hame dawa: Hano bagade da gafulusa be amo alalo legesu hame baligisa. Hano gafului da fugala: sa, be osoba amo ganodini golili misunu hame dawa:
23 Ṣùgbọ́n, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ní ọkàn líle àti ọkàn ọ̀tẹ̀, wọ́n ti yípadà, wọ́n sì ti lọ.
Be dilia Na fi dunu! Dilia da gasa fili, odoga: su dunu. Dilia da la: ididili asili, Na yolesi.
24 Wọn kò sọ fún ara wọn pé, ‘Ẹ jẹ́ ká a bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni tí ó fún wa ní òjò àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò ní ìgbà rẹ̀, tí ó fi wá lọ́kàn balẹ̀ nípa ìkórè ọ̀sẹ̀ déédé.’
Na da woufo gibu amola mugi gibu dilima iasu amola dilia hahawane bugi gamini moma: ne eso dilima iasu. Be dilia da Nama nodomu hame dawa: i galu.
25 Àìṣedéédéé yín mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí kúrò, ẹ̀ṣẹ̀ yín sì mú kí a fi nǹkan rere dù yín.
Be dilia da wadela: le hamobeba: le, amo liligi ida: iwane hame ba: i.
26 “Láàrín ènìyàn mi ni ìkà ènìyàn wà tí ó wà ní ibùba bí ẹni tí ó ń dẹ ẹyẹ, àti bí àwọn tí ó ń dẹ pàkúté láti mú ènìyàn.
Na fi dunu gilisisu ganodini da wadela: idafa dunu esalebe. Ilia da dunu ilia sio sa: ima: ne sanebe, amo defele dunu dafama: ne, sanigesa.
27 Bí àgò tí ó kún fún ẹyẹ, ilé wọn sì kún fún ẹ̀tàn; wọ́n ti di ọlọ́lá àti alágbára,
Benea ahoasu dunu da sio lale, ea gagili amo ganodini sala, amo defele ilia inia liligi lale, ilia diasu nabama: ne ligisisa. Amaiba: le, ilia da bagade gagui amola gasa bagade ba: sa.
28 wọ́n sanra wọ́n sì ń dán. Ìwà búburú wọn kò sì lópin; wọn kò bẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ àwọn aláìní baba láti borí rẹ̀. Wọn kò jà fún ẹ̀tọ́ àwọn tálákà.
Ilia da sadi dagoi amola dunu basului agoane ba: sa. Ilia da baligili, mae yolele, wadela: i hou hamonana. Ilia da guluba: mano hame fidisa, amola hame gagui banenesi dunu ilima moloidafa fofada: su imunu hame dawa:
29 Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n fún èyí bí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gbẹ̀san ara mi lára orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
Be Na, Hina Gode, da ilia wadela: i hou hamobeba: le, ilima se imunu. Na da amo fima dabe imunu.
30 “Nǹkan ìbànújẹ́ àti ohun ìtara ti ṣẹlẹ̀ ní ilẹ̀ náà.
Yuda soge ganodini, fofogadigisu wadela: i houdafa da doaga: i dagoi.
31 Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké, àwọn àlùfáà sì ń ṣe àkóso pẹ̀lú àṣẹ ara wọn, àwọn ènìyàn mi sì ní ìfẹ́ sí èyí, kí ni ẹ̀yin yóò ṣe ní òpin?
Balofede dunu da ogogole fawane sia: sa. Gobele salasu dunu da balofede dunu ilia sia: defele ouligisa, amola Na fi dunu da ilia wadela: i logo hame hedofasa. Be amo hou ea dabe doaga: sea, ilia da adi hamoma: bela: ?’”

< Jeremiah 5 >