< Jeremiah 47 >

1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tó tọ wòlíì Jeremiah wá nípa àwọn Filistini, kí ó tó di pé Farao dojúkọ Gasa.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩrĩa yakinyĩrĩire Jeremia ũrĩa mũnabii, ĩkoniĩ andũ a Filisti, Firaũni atanatharĩkĩra Gaza:
2 Báyìí ni Olúwa wí: “Wo bí omi ti ń ru sókè ní àríwá, wọn ó di odò tí ń bo bèbè mọ́lẹ̀. Wọn kò ní borí ilẹ̀ àti ohun gbogbo tó wà lórí rẹ̀, ìlú àti àwọn tó ń gbé nínú wọn. Àwọn ènìyàn yóò kígbe, gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà yóò hu
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Ta rora ũrĩa kĩguũ kĩa maaĩ kĩroima na kũu mwena wa gathigathini; nĩgĩgũtuĩka ta rũũĩ rũiyũru mũno, rũkoina. Megũtherera moinĩre bũrũri na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ kuo, na moinĩre matũũra-inĩ na arĩa matũũraga kuo. Andũ nĩmagakaya; arĩa othe maikaraga bũrũri ũcio makaarĩra na magirĩke,
3 nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ìró títẹ̀lé pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ariwo kẹ̀kẹ́ ogun ọ̀tá ńlá àti iye kẹ̀kẹ́ wọn. Àwọn baba kò ní lè ran àwọn ọmọ lọ́wọ́; ọwọ́ wọn yóò kákò.
maigua mũkubio wa mbarathi igĩtengʼera, na inegene rĩa ngaari cia ita cia thũ ciao, o na mũrurumo wa magũrũ ma ngaari icio. Maithe ma ciana matikehũgũra mateithie ciana ciao; moko mao magaikara o ũguo maregerete.
4 Nítorí tí ọjọ́ náà ti pé láti pa àwọn Filistini run, kí a sì mú àwọn tí ó là tí ó lè ran Tire àti Sidoni lọ́wọ́ kúrò. Olúwa ti ṣetán láti pa Filistini run, àwọn tí ó kù ní agbègbè Kafitori.
Nĩgũkorwo mũthenya nĩmũkinyu wa kũniina andũ a Filisti othe, na wa kweheria matigari mothe ma andũ arĩa mangĩteithia Turo na Sidoni. Jehova arĩ hakuhĩ kwananga andũ a Filisti, acio maatigaire kuuma hũgũrũrũ-inĩ cia Kafitori.
5 Gasa yóò fá irun orí rẹ̀ nínú ọ̀fọ̀. A ó pa Aṣkeloni lẹ́nu mọ́; ìyókù ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, ìwọ yóò ti sá ara rẹ lọ́gbẹ́ pẹ́ tó?
Andũ a Gaza makeenjwo njuĩrĩ macakae; Ashikeloni nakuo gũgaakira ki. Atĩrĩrĩ, inyuĩ matigari maya mũrĩ kũu werũ-inĩ, mũgũtũũra mwĩtemangaga nginya-rĩ?
6 “Ẹ̀yin kígbe, ‘Yé è, idà Olúwa, yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò sinmi? Padà sínú àkọ̀ rẹ; sinmi kí o sì dákẹ́ jẹ́ẹ́.’
“Mũrarĩra mũkooria atĩrĩ, ‘Wee, rũhiũ rwa njora rwa Jehova-rĩ, ũgũthiĩ na mbere nginya rĩ ũngĩkaahurũka? Wĩcookie njora-inĩ; hurũka na ũkire o ro ũguo.’
7 Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi, nígbà tí Olúwa ti pàṣẹ fún un, nígbà tí ó ti pa á láṣẹ láti dojúkọ Aṣkeloni àti agbègbè rẹ̀.”
No rĩrĩ, rũngĩkĩhuurũka atĩa, o rĩrĩa arĩ Jehova ũrwathĩte, o rĩrĩa arwĩrĩte rũtharĩkĩre Ashikeloni, o na kũu ndwere-inĩ cia iria?”

< Jeremiah 47 >