< Jeremiah 49 >

1 Nípa Ammoni. Báyìí ni Olúwa wí, “Israẹli kò ha ní ọmọkùnrin? Israẹli kò ha ní àrólé bí? Nítorí kí ni Malkomu ṣe jogún Gadi? Kí ló dé tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ń gbé ìlú rẹ̀?
Ũhoro ũkoniĩ andũ a Amoni: Jehova ekuuga atĩrĩ: “Kaĩ Isiraeli atarĩ na aanake? Ndarĩ na andũ a kũmũgaya? Nĩ kĩĩ gĩgĩtũmĩte Moleku egwatĩre bũrũri wa Gadi? Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte andũ ake matũũre matũũra-inĩ makuo?”
2 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí; “nígbà tí èmi yóò mú kí a gbọ́ ìdágìrì ogun ní Rabba tí Ammoni; yóò sì di òkìtì ahoro, gbogbo ìlú tí ó yí i ká ni a ó jó níná. Nígbà náà ni Israẹli yóò lé wọn, àwọn tí ó ti lé e jáde,” ni Olúwa wí.
Jehova ekuuga atĩrĩ, “No rĩrĩ, matukũ nĩmarooka rĩrĩa ngoigithia mbu ya mbaara ya gũũkĩrĩra Raba kũu kwa andũ a Amoni; nakuo gũgaatuĩka hĩba ya mwanangĩko, natuo tũtũũra tũrĩa tũkũrigiicĩirie tũcinwo na mwaki. Hĩndĩ ĩyo nĩguo Isiraeli akaingata andũ arĩa maamũingatĩte,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
3 “Hu, ìwọ Heṣboni, nítorí Ai tí rún! Kígbe ẹ̀yin olùgbé Rabba! Ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀ kí ẹ sì ṣọ̀fọ̀. Ẹ sáré sókè sódò nínú ọgbà, nítorí Malkomu yóò lọ sí ìgbèkùn, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti ìjòyè rẹ̀.
“Wee Heshiboni, girĩka, nĩgũkorwo Ai nĩ kwanange! Rĩrai, inyuĩ mũtũũraga Raba! Mwĩhumbei nguo cia makũnia mũcakae; Tengʼerai ũũ na ũũ kũu thingo-inĩ ciakuo, nĩgũkorwo Moleku nĩegũtahwo atwarwo bũrũri ũngĩ, hamwe na athĩnjĩri-ngai na anene ake.
4 Èéṣe tí ìwọ fi ń ṣògo nínú àfonífojì rẹ, ṣògo nínú àfonífojì rẹ fún èso? Ẹ̀yin ọmọbìnrin Ammoni aláìṣòótọ́, ẹ gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ yín, ẹ sì wí pé, ‘Ta ni yóò kò mí lójú?’
Nĩ kĩĩ gĩtũmaga wĩrahĩre ituamba ciaku, ũkeraha nĩ ũndũ wa ituamba ciaku icio noru mũno? Wee mwarĩ ũyũ ũtarĩ mwĩhokeku, wee ũtũũrĩte wĩhokete ũtonga waku ũkiugaga atĩrĩ, ‘Nũũ ũngĩĩtharĩkĩra?’
5 Èmi yóò mu ẹ̀rù wá lórí rẹ láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tó yí ọ ká,” ni Olúwa, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Nĩngakũrehithĩria imakania kuuma kũrĩ arĩa othe makũrigiicĩirie,” nĩguo Mwathani ekuuga, o we Jehova Mwene-Hinya-Wothe. “Andũ othe anyu nĩmakaingatwo, na gũtikagĩa na mũndũ wa gũcookereria andũ acio mahurunjũkĩte.
6 “Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Gbogbo yín ni ó lé jáde, kò sì ṣí ẹnìkan tí yóò dá ìkólọ Ammoni padà,” ni Olúwa wí.
“No rĩrĩ, thuutha-inĩ nĩngacookia ũgaacĩru wa andũ a Amoni,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
7 Nípa Edomu. Èyí ní ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ṣe kò ha sí ọgbọ́n mọ́ ni Temani? Ṣé a ti ké ìmọ̀ràn kúrò ní ọ̀dọ̀ olóyè? Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ bí?
Ha ũhoro ũkoniĩ Edomu: Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ: “Kaĩ gũtarĩ na ũũgĩ ũtigarĩte kũu Temani? Kaĩ kĩrĩra gĩthirĩte harĩ andũ arĩa akuũku? Kaĩ ũũgĩ wao ũbuthĩte biũ?
8 Yípadà kí o sálọ, sá pamọ́ sínú ihò, ìwọ tí ó ń gbé ní Dedani, nítorí èmi yóò mú ibi wá sórí Esau, ní àkókò tí èmi ó bẹ̀ ẹ́ wò.
Garũrũkai mwĩthare, mũthiĩ mũkehithe thĩinĩ wa ngurunga iria ndiku, inyuĩ arĩa mũtũũraga kũu Dedani, tondũ nĩngarehithĩria Esaũ mwanangĩko rĩrĩa ngaamũherithia.
9 Tí àwọn tí ń ṣa èso bá tọ̀ ọ́ wá; ǹjẹ́ wọn kò ní fi èso díẹ̀ sílẹ̀? Tí olè bá wá ní òru; ǹjẹ́ wọn kò ní kó gbogbo ohun tí wọ́n bá fẹ́?
Agethi a thabibũ mangĩũka kũrĩ we-rĩ, githĩ to matigie tũthabibũ tũnini? Aici mangĩũka ũtukũ-rĩ, githĩ matingĩiya o indo iria imabatarĩtie?
10 Ṣùgbọ́n èmi yóò tu Esau sí ìhòhò, èmi ti fi ibi ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ hàn, nítorí kí o máa ba à fi ara rẹ pamọ́. Àwọn ọmọ rẹ, ẹbí rẹ àti àwọn ará ilé rẹ yóò parun. Wọn kò sì ní sí mọ́.
No rĩrĩ, niĩ nĩngaguũria Esaũ nguo atigwo njaga, nĩngaguũria ciĩhitho ciake, nĩguo ndakanacooke kuona gwa kwĩhitha. Ciana ciake, na andũ a nyũmba yao, na andũ a itũũra rĩake nĩmakaniinwo, na o nake ndagatigara.
11 Fi àwọn ọmọ aláìní baba sílẹ̀ èmi yóò dáàbò bo ẹ̀mí wọn. Àwọn opó rẹ gan an lè gbẹ́kẹ̀lé mi.”
Ndigĩrai ciana cianyu cia ngoriai; nĩngagitĩra mĩoyo yacio. Atumia anyu a ndigwa mũreke o nao manjĩhoke.”
12 Èyí ni ohun tí Olúwa wí bí ẹnikẹ́ni tí kò bá yẹ kí ó mu ago náà bá mú un, kí ló dé tí ìwọ yóò fi lọ láìjìyà? Ìwọ kò ní lọ láìjìyà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò mú un.
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Kũngĩkorwo arĩa mataagĩrĩirwo kũnyuĩra gĩkombe kĩu no nginya makĩnyuĩre-rĩ, wee ũngĩkĩaga kũherithio nĩkĩ? Ndũrĩ hĩndĩ ũtakaherithio, no rĩrĩ, no nginya ũgaakĩnyuĩra.”
13 Èmi fi ara mi búra ni Olúwa wí, wí pé, “Bosra yóò ba ayé ara rẹ̀ jẹ́. Yóò di ẹni ẹ̀gàn, ẹni èpè àti ẹni ègún, àti gbogbo ìlú rẹ̀ yóò di ìbàjẹ́ títí láé.”
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Ngwĩhĩta ngĩgwetaga rĩĩtwa rĩakwa, njuge atĩ Bozara gũgaatuĩka kũndũ kwanangĩku na kũrĩ magigi, gwa kũmenwo na gwa kũnyiitwo nĩ kĩrumi; namo matũũra makuo mothe magatũũra marĩ manangĩku nginya tene.”
14 Ní gbígbọ́, èmi ti gbọ́ ìró kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa, a rán ikọ̀ kan sí orílẹ̀-èdè pé, ẹ kó ara yín jọ, ẹ wá sórí rẹ̀, ẹ sì dìde láti jagun.
Nĩnjiguĩte ndũmĩrĩri kuuma kũrĩ Jehova: Atĩ nĩatũmire mũrekio athiĩ kũrĩ ndũrĩrĩ, agaciĩre atĩrĩ, “Ũnganai mũrĩtharĩkĩre! Arahũkai mũkarũe mbaara!”
15 “Ní báyìí, èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo; ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ènìyàn.
“Rĩu nĩngũkũnyiihia mũno gatagatĩ-inĩ ka ndũrĩrĩ, ndũme ũmenwo nĩ andũ.
16 Ìpayà tí ìwọ ti fà sínú ìgbéraga ọkàn rẹ sì ti tàn ọ́ jẹ; ìwọ tí ń gbé ní pàlàpálá àpáta, tí o jókòó lórí ìtẹ́ gíga síbẹ̀ o kọ́ ìtẹ́ rẹ ga gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ idì; láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá,” ni Olúwa wí.
Guoya ũrĩa ũtũmaga andũ magwĩtigĩre na mwĩtĩĩo wa ngoro yaku-rĩ, nĩikũheenetie, o wee ũtũũraga thĩinĩ wa ngurunga cia ndwaro cia mahiga, o na ũgaikaraga tũcũmbĩrĩ igũrũ twa karĩma. O na ũngĩgaaka itara igũrũ mũno ta cia nderi, ngaakũruta kuo, ngũharũrũkie,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
17 “Edomu yóò di ahoro gbogbo àwọn tí ń kọjá yóò jáyà, wọn ó sì fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà nítorí gbogbo ìpalára rẹ.
“Edomu gũgaatuĩka kũndũ gwa kũmakania; arĩa othe makaahĩtũkĩra kuo nĩmakamaka na makũnyũrũrie, nĩ ũndũ wa ũrĩa gũgaakorwo kwanangĩtwo.
18 Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká rẹ,” ní Olúwa wí. “Bẹ́ẹ̀ ni, kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé níbẹ̀; kò sì ní sí ènìyàn tí yóò tẹ̀dó síbẹ̀ mọ́.
O ta ũrĩa Sodomu na Gomora kwangʼaũranirio, hamwe na matũũra marĩa maariganĩtie namo, atĩ gũtirĩ mũndũ ũngĩtũũra kuo; gũtirĩ mũndũ ũgaacooka gũtũũra kuo,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
19 “Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Edomu kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
“O ta mũrũũthi ũũkĩte kuuma ihinga-inĩ cia Jorodani, ũgakinya ũrĩithio-inĩ ũrĩa mũnoru-rĩ, noguo ngaingata Edomu oime bũrũri-inĩ wake o rĩmwe. Nũũ ũthuurĩtwo wa kũruta wĩra ũcio nĩgeetha ndĩmũtue wa kũũrũgamĩrĩra? Nũũ ũngĩ ũhaana ta niĩ, na nũũ ũngĩhota kũngararia? Ningĩ nĩ mũrĩithi ũrĩkũ ũngĩkĩhota kũregana na niĩ?”
20 Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí Olúwa ní fún Edomu, ohun tí ó ní ní pàtàkì fún àwọn tí ń gbé ní Temani. Àwọn ọ̀dọ́ àgbò ni à ó lé jáde; pápá oko wọn ni yóò run nítorí wọn.
Nĩ ũndũ ũcio, ta thikĩrĩriai, mũigue ũrĩa Jehova athugundĩte gwĩka Edomu, o na ũrĩa atuĩte gwĩka arĩa matũũraga Temani: Arĩa anini thĩinĩ wa rũũru rũu rwa mbũri magaakururio matwarwo kũndũ kũraya; nĩakaniina ũrĩithio wao ũthire biũ nĩ ũndũ wao.
21 Ilẹ̀ yóò mì tìtì nípa ariwo ìṣubú wọn, a ó gbọ́ igbe wọn ní Òkun pupa.
Thĩ nĩĩkainainio nĩ mũrurumo wao makĩgũa thĩ; kayũ ga kĩrĩro kĩao gakaiguuo o nginya Iria Itune.
22 Wò ó! Ẹyẹ idì yóò gòkè fò wálẹ̀, yóò tẹ ìyẹ́ rẹ̀ lórí Bosra. Ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn ajagun Edomu yóò dàbí ọkàn obìnrin tí ń rọbí.
Atĩrĩrĩ! Nderi nĩĩkombũka na ĩcuuhũke, ĩtambũrũkĩtie mathagu mayo igũrũ rĩa Bozara. Mũthenya ũcio-rĩ, ngoro cia njamba iria irĩ hinya cia Edomu igaatuĩka ta ngoro ya mũndũ-wa-nja akĩrũmwo.
23 Nípa Damasku. “Inú Hamati àti Arpadi bàjẹ́ nítorí wọ́n gbọ́ ìròyìn búburú, ìjayà dé bá wọn, wọ́n sì dààmú bí omi Òkun.
Ha ũhoro ũkoniĩ Dameski: “Hamathu na Aripadi nĩamaku, nĩ ũndũ nĩmaiguĩte ndeto njũru. Nĩmorĩtwo nĩ hinya, makaagaaga ta maaĩ ma iria.
24 Damasku di aláìlera, ó pẹ̀yìndà láti sálọ, ìwárìrì sì dé bá a; ìbẹ̀rù àti ìrora dìímú, ìrora bí ti obìnrin tí ó wà ní ipò ìrọbí.
Dameski nĩrĩũrĩtwo nĩ hinya, nao andũ a rĩo makahũndũka meethare, rĩiyũrĩtwo nĩ kũinaina; andũ a rĩo manyiitĩtwo nĩ ruo rwa ngoro na kĩeha, ruo ta rwa mũndũ-wa-nja akĩrũmwo.
25 Kí ló dé tí ìlú olókìkí di ohun ìkọ̀sílẹ̀; ìlú tí mo dunnú sí.
Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte itũũra rĩrĩa rĩrĩ ngumo rĩage gũtiganĩrio, o itũũra rĩu rĩngenagia?
26 Lóòtítọ́, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ yóò ṣubú lójú pópó, gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ yóò pa ẹnu mọ́ ní ọjọ́ náà,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Ti-itherũ, aanake a rĩo nĩmakarũndwo barabara-inĩ ciarĩo; thigari ciakuo ciothe igaakirio ki mũthenya ũcio,” ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga.
27 “Èmi yóò fi iná sí odi Damasku, yóò sì jó gbọ̀ngàn Beni-Hadadi run.”
“Nĩngacina thingo cia Dameski; naguo mwaki ũcio nĩũgaacina ciĩgitĩro cia Beni-Hadadi.”
28 Nípa ìlú Kedari àti ìjọba Hasori èyí ti Nebukadnessari ọba Babeli dojú ìjà kọ, èyí ni ohun tí Olúwa sọ, “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ ìlú Kedari, kí o sì pa àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn run.
Ũhoro ũkoniĩ Kedari, o na mothamaki ma Hazoru, marĩa Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni aatharĩkĩire: Jehova ekuuga atĩrĩ: “Arahũkai mũtharĩkĩre Kedari, na mũniine andũ acio a mwena wa Irathĩro.
29 Àgọ́ wọn àti agbo àgùntàn wọn ni wọn ó kó lọ; àgọ́ wọn yóò di ìṣínípò padà pẹ̀lú gbogbo ẹrù àti ìbákasẹ wọn. Àwọn ènìyàn yóò ké sórí wọ́n pé, ‘Ẹ̀rù yí káàkiri!’
Hema ciao na ndũũru ciao cia mbũri nĩigatahwo; ciandarũa ciao nĩigakuuo, hamwe na indo ciao ciothe, na ngamĩĩra ciao ciothe. Andũ nĩmakanĩrĩra, mameere atĩrĩ, ‘Kĩmako kĩnene kiumanĩte na mĩena yothe!’
30 “Sálọ kíákíá! Fi ara pamọ́ sí ibi jíjìn, ẹ̀yin olùgbé Hasori,” ni Olúwa wí. “Nebukadnessari ọba Babeli ti dojú ìjà kọ ọ́.
“Mwĩtharei narua! Ikarai thĩinĩ wa ngurunga iria ndiku, inyuĩ mũtũũraga kũu Hazoru. Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni nĩaciirĩire kũmũũkĩrĩra; nĩathugundĩte ũrĩa ekũmũũkĩrĩra,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
31 “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ orílẹ̀-èdè tí ó wà nínú ìrọ̀rùn, èyí tí ó gbé ní àìléwu,” ní Olúwa wí. “Orílẹ̀-èdè tí kò ní odi tàbí irin, àwọn ènìyàn rẹ̀ ń dágbé.
“Arahũkai mũtharĩkĩre rũrĩrĩ rũu rũtũũrĩte rũgaacĩire na rũhooreire, o rũu rũtũũrĩte rũrĩ na thayũ, rũrĩrĩ rũteehingagĩra na ihingo kana rũkeirigĩra na igera; andũ aruo matũũraga marĩ oiki,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
32 Àwọn ìbákasẹ á di ẹrù àti àwọn ẹran ọ̀sìn, wọ́n á di ìkógun. Èmi yóò tú àwọn tí ó wà ní òkèèrè sí inú afẹ́fẹ́. Èmi yóò sì mú ibi wá sí àyíká gbogbo,” báyìí ní Olúwa wí.
“Ngamĩĩra ciao igaatuĩka cia gũtahwo, nacio ndũũru icio ciao nyingĩ cia ngʼombe ituĩke cia ndaho. Arĩa marĩ kũndũ kũraya nĩngamahurunjĩra mĩena yothe ĩrĩa yumaga rũhuho. na nĩngamarehithĩria mwanangĩko kuuma mĩena yothe,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
33 “Hasori yóò di ibi ìdọdẹ àwọn akátá, ibi ìkọ̀sílẹ̀ ayérayé, kò sí ẹni tí yóò gbé ní ibẹ̀.”
“Hazoru gũgaatuĩka ũtũũro wa mbwe, gũtũũre gũkirĩte ihooru nginya tene. Gũtirĩ mũndũ ũgaatũũra kuo; gũtirĩ mũndũ ũgaikara kuo.”
34 Èyí ní ọ̀rọ̀ Olúwa èyí tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa Elamu ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekiah ọba Juda.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩrĩa yakinyĩrĩire Jeremia ũcio mũnabii ĩkoniĩ Elamu, o kĩambĩrĩria-inĩ kĩa wathani wa Zedekia mũthamaki wa Juda:
35 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “Wò ó, èmi yóò fọ́ ìtẹ̀gùn Elamu, ẹni tí wọ́n sinmi lé nípa agbára.
Ũũ nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga: “Atĩrĩrĩ, nĩngoinanga ũta wa Elamu, ũrĩa arĩ guo kĩhumo kĩa hinya wao.
36 Èmi yóò mú kí afẹ́fẹ́ orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé lòdì sí Elamu. Èmi yóò tú wọn ká sí ìpín afẹ́fẹ́ mẹ́rin àti pé, kò sí orílẹ̀-èdè tí ilẹ̀ àjèjì Elamu kò ní lọ.
Nĩngarehithĩria andũ a Elamu huho iria inya ciumaga mĩena ĩrĩa ĩna ya igũrũ; ngaamahurunjĩra na kũu huho icio inya ciumaga, na gũtirĩ rũrĩrĩ o na rũmwe andũ acio aingate a Elamu matakoorĩra.
37 Èmi yóò kẹ́gàn Elamu níwájú àwọn ọ̀tá wọn, àti níwájú àwọn tí wọ́n ń wá ẹ̀mí wọn, Èmi yóò mú ibi wá sí orí wọn, àní, ìbínú gbígbóná mi,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Èmi yóò lé wọn pẹ̀lú idà, di ìgbà tí èmi yóò rẹ́yìn wọn.
Nĩngahehenja Elamu maitho-inĩ ma thũ ciao, marĩ o mbere ya andũ arĩa macaragia kũmaruta muoyo; nĩngamarehithĩria mwanangĩko, o na marakara makwa mahiũ,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “Ngaamatengʼeria na rũhiũ rwa njora nginya ndĩmaniine biũ.
38 Èmi yóò sì gbé ìtẹ́ mi kalẹ̀ ní Elamu, èmí yóò sì pa ọba wọn àti ìjòyè wọn run,” báyìí ni Olúwa wí.
Nĩngaiga gĩtĩ gĩakwa kĩa ũnene kũu Elamu, na niine mũthamaki wakuo o na anene akuo,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
39 “Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ Elamu padà láìpẹ́ ọjọ́,” báyìí ni Olúwa wí.
“No rĩrĩ, nĩngacookia ũgaacĩru wa Elamu matukũ-inĩ marĩa magooka,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.

< Jeremiah 49 >