< Jeremiah 49 >

1 Nípa Ammoni. Báyìí ni Olúwa wí, “Israẹli kò ha ní ọmọkùnrin? Israẹli kò ha ní àrólé bí? Nítorí kí ni Malkomu ṣe jogún Gadi? Kí ló dé tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ń gbé ìlú rẹ̀?
Mo nga tamariki a Amona. Ko te kupu tenei a Ihowa: Kahore ianei a Iharaira tamariki? kahore ana tangata hei whakarerenga iho mo ana taonga? na he aha a Kara i riro ai i a Marakomo, i noho ai tona iwi ki roto ki ona pa?
2 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí; “nígbà tí èmi yóò mú kí a gbọ́ ìdágìrì ogun ní Rabba tí Ammoni; yóò sì di òkìtì ahoro, gbogbo ìlú tí ó yí i ká ni a ó jó níná. Nígbà náà ni Israẹli yóò lé wọn, àwọn tí ó ti lé e jáde,” ni Olúwa wí.
Mo reira, tenei nga ra te haere mai nei, e ai ta Ihowa, e meinga ai e ahau te whakaoho o te riri kia rangona ki Rapa o nga tama a Amona; a ka waiho hei puranga kua ururuatia, ka tahuna ana tamahine ki te ahi: a ka riro i a Iharaira te hunga i a r atou nei ia i mua, e ai ta Ihowa.
3 “Hu, ìwọ Heṣboni, nítorí Ai tí rún! Kígbe ẹ̀yin olùgbé Rabba! Ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀ kí ẹ sì ṣọ̀fọ̀. Ẹ sáré sókè sódò nínú ọgbà, nítorí Malkomu yóò lọ sí ìgbèkùn, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti ìjòyè rẹ̀.
Aue, e Hehepona, kua pahuatia hoki a Hai; e tangi, e nga tamahine a Rapa, whitikiria koutou ki te kakahu taratara: e tangi, ka omaoma noa i waenga i nga taiepa; no te mea ka riro a Marakomo i te whakarau, ona tohunga me ona rangatira ngatahi ano.
4 Èéṣe tí ìwọ fi ń ṣògo nínú àfonífojì rẹ, ṣògo nínú àfonífojì rẹ fún èso? Ẹ̀yin ọmọbìnrin Ammoni aláìṣòótọ́, ẹ gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ yín, ẹ sì wí pé, ‘Ta ni yóò kò mí lójú?’
He aha koe i whakamanamana ai ki nga raorao, ki tou raorao taheke, e te tamahine tahurihuri ke? e whakawhirinaki nei ki ona taonga, e mea nei, Ko wai e haere mai ki ahau?
5 Èmi yóò mu ẹ̀rù wá lórí rẹ láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tó yí ọ ká,” ni Olúwa, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Nana, ka takina e ahau he wehi ki runga ki a koe, e ai ta te Ariki, ta Ihowa o nga mano, he mea na te hunga katoa i tetahi taha ou, i tetahi taha; a ka aia rawatia atu koutou, tera, tera, ki waho, a kahore he kaitawhiu mai mo te mea i marara atu.
6 “Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Gbogbo yín ni ó lé jáde, kò sì ṣí ẹnìkan tí yóò dá ìkólọ Ammoni padà,” ni Olúwa wí.
Hei muri ia ka whakahokia e ahau nga tama a Amona i te whakarau, e ai ta Ihowa.
7 Nípa Edomu. Èyí ní ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ṣe kò ha sí ọgbọ́n mọ́ ni Temani? Ṣé a ti ké ìmọ̀ràn kúrò ní ọ̀dọ̀ olóyè? Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ bí?
Mo Eroma. Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano: Kua kahore ranei te whakaaro nui i Temana? kua moti ianei te whakatakoto korero a te hunga mohio? kua memeha ranei to ratou whakaaro nui?
8 Yípadà kí o sálọ, sá pamọ́ sínú ihò, ìwọ tí ó ń gbé ní Dedani, nítorí èmi yóò mú ibi wá sórí Esau, ní àkókò tí èmi ó bẹ̀ ẹ́ wò.
E rere koutou, tahuri atu, hei roro riro noho ai, e nga tangata o Rerana; no te mea ka takina mai e ahau te aitua o Ehau ki runga ki a ia, i te wa e tirotiro ai ahau i a ia.
9 Tí àwọn tí ń ṣa èso bá tọ̀ ọ́ wá; ǹjẹ́ wọn kò ní fi èso díẹ̀ sílẹ̀? Tí olè bá wá ní òru; ǹjẹ́ wọn kò ní kó gbogbo ohun tí wọ́n bá fẹ́?
Ki te tae atu he kaikohikohi karepe ki a koe, e kore ianei e mahue i a ratou etahi karepe hei hamunga? ki te mea he tahae i te po, e kore ianei ratou e tukituki kia makona rawa ratou?
10 Ṣùgbọ́n èmi yóò tu Esau sí ìhòhò, èmi ti fi ibi ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ hàn, nítorí kí o máa ba à fi ara rẹ pamọ́. Àwọn ọmọ rẹ, ẹbí rẹ àti àwọn ará ilé rẹ yóò parun. Wọn kò sì ní sí mọ́.
Kua takoto kau ia i ahau a Ehau, kua hurahia e ahau ona wahi ngaro, te ahei ia te huna i a ia: kua oti ona uri te pahua, ona teina me ona hoa tata, a kua kore hoki ia.
11 Fi àwọn ọmọ aláìní baba sílẹ̀ èmi yóò dáàbò bo ẹ̀mí wọn. Àwọn opó rẹ gan an lè gbẹ́kẹ̀lé mi.”
Waiho au pani, maku e whakaora; ko ou pouaru, kia whakawhirinaki ratou ki ahau.
12 Èyí ni ohun tí Olúwa wí bí ẹnikẹ́ni tí kò bá yẹ kí ó mu ago náà bá mú un, kí ló dé tí ìwọ yóò fi lọ láìjìyà? Ìwọ kò ní lọ láìjìyà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò mú un.
Ko te kupu hoki tenei a Ihowa: Nana, ko te hunga i takoto nei te tikanga kia kaua e inu i te kapu, he pono ka inumia e ratou; a ko koe ranei te mea e kore rawa e whiua? e kore e kore ka whiua koe, engari ka tino inu nei koe.
13 Èmi fi ara mi búra ni Olúwa wí, wí pé, “Bosra yóò ba ayé ara rẹ̀ jẹ́. Yóò di ẹni ẹ̀gàn, ẹni èpè àti ẹni ègún, àti gbogbo ìlú rẹ̀ yóò di ìbàjẹ́ títí láé.”
No te mea kua waiho ahau e ahau ano hei oati, e ai ta Ihowa, ka waiho a Potora hei miharotanga, hei ingoa kino, hei ururua, hei kanga ano hoki; a ka waiho ona pa katoa hei koraha ake ake.
14 Ní gbígbọ́, èmi ti gbọ́ ìró kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa, a rán ikọ̀ kan sí orílẹ̀-èdè pé, ẹ kó ara yín jọ, ẹ wá sórí rẹ̀, ẹ sì dìde láti jagun.
Kua rangona e ahau he korero i a Ihowa, kua oti hoki te karere te tuku ki nga iwi, hei ki atu, Whakahuihui i a koutou, haere mai hoki ki a ia, a ka whakatika atu ki te whawhai.
15 “Ní báyìí, èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo; ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ènìyàn.
No te mea, na, kua meinga koe e ahau kia iti i roto i nga tauiwi, he mea whakahawea i roto i nga tangata.
16 Ìpayà tí ìwọ ti fà sínú ìgbéraga ọkàn rẹ sì ti tàn ọ́ jẹ; ìwọ tí ń gbé ní pàlàpálá àpáta, tí o jókòó lórí ìtẹ́ gíga síbẹ̀ o kọ́ ìtẹ́ rẹ ga gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ idì; láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá,” ni Olúwa wí.
Tena ko tou whakamataku, he whakakake no tou ngakau i pohewa ai koe, e koe e noho na i nga kapiti o te kamaka, e pupuri na i te wahi tiketike o te pukepuke: ahakoa hanga e koe tou ohanga kia rite ki to te ekara te tiketike, ka whakahokia iho koe e ahau i reira, e ai ta Ihowa.
17 “Edomu yóò di ahoro gbogbo àwọn tí ń kọjá yóò jáyà, wọn ó sì fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà nítorí gbogbo ìpalára rẹ.
A ka meinga a Eroma hei miharotanga: ko nga tangata katoa e tika ana na reira, ka miharo, ka hi mai ki ona whiunga katoa.
18 Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká rẹ,” ní Olúwa wí. “Bẹ́ẹ̀ ni, kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé níbẹ̀; kò sì ní sí ènìyàn tí yóò tẹ̀dó síbẹ̀ mọ́.
Ka rite ki te hurihanga o Horoma, o Komora, o nga pa hoki i tata ki reira, e ai ta Ihowa, e kore tetahi tangata e whai kainga ki reira, e kore hoki tetahi tama a te tangata e noho ki reira.
19 “Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Edomu kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
Nana, ka rite ia ki te raiona e haere ake ana i te whakamanamana o Horano ki te nohoanga kaha: otiia ka meinga ohoreretia ai e ahau kia rere atu i a ia; a ko wai te mea e whiriwhiria e ahau ko ia hei rangatira mona? Ko wai hoki e rite ana ki aha u? ko wai hei whakarite he wa moku? ko wai ano tenei hepara hei tu ki toku aroaro?
20 Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí Olúwa ní fún Edomu, ohun tí ó ní ní pàtàkì fún àwọn tí ń gbé ní Temani. Àwọn ọ̀dọ́ àgbò ni à ó lé jáde; pápá oko wọn ni yóò run nítorí wọn.
Mo reira whakarongo ki te tikanga a Ihowa kua whakatakotoria e ia mo Eroma; ki ona whakaaro hoki, kua whakaaroa e ia mo nga tangata o Temana: He pono ka toia atu ratou, ara nga mea ririki o te kahui; he pono ka meinga e ia to ratou nohoanga, rat ou hoki kia ngaro.
21 Ilẹ̀ yóò mì tìtì nípa ariwo ìṣubú wọn, a ó gbọ́ igbe wọn ní Òkun pupa.
Oho ana te whenua i te haruru o to ratou hinganga: tera te hamama, rangona ana mai tona ngangau i te Moana Whero.
22 Wò ó! Ẹyẹ idì yóò gòkè fò wálẹ̀, yóò tẹ ìyẹ́ rẹ̀ lórí Bosra. Ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn ajagun Edomu yóò dàbí ọkàn obìnrin tí ń rọbí.
Nana, ka haere mai ia a ka rere ano he ekara, a ka roha atu ona parirau ki runga ki Potora: a ka rite te ngakau o nga marohirohi o Eroma i taua ra ki te ngakau o te wahine e whakamamae ana.
23 Nípa Damasku. “Inú Hamati àti Arpadi bàjẹ́ nítorí wọ́n gbọ́ ìròyìn búburú, ìjayà dé bá wọn, wọ́n sì dààmú bí omi Òkun.
Mo Ramahiku. Kua whakama a Hamata, raua ko Arapara; no te mea kua tae he rongo kino ki a ratou, harotu kau ratou: tera te tangi kei te moana; kahore e marino.
24 Damasku di aláìlera, ó pẹ̀yìndà láti sálọ, ìwárìrì sì dé bá a; ìbẹ̀rù àti ìrora dìímú, ìrora bí ti obìnrin tí ó wà ní ipò ìrọbí.
Kua ngoikore a Ramahiku, kua anga ki te rere, mau pu hoki i te wehi: kua rokohanga hoki ia e te raru, e te mamae, me te mea he wahine e whanau ana.
25 Kí ló dé tí ìlú olókìkí di ohun ìkọ̀sílẹ̀; ìlú tí mo dunnú sí.
Taukiri e! kihai i mahue te pa e whakamoemititia ana, te pa i koa ai ahau!
26 Lóòtítọ́, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ yóò ṣubú lójú pópó, gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ yóò pa ẹnu mọ́ ní ọjọ́ náà,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Heoi hinga ana ana taitama i ona waharoa, moti pu nga tangata whawhai katoa i taua ra, e ai ta Ihowa o nga mano.
27 “Èmi yóò fi iná sí odi Damasku, yóò sì jó gbọ̀ngàn Beni-Hadadi run.”
Na ka tahuna ano e ahau he ahi i roto i te taiepa o Ramahiku, a ka pau i reira nga whare kingi o Peneharara.
28 Nípa ìlú Kedari àti ìjọba Hasori èyí ti Nebukadnessari ọba Babeli dojú ìjà kọ, èyí ni ohun tí Olúwa sọ, “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ ìlú Kedari, kí o sì pa àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn run.
Mo Kerara, mo nga kingitanga hoki o Hatoro i patua nei e Nepukareha kingi o Papurona. Ko te kupu tenei a Ihowa: Whakatika koutou, whakaekea a Kerara, pahuatia hoki nga tama o te rawhiti.
29 Àgọ́ wọn àti agbo àgùntàn wọn ni wọn ó kó lọ; àgọ́ wọn yóò di ìṣínípò padà pẹ̀lú gbogbo ẹrù àti ìbákasẹ wọn. Àwọn ènìyàn yóò ké sórí wọ́n pé, ‘Ẹ̀rù yí káàkiri!’
Ka tangohia e ratou o ratou teneti, a ratou hipi; a ka mauria atu e ratou ma ratou o ratou kakahu arai, a ratou oko katoa, me a ratou kamera: a tera ratou e karanga ki a ratou, He wehi kei nga taha katoa.
30 “Sálọ kíákíá! Fi ara pamọ́ sí ibi jíjìn, ẹ̀yin olùgbé Hasori,” ni Olúwa wí. “Nebukadnessari ọba Babeli ti dojú ìjà kọ ọ́.
E rere koutou, haere atu ki tawhiti, nohoia a roto riro, e nga tangata o Hatoro, e ai ta Ihowa; kua takoto hoki te tikanga a Nepukareha kingi o Papurona mo koutou, kua whakaaroa hoki e ia he whakaaro mo koutou.
31 “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ orílẹ̀-èdè tí ó wà nínú ìrọ̀rùn, èyí tí ó gbé ní àìléwu,” ní Olúwa wí. “Orílẹ̀-èdè tí kò ní odi tàbí irin, àwọn ènìyàn rẹ̀ ń dágbé.
Whakatika, whakaekea te iwi e noho ana i te rangimarie, e noho kore wehi na, e ai ta Ihowa; kahore na o ratou keti, kahore he tutaki, e noho takitahi ana.
32 Àwọn ìbákasẹ á di ẹrù àti àwọn ẹran ọ̀sìn, wọ́n á di ìkógun. Èmi yóò tú àwọn tí ó wà ní òkèèrè sí inú afẹ́fẹ́. Èmi yóò sì mú ibi wá sí àyíká gbogbo,” báyìí ní Olúwa wí.
A ka pahuatia a ratou kamera, a hei taonga parau hoki te tini o a ratou kararehe: a ka whakamararatia e ahau ki nga hau katoa te hunga i tapahia nga tapa o o ratou makawe; a ka takina mai e ahau te aitua mo ratou i nga taha katoa o ratou, e ai t a Ihowa.
33 “Hasori yóò di ibi ìdọdẹ àwọn akátá, ibi ìkọ̀sílẹ̀ ayérayé, kò sí ẹni tí yóò gbé ní ibẹ̀.”
A hei nohoanga a Hatoro mo nga kuri mohoao, hei ururua ake ake: e kore tetahi tangata e whai kainga ki reira, e kore ano hoki tetahi tama a te tangata e noho ki reira.
34 Èyí ní ọ̀rọ̀ Olúwa èyí tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa Elamu ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekiah ọba Juda.
Ko te kupu a Ihowa i puta mai ki a Heremaia poropiti mo Erama i te timatanga o te kingitanga o Terekia kingi o Hura; i mea ia,
35 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “Wò ó, èmi yóò fọ́ ìtẹ̀gùn Elamu, ẹni tí wọ́n sinmi lé nípa agbára.
Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano: Nana, ka whatiia e ahau te kopere a Erama, te mea nui rawa o to ratou kaha.
36 Èmi yóò mú kí afẹ́fẹ́ orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé lòdì sí Elamu. Èmi yóò tú wọn ká sí ìpín afẹ́fẹ́ mẹ́rin àti pé, kò sí orílẹ̀-èdè tí ilẹ̀ àjèjì Elamu kò ní lọ.
A ka takina atu e ahau nga hau e wha i nga pito e wha o te rangi ki runga ki Erama, a ka titaritaria atu ratou e ahau ki aua hau katoa; kahore hoki he iwi e kore te taea atu e te hunga o Erama ka peia atu nei.
37 Èmi yóò kẹ́gàn Elamu níwájú àwọn ọ̀tá wọn, àti níwájú àwọn tí wọ́n ń wá ẹ̀mí wọn, Èmi yóò mú ibi wá sí orí wọn, àní, ìbínú gbígbóná mi,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Èmi yóò lé wọn pẹ̀lú idà, di ìgbà tí èmi yóò rẹ́yìn wọn.
A ka meinga e ahau a Erama kia wehi i te aroaro o ona hoariri, i te aroaro hoki o te hunga e whai ana kia whakamatea ratou: ka takina hoki e ahau he kino ki runga ki a ratou, ko toku riri e mura ana, e ai ta Ihowa; a ka unga e ahau te hoari ki m uri i a ratou, a kia poto ra ano ratou i ahau:
38 Èmi yóò sì gbé ìtẹ́ mi kalẹ̀ ní Elamu, èmí yóò sì pa ọba wọn àti ìjòyè wọn run,” báyìí ni Olúwa wí.
Na ka whakaturia e ahau toku torona ki Erama, a ka whakakahoretia atu to reira kingi, ratou ko nga rangatira, e ai ta Ihowa.
39 “Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ Elamu padà láìpẹ́ ọjọ́,” báyìí ni Olúwa wí.
Otiia hei nga ra whakamutunga ka whakahokia e ahau a Erama i te whakarau, e ai ta Ihowa.

< Jeremiah 49 >