< Jeremiah 46 >

1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa àwọn Orílẹ̀-èdè.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩkoniĩ ndũrĩrĩ ĩrĩa yakinyĩrĩire mũnabii Jeremia:
2 Nípa Ejibiti. Èyí ni ọ̀rọ̀ nípa àwọn ọmọ-ogun Farao Neko ọba Ejibiti ẹni tí a borí rẹ̀ ní Karkemiṣi, ní odò Eufurate láti ọwọ́ Nebukadnessari ọba Babeli ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda:
Ha ũhoro ũkoniĩ bũrũri wa Misiri: Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ya gũũkĩrĩra mbũtũ cia ita cia Firaũni Neko, mũthamaki wa bũrũri wa Misiri, iria ciahooteirwo kũu Karikemishi, Rũũĩ-inĩ rwa Farati, nĩ Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni, mwaka-inĩ wa kana wa wathani wa Jehoiakimu mũrũ wa Josia, mũthamaki wa Juda:
3 “Ẹ múra àpáta, èyí tí ó tóbi, àti èyí tí ó kéré, kí ẹ sì súnmọ́ ojú ìjà!
“Thagathagai ngo cianyu, iria nene na tũrĩa tũnini, mũthiĩ mbaara-inĩ!
4 Ẹ di ẹṣin ní gàárì, kí ẹ sì gùn ún. Ẹ dúró lẹ́sẹẹsẹ pẹ̀lú àṣíborí yín! Ẹ dán ọ̀kọ̀ yín, kí ẹ sì wọ ẹ̀wù irin.
Tandĩkai mbarathi, mũcihaice! Rũgamai o mũndũ handũ hake mwĩkĩrĩte ngũbia cia igera! Kumuthai matimũ manyu, na mwĩhumbe nguo cianyu cia mbaara.
5 Kí ni nǹkan tí mo tún rí? Wọ́n bẹ̀rù, wọ́n sì ń padà sẹ́yìn, wọ́n ti ṣẹ́gun àwọn jagunjagun. Wọ́n sá, wọn kò sì bojú wẹ̀yìn, ìbẹ̀rù sì wà níbi gbogbo,” ni Olúwa wí.
Nĩ kĩĩ ndĩrona? Nĩamaku mũno, nĩmaracooka na thuutha, njamba ciao nĩndoorie. Nĩmetharĩte na ihenya matekwĩhũgũra, na kũrĩ na itua-nda mĩena yothe,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
6 “Ẹni tí ó yára kì yóò le sálọ, tàbí alágbára kò ní lè sá àsálà. Ní àríwá ní ibi odò Eufurate wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò sì ṣubú.
“Arĩa marĩ ihenya matingĩhota kũũra, kana arĩa marĩ hinya meethare. Mwena wa gathigathini kũu Rũũĩ-inĩ rwa Farati mahĩngagwo makagũa.
7 “Ta ni èyí tí ó gòkè wá bí odò Ejibiti, tí omi rẹ̀ ń ru gẹ́gẹ́ bí odò wọ̀n-ọn-nì?
“Nũũ ũyũ wĩyambararĩtie ta Rũũĩ rwa Nili, akaambarara ta njũũĩ irĩ na ndiihũ cia maaĩ?
8 Ejibiti dìde bí odò náà, bí omi odò tí ń ru. Ó sì wí pé, ‘Èmi yóò dìde, n ó sì bo gbogbo ilẹ̀ ayé.’ Èmi yóò pa ìlú àti àwọn ènìyàn rẹ̀ run.
Bũrũri wa Misiri wĩyambararĩtie ta Rũũĩ rwa Nili, ũkambarara ta njũũĩ irĩ na ndiihũ cia maaĩ. Oigaga atĩrĩ, ‘Nĩngũiyũra nginya humbĩre thĩ; nĩngwananga matũũra marĩa manene na andũ arĩa matũũraga kuo.’
9 Ẹ gòkè wá ẹ̀yin ẹṣin, ẹ sì sáré kíkankíkan ẹ̀yin kẹ̀kẹ́. Kí àwọn alágbára túbọ̀ tẹ̀síwájú, àwọn ará Kuṣi àti àwọn ará Puti tí ń di asà mú; àti àwọn ará Lidia tí ń fa ọrun.
Guthũkai, inyuĩ mbarathi ici! Matengʼeriei hatarĩ itherũ, inyuĩ mũtwarithagia ngaari cia ita. Umagarai, inyuĩ njamba ici cia ita: inyuĩ andũ a Kushi na a Putu, inyuĩ mũũĩ kũrũmia ngo, na inyuĩ andũ a Ludu, inyuĩ mũgeetaga ũta.
10 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà jẹ́ ti Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ọjọ́ ìgbẹ̀san, ìgbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀. Idà yóò sì jẹ́ títí yóò fi ní ìtẹ́lọ́rùn, títí yóò fi pa òǹgbẹ rẹ̀ rẹ́ pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀. Nítorí pé Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò rú ẹbọ ní ilẹ̀ gúúsù ní odò Eufurate.
No rĩrĩ, mũthenya ũcio nĩ wa Mwathani, o we Jehova Mwene-Hinya-Wothe: nĩ mũthenya wa kwĩrĩhĩria, erĩhĩrie harĩ thũ ciake. Rũhiũ rwa njora rũkaarĩa nginya rũhũũne, rũkaanyua thakame yao nginya rũnyootoke. Nĩgũkorwo Mwathani, o we Jehova Mwene-Hinya-Wothe, nĩakarutĩra igongona kũu bũrũri wa mwena wa gathigathini gũkuhĩ na Rũũĩ rwa Farati.
11 “Gòkè lọ sí Gileadi, kí o sì mú ìkunra, ìwọ wúńdíá ọmọbìnrin Ejibiti. Ṣùgbọ́n ní asán ni ìwọ ń lo oògùn, kì yóò sí ìwòsàn fún ọ.
“Ambata, ũkinye Gileadi, ũgĩĩre ndawa, wee Mũirĩtu Gathirange, Mwarĩ wa bũrũri wa Misiri. No rĩrĩ, ũingĩhagia ndawa icio mũno, o tũhũ; gũtirĩ ingĩkũhonia.
12 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ nípa ìtìjú rẹ, igbe rẹ yóò kún gbogbo ayé. Jagunjagun yóò máa ṣubú lu ara wọn lórí rẹ, àwọn méjèèjì yóò sì jọ ṣubú papọ̀.”
Ndũrĩrĩ nĩikaigua ũhoro wa gũconorithio gwaku; kĩrĩro gĩaku gĩkaaiyũra thĩ. Njamba ĩkaahĩngagwo nĩ ĩrĩa ĩngĩ; cierĩ ikaagũa thĩ hamwe.”
13 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó bá Jeremiah wòlíì nì sọ nípa wíwá Nebukadnessari ọba Babeli láti lọ dojú ìjà kọ Ejibiti:
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ĩrĩa Jehova aaheire Jeremia ũcio mũnabii ĩkoniĩ gũũka kwa Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni, gũtharĩkĩra bũrũri wa Misiri:
14 “Kéde èyí ní Ejibiti, sì sọ ọ́ ní Migdoli, sọ ọ́ ní Memfisi àti Tafanesi: ‘Dúró sí ààyè rẹ kí o sì múra sílẹ̀, nítorí pé idà náà ń pa àwọn tí ó yí ọ ká.’
“Anĩrĩrai ũhoro ũyũ bũrũri-inĩ wa Misiri, na mũũhunjie kũu Migidoli; ningĩ mũũhunjanĩrie kũu Nofu na Tahapanahesi: ‘Rũgamai harĩa hamwagĩrĩire na mwĩhaarĩrie, nĩgũkorwo rũhiũ rwa njora nĩrũrarĩa arĩa mamũthiũrũrũkĩirie.’
15 Èéṣe tí àwọn akọni rẹ fi ṣubú? Wọn kò ní le dìde dúró, nítorí Olúwa yóò tì wọ́n ṣubú.
Nĩ kĩĩ gĩgũtũma njamba cianyu cia ita ciaraganio thĩ? Itingĩhota gwĩtiiria, nĩgũkorwo Jehova nĩwe ũgaacitindĩka acigũithie thĩ.
16 Wọn yóò máa ṣubú léraléra wọn yóò máa ṣubú lu ara wọn. Wọn yóò sọ wí pé, ‘Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a padà sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn wa àti ilẹ̀ ìbí wa, kúrò níbi idà àwọn aninilára.’
Nĩikahĩngwo rĩngĩ na rĩngĩ; ikaagũanĩra o mũndũ igũrũ rĩa ũrĩa ũngĩ. Ikoiga atĩrĩ, ‘Ũkĩrai, nĩtũcookei kũrĩ andũ aitũ, kũrĩa twaciarĩirwo, tweherere rũhiũ rũrũ rwa njora rwa mũtũhatĩrĩria.’
17 Níbẹ̀ ni wọn ó kígbe pé, ‘Ariwo lásán ni Farao ọba Ejibiti pa, ó ti sọ àǹfààní rẹ̀ nù.’
Marĩ kũu makaanagĩrĩra, makoiga atĩrĩ, ‘Firaũni mũthamaki wa bũrũri wa Misiri, nĩ inegene rĩa tũhũ; nĩorirwo nĩ mweke wake.’”
18 “Bí èmi ti wà láààyè,” ni ọba, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Nítòótọ́ gẹ́gẹ́ bí Tabori láàrín àwọn òkè àti gẹ́gẹ́ bi Karmeli lẹ́bàá Òkun bẹ́ẹ̀ ni òun yóò dé.
Mũthamaki, o we ũrĩa wĩtagwo Jehova Mwene-Hinya-Wothe, ekuuga atĩrĩ, “Ti-itherũ o ta ũrĩa niĩ ndũũraga muoyo-rĩ, nĩ kũrĩ mũndũ ũroka, ũgaakorwo ahaana ta Kĩrĩma gĩa Taboru kĩrĩ gatagatĩ-inĩ ka irĩma iria ingĩ, o na ta ũrĩa Kĩrĩma gĩa Karimeli kĩhaana kĩrĩ hakuhĩ na iria.
19 Ìwọ, ọmọbìnrin ti ń gbé Ejibiti pèsè ohun èlò ìrìnàjò fún ara rẹ nítorí Memfisi yóò di ahoro a ó sì fi jóná, láìní olùgbé.
Oha mĩrigo yaku ya gũthiĩ nayo kũrĩa ũgaatahwo, ũtwarwo, wee ũtũũraga bũrũri wa Misiri, nĩgũkorwo Nofu gũkaanangwo, kwage kĩndũ, o na gũkire ihooru, gũtarĩ mũndũ wa gũgũtũũra.
20 “Ẹgbọrọ abo màlúù tó lẹ́wà ní Ejibiti ṣùgbọ́n eṣinṣin ìparun dé, ó dé láti àríwá.
“Bũrũri wa Misiri ũhaana moori njega mũno, no rĩrĩ, nĩ harĩ mbogo kanyarare ĩrooka kũmĩũkĩrĩra, yumĩte mwena wa gathigathini.
21 Àwọn jagunjagun rẹ̀ dàbí àbọ́pa akọ màlúù. Àwọn pẹ̀lú yóò yípadà, wọn ó sì jùmọ̀ sá, wọn kò ní le dúró, nítorí tí ọjọ́ ibi ń bọ̀ lórí wọn àsìkò láti jẹ wọ́n ní ìyà.
Thigari cia mũcaara iria irĩ kuo ihaana ta njaũ cia gĩcegũ. O nao nĩmakagarũrũka more marĩ hamwe, matikahota gwĩtiiria, nĩgũkorwo mũthenya wa mwanangĩko nĩũkamakorerera, na nĩrĩo ihinda rĩao rĩa kũherithio.
22 Ejibiti yóò pòṣé bí ejò tí ń sá bí ọmọ-ogun ṣe ń tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú agbára. Wọn ó tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú àáké, gẹ́gẹ́ bí i ti agégi.
Mũrurumo wa andũ a Misiri ũgaatuĩka ta wa nyoka rĩrĩa ĩrethara, rĩrĩa thũ ĩgooka ĩrĩ na hinya; magaagũũkĩrĩra na mathanwa, o ta andũ maratema mĩtĩ.”
23 Wọn o gé igbó rẹ̀ lulẹ̀,” ni Olúwa wí, “nítorí ti a kò le rídìí rẹ̀. Nítorí pé wọ́n pọ̀ ju ẹlẹ́ǹgà lọ, wọ́n sì jẹ́ àìníye.
Jehova ekuuga atĩrĩ, “Nĩmagatema mũtitũ wakuo, o na ũrĩ mũtumanu ũguo. Tondũ nĩ andũ aingĩ mũno gũkĩra ngigĩ, na matingĩtarĩka.
24 A ó dójútì ọmọbìnrin Ejibiti, a ó fà á lé ọwọ́ àwọn ènìyàn àríwá.”
Mwarĩ ũcio wa bũrũri wa Misiri nĩagaconorithio, akaanenganĩrwo kũrĩ andũ a mwena wa gathigathini.”
25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí pé: “Èmi yóò rọ̀jò ìyà mi sórí Amoni òrìṣà Tebesi, sórí Farao, sórí Ejibiti àti àwọn òrìṣà rẹ̀ àti sórí àwọn ọba rẹ̀ àti sórí àwọn tó gbẹ́kẹ̀lé Farao.
Jehova Mwene-Hinya-Wothe, Ngai wa Isiraeli, ekuuga atĩrĩ: “Ndĩ hakuhĩ kũherithia Amoni ngai ya Thebesi, na Firaũni, na bũrũri wa Misiri na ngai ciakuo, na athamaki akuo, na arĩa othe mehokaga Firaũni.
26 Èmi ó sì fi wọ́n lé àwọn tó wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́, lé Nebukadnessari ọba Babeli, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Ejibiti yóò sì di gbígbé bí i ti àtijọ́,” ni Olúwa wí.
Nĩngamaneana kũrĩ andũ arĩa mendaga kũmaruta muoyo, ndĩmaneane kũrĩ Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni na anene ake. No rĩrĩ, thuutha-inĩ bũrũri wa Misiri nĩgũgatũũrwo nĩ andũ rĩngĩ o ta tene,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
27 “Má bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi, má fòyà, ìwọ Israẹli. Dájúdájú èmi ó gbà ọ́ láti ọ̀nà jíjìn, àwọn ọmọ ọmọ rẹ ní ilẹ̀ ìgbèkùn. Jakọbu yóò tún ní àlàáfíà àti ààbò, kò sì ṣí ẹni tí yóò dẹ́rùbà á.
“Tiga gwĩtigĩra, wee Jakubu ndungata yakwa: o nawe Isiraeli-rĩ, ndũkamake. Ti-itherũ nĩngakũhonokia ngũrutĩte kũndũ kũraya, njiaro ciaku ciume bũrũri ũrĩa ciatahirwo igĩtwarwo. Jakubu nĩagakorwo na thayũ na ũgitĩri rĩngĩ, na gũtirĩ mũndũ ũgaatũma acooke gwĩtigĩra.”
28 Má bẹ̀rù, Jakọbu ìránṣẹ́ mi, nítorí pé mo wà pẹ̀lú rẹ,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Bí mo tilẹ̀ pa gbogbo orílẹ̀-èdè run, láàrín àwọn tí mo fọ́n yín ká sí. Èmi kò ní run yín tán. Èmi yóò jẹ ọ́ ní ìyà lórí òdodo, èmi kí yóò jọ̀wọ́ rẹ lọ́wọ́ lọ láìjẹ ọ́ ní yà.”
Jehova ekuuga atĩrĩ “Tiga gwĩtigĩra, wee Jakubu ndungata yakwa, nĩgũkorwo ndĩ hamwe nawe. o na ingĩkaniinũkia ndũrĩrĩ ciothe kũrĩa ndarekire mũtwarwo mũrĩ atahe-rĩ, wee ndigakũniina biũ, no rĩrĩ, nĩngakũherithia na kĩhooto; ndigakũreka ũthiĩ o ũguo ũtaherithĩtio.”

< Jeremiah 46 >