< Jeremiah 47 >

1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tó tọ wòlíì Jeremiah wá nípa àwọn Filistini, kí ó tó di pé Farao dojúkọ Gasa.
Ko te kupu a Ihowa i puta mai ki a Heremaia poropiti mo nga Pirihitini i te mea kahore ano a Parao i patu noa i Kaha.
2 Báyìí ni Olúwa wí: “Wo bí omi ti ń ru sókè ní àríwá, wọn ó di odò tí ń bo bèbè mọ́lẹ̀. Wọn kò ní borí ilẹ̀ àti ohun gbogbo tó wà lórí rẹ̀, ìlú àti àwọn tó ń gbé nínú wọn. Àwọn ènìyàn yóò kígbe, gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà yóò hu
Ko te kupu tenei a Ihowa: Nana, te puta mai nei nga wai i te raki, ka meinga hei waipuke e ngawha ana, a ka pokia te whenua me ona mea katoa, te pa me nga tangata e noho ana i roto: a ka hamama nga tangata, ka aue hoki nga tangata katoa o te when ua.
3 nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ìró títẹ̀lé pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ariwo kẹ̀kẹ́ ogun ọ̀tá ńlá àti iye kẹ̀kẹ́ wọn. Àwọn baba kò ní lè ran àwọn ọmọ lọ́wọ́; ọwọ́ wọn yóò kákò.
Hei te haruru o te takahi o nga paua o ona hoiho kaha, hei te rorohu o ona hariata, hei te ngaehe o ona wira, kore iho nga matua e tahuri ki muri ki a ratou tamariki i te ngoikore hoki o nga ringa;
4 Nítorí tí ọjọ́ náà ti pé láti pa àwọn Filistini run, kí a sì mú àwọn tí ó là tí ó lè ran Tire àti Sidoni lọ́wọ́ kúrò. Olúwa ti ṣetán láti pa Filistini run, àwọn tí ó kù ní agbègbè Kafitori.
Na, mo te ra e haere mai nei, e pahuatia ai nga Pirihitini katoa, e hatepea atu ai i Taira, i Hairona nga kaiawhina katoa e toe nei: ka pahuatia hoki e Ihowa nga Pirihitini, nga morehu o te motu, o Kapatoro.
5 Gasa yóò fá irun orí rẹ̀ nínú ọ̀fọ̀. A ó pa Aṣkeloni lẹ́nu mọ́; ìyókù ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, ìwọ yóò ti sá ara rẹ lọ́gbẹ́ pẹ́ tó?
Kua tae te pakira ki runga ki Kaha; kua whakamotitia a Ahakerono, me te toenga ano o to ratou awaawa: kia pehea te roa o tau haehae i a koe?
6 “Ẹ̀yin kígbe, ‘Yé è, idà Olúwa, yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò sinmi? Padà sínú àkọ̀ rẹ; sinmi kí o sì dákẹ́ jẹ́ẹ́.’
E te hoari a Ihowa, kia pehea te roa ka ata takoto ai koe? hoki atu ki roto ki tou kopaki: okioki, kati hoki tau.
7 Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi, nígbà tí Olúwa ti pàṣẹ fún un, nígbà tí ó ti pa á láṣẹ láti dojúkọ Aṣkeloni àti agbègbè rẹ̀.”
Me pehea koe e ata takoto ai, kua hoatu nei hoki e Ihowa he whakahau ki a koe? he he mo Ahakerono, mo te tahatika hoki o te moana, kua whakaritea e ia ki reira.

< Jeremiah 47 >