< Jeremiah 4 >
1 “Tí ìwọ yóò bá yí padà, ìwọ Israẹli, padà tọ̀ mí wá,” ni Olúwa wí. “Tí ìwọ yóò bá sì mú ìríra rẹ kúrò níwájú mi, ìwọ kí ó sì rìn kiri.
“Atĩrĩrĩ wee Isiraeli, ũngĩkorwo nĩũgũcooka-rĩ, njookerera,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “Ũngĩeheria mĩhianano ĩyo yaku ĩrĩ magigi, na ũtige gũcooka kũũrũũra rĩngĩ,
2 Tí ó bá jẹ́ lóòtítọ́ àti òdodo ni ìwọ búra. Nítòótọ́ bí Olúwa ti wà láààyè, nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò di alábùkún fún nípasẹ̀ rẹ, àti nínú rẹ̀ ni wọn yóò ṣògo.”
ningĩ ũngĩrũmia ũhoro wa ma, na ũtuanĩri ciira wa kĩhooto, na wa ũthingu, na wĩhĩte ũkiugaga atĩrĩ, ‘Ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo,’ hĩndĩ ĩyo ndũrĩrĩ nĩikarathimwo nĩwe, na thĩinĩ wake nĩikaagĩa na riiri.”
3 Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu: “Hú gbogbo ilẹ̀ tí ẹ kò lò rí, kí o má sì ṣe gbìn sáàrín ẹ̀gún.
Atĩrĩrĩ, Jehova areera andũ a Juda, o na andũ a Jerusalemu ũũ: “Cimbai mĩgũnda yanyu ĩrĩa ĩrĩ ngamba, na mũtikahaande irio mĩigua-inĩ.
4 Kọ ara rẹ ní ilà sí Olúwa, kọ ọkàn rẹ ní ilà, ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìbínú mi yóò ru jáde yóò sì jó bí iná, nítorí ibi tí o ti ṣe kì yóò sí ẹni tí yóò pa á.
Mwĩamũrĩrei Jehova, na ũndũ wa kũruithia ngoro cianyu inyuĩ andũ aya a Juda, na inyuĩ mũtũũraga Jerusalemu, nĩgeetha mangʼũrĩ makwa matigaakane ta mwaki, nĩ ũndũ wa ũũru ũrĩa mwĩkĩte, maakane mage mũndũ wa kũmahoria.
5 “Kéde ní Juda, kí o sì polongo ní Jerusalẹmu, kí o sì wí pé: ‘Fun fèrè káàkiri gbogbo ilẹ̀!’ Kí o sì kígbe: ‘Kó ara jọ pọ̀! Jẹ́ kí a sálọ sí ìlú olódi.’
“Anĩrĩrai kũu Juda, na mũhunjie ũhoro kũu Jerusalemu, muuge ũũ: ‘Huhai tũrumbeta bũrũri-inĩ guothe!’ Anĩrĩrai na kayũ muuge atĩrĩ: ‘Mwĩcookanĩrĩriei! Nĩtũũrĩrei matũũra-inĩ marĩa manene mairigĩre!’
6 Fi àmì láti sálọ sí Sioni hàn, sálọ fún ààbò láìsí ìdádúró. Nítorí èmi ó mú àjálù láti àríwá wá, àní ìparun tí ó burú jọjọ.”
Haandai bendera mũthiĩ mwerekeire Zayuni! Mwĩtharei narua mwĩhonokie! Nĩgũkorwo nĩndĩrarehithia mwanangĩko uumĩte mwena wa gathigathini, o na kũniinanwo kũnene.”
7 Kìnnìún ti sá jáde láti inú ibùgbé rẹ̀, apanirun orílẹ̀-èdè sì ti jáde. Ó ti fi ààyè rẹ̀ sílẹ̀ láti ba ilẹ̀ rẹ̀ jẹ́. Ìlú rẹ yóò di ahoro láìsí olùgbé.
Mũrũũthi nĩumĩte kĩmamo-inĩ kĩaguo; mũniinani wa kũniina ndũrĩrĩ nĩoimagarĩte. Oimĩte gwake oke aanange bũrũri waku. Matũũra maku makaanangĩka, mage mũndũ wa gũtũũra kuo.
8 Nítorí náà, gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀ káàánú kí o sì pohùnréré ẹkún, nítorí ìbínú ńlá Olúwa kò tí ì kúrò lórí wa.
Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, mwĩhumbei nguo cia makũnia, cakayai na mũrĩre, nĩ ũndũ tũtirĩ tũrehererwo nĩ mangʼũrĩ macio mahiũ ma Jehova.
9 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí pé, “Àwọn ọba àti ìjòyè yóò pàdánù ẹ̀mí wọn, àwọn àlùfáà yóò wárìrì, àwọn wòlíì yóò sì fòyà.”
Jehova ekuuga atĩrĩ, “Mũthenya ũcio-rĩ, mũthamaki na anene ake nĩmagakua ngoro, nao athĩnjĩri-Ngai nĩmakagegeara, nao anabii mamake.”
10 Nígbà náà ni mo sì wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè, báwo ni ìwọ ti ṣe tan àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti Jerusalẹmu jẹ nípa sísọ wí pé, ‘Ìwọ yóò wà ní àlàáfíà,’ nígbà tí o jẹ́ wí pé idà wà ní ọ̀fun wa.”
Hĩndĩ ĩyo ngiuga atĩrĩ: “Hĩ! Mwathani Jehova, ti-itherũ nĩ ta ũkĩheenetie andũ aya biũ, o na ũkaheenia Jerusalemu, nĩ ũndũ wa kũmeera atĩrĩ, ‘Nĩmũkaagĩa na thayũ,’ o rĩrĩa tũigĩrĩirwo rũhiũ rwa njora mĩmero.”
11 Nígbà náà ni a ó sọ fún Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn pé, “Ẹ̀fúùfù líle láti aṣálẹ̀ fẹ́ lu àwọn ènìyàn mi, kì í ṣe láti sọ di mímọ́.
Ihinda rĩu andũ aya o hamwe na Jerusalemu nĩmakeerwo atĩrĩ, “Rũhuho rũhiũ ruumĩte kũndũ kũrĩa gũtarĩ kĩndũ kũu gũtũũgĩru werũ-inĩ nĩrũkahurutana rwerekeire kũrĩ andũ akwa, no rĩrĩ, ti ta rũrĩa rwa kũhuha irio kana rwa gũcitheria;
12 Ẹ̀fúùfù líle tí ó wá láti ọ̀dọ̀ mi. Báyìí mo kéde ìdájọ́ mi lórí wọn.”
nĩ rũhuho rũrĩ na hinya kũrĩ rũu ruumĩte kũrĩ niĩ. Rĩu nĩngũmatuĩra matuĩro ma ciira.”
13 Wò ó! O ń bọ̀ bí ìkùùkuu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ sì wá bí ìjì líle ẹṣin rẹ̀ sì yára ju idì lọ. Ègbé ni fún wa àwa parun.
Ta rorai muone! Mũndũ ũcio aroka ta matu, ngaari ciake cia ita irooka ta kĩhuhũkanio, nacio mbarathi ciake ihanyũkaga gũkĩra nderi. Ĩiya witũ-ĩ! Tũrĩ aniine biũ.
14 Ìwọ Jerusalẹmu, mú búburú kúrò lọ́kàn rẹ kí o sì yè. Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò mú èrò búburú wà ní ọkàn rẹ?
Wee Jerusalemu-rĩ, theria ũũru kuuma ngoro-inĩ yaku nĩguo ũhonoke. Ũgũtũũra ũthugundaga ũũru meciiria-inĩ maku nginya-rĩ?
15 Ohùn kan sì ń kéde ní Dani o ń kókìkí ìparun láti orí òkè Efraimu wá.
Nĩ kũrĩ na mũgambo wa mũndũ ũranĩrĩra kũu Dani, ũkaanĩrĩra ũhoro wa mwanangĩko kũu irĩma-inĩ cia Efiraimu.
16 “Sọ èyí fún àwọn orílẹ̀-èdè, kéde rẹ̀ fún Jerusalẹmu pé: ‘Ọmọ-ogun ọ̀tá ń bọ̀ láti ilẹ̀ jíjìn wá wọ́n sì ń kígbe ogun láti dojúkọ ìlú Juda.
“Ĩrai ndũrĩrĩ ũhoro ũcio, hunjĩriai Jerusalemu muuge atĩrĩ: ‘Ita inene rĩa gũgũũkĩrĩra nĩrĩroka riumĩte bũrũri wa kũraya, na rĩroka na mbugĩrĩrio ya mbaara ya gũũkĩrĩra matũũra mothe manene ma Juda.
17 Wọ́n yí i ká bí ìgbà tí àwọn ọkùnrin bá ń ṣọ́ pápá, nítorí pé ó ti dìtẹ̀ sí mi,’” ni Olúwa wí.
Marĩrigiicĩirie o ta andũ marangĩire mũgũnda, tondũ itũũra rĩu nĩrĩnemeire, rĩkanjũkĩrĩra,’” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
18 “Ìwà rẹ àti ìṣe rẹ ló fa èyí bá ọ ìjìyà rẹ sì nìyìí. Báwo ló ti ṣe korò tó! Báwo ló ti ṣe gún ọkàn rẹ sí!”
“Mĩthiĩre yaku mwene na ciĩko ciaku nĩcio ikũreheire maũndũ macio. Rĩĩrĩ nĩrĩo iherithia rĩaku. Na kaĩ nĩ irũrũ-ĩ! Kaĩ nĩrĩgũtheeca ngoro-ĩ!”
19 Háà! Ìrora mi, ìrora mi! Mo yí nínú ìrora. Háà, ìrora ọkàn mi! Ọkàn mi lù kìkì nínú mi, n kò le è dákẹ́. Nítorí mo ti gbọ́ ohùn ìpè, mo sì ti gbọ́ igbe ogun.
Wũi, ruo-ĩ, wũi ruo-ĩ! Ndĩrenyogonda nĩ ruo. Wũi, ruo rũnene ngoro-inĩ yakwa-ĩ! Ngoro yakwa nĩĩratumatuuma, ndingĩhota gũkirĩrĩria. Nĩgũkorwo nĩnjiguĩte mũgambo wa karumbeta; nĩnjiguĩte mbugĩrĩrio ya mbaara.
20 Ìparun ń gorí ìparun; gbogbo ilẹ̀ náà sì ṣubú sínú ìparun lọ́gán ni a wó àwọn àgọ́ mi, tí ó jẹ́ ohun ààbò mi níṣẹ́jú kan.
Mwanangĩko ũrarũmanĩrĩra na mwanangĩko; bũrũri wothe nĩwanangĩtwo. O rĩmwe hema ciakwa nĩthũkangie, o kahinda gatarĩ cooho kĩĩgitio gĩakwa gĩgathũkangio.
21 Yóò ti pẹ́ tó, tí èmi yóò rí ogun tí èmi yóò sì gbọ́ ìró fèrè?
Nĩ nginya rĩ ngũtũũra nyonaga bendera ya mbaara, na ngaigua mũgambo wa karumbeta?
22 “Aṣiwèrè ni àwọn ènìyàn mi; wọn kò mọ̀ mí. Wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n ọmọ; wọ́n sì jẹ́ aláìlóye. Wọ́n mọ ibi ni ṣíṣe; wọn kò mọ bí a ti í ṣe rere.”
“Andũ akwa nĩ irimũ; matinjũũĩ. Nĩ ciana iteciiragia, na ikaaga ũmenyo. Ũũgĩ ũrĩa marĩ naguo no wa gwĩka ũũru; matiũĩ gwĩka wega.”
23 Mo bojú wo ayé, ó sì wà ní júujùu, ó sì ṣófo àti ní ọ̀run, ìmọ́lẹ̀ wọn kò sì ṣí.
Ndaacũthĩrĩirie thĩ, ngĩkĩona atĩ ndĩarĩ ũrĩa yatariĩ na ndĩarĩ na kĩndũ; ningĩ ngĩcũthĩrĩria matu-inĩ, ngĩona atĩ gũtiarĩ na ũtheri.
24 Mo wo àwọn òkè ńlá, wọ́n wárìrì; gbogbo òkè kéékèèké mì jẹ̀jẹ̀.
Ndaacũthĩrĩria irĩma, ngĩona atĩ nĩgũthingitha ciathingithaga; natuo tũrĩma tuothe nĩ kwereera twereeraga.
25 Mo wò yíká n kò rí ẹnìkan; gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ló ti fò lọ.
Ngĩcũthĩrĩria, ngĩona atĩ gũtiarĩ na andũ; nyoni ciothe cia rĩera-inĩ nĩciombũkĩte ikoora.
26 Mo bojú wò, ilẹ̀ eléso, ó sì di aṣálẹ̀ gbogbo àwọn ìlú inú rẹ̀ sì ṣubú sínú ìparun níwájú Olúwa àti níwájú ríru ìbínú rẹ̀.
Ngĩcũthĩrĩria, ngĩona bũrũri ũrĩa waciaraga maciaro maingĩ, watuĩkĩte o werũ mũtheri, matũũra makuo mothe nĩmamomokeire hau mbere ya Jehova, makagũa thĩ nĩ ũndũ wa marakara make mahiũ.
27 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Gbogbo ìlú náà yóò sì di ahoro, síbẹ̀ èmi kì yóò pa á run pátápátá.
Ũũ nĩguo Jehova ekuuga: “Bũrũri wothe nĩũkanangwo, o na gũtuĩka ndikaũniina biũ.
28 Nítorí náà, ayé yóò pohùnréré ẹkún àwọn ọ̀run lókè yóò ṣú òòkùn nítorí mo ti sọ, mo sì ti pète rẹ̀ mo ti pinnu, n kì yóò sì yí i padà.”
Nĩ ũndũ ũcio thĩ nĩĩgacakaya, narĩo igũrũ rĩgĩe nduma, tondũ ũguo nĩguo njugĩte, na ndingĩĩricũkwo. Nĩnduĩte itua na ndikũgarũrũka.”
29 Nípa ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin àti àwọn tafàtafà gbogbo ìlú yóò sálọ. Ọ̀pọ̀ sálọ sínú igbó; ọ̀pọ̀ yóò sì gun orí àpáta lọ. Gbogbo ìlú náà sì di ahoro; kò sì ṣí ẹnìkan nínú rẹ̀.
Rĩrĩa kwaiguuo mũrurumo wa andũ arĩa mathiiaga mahaicĩte mbarathi na wa andũ arĩa maikagia mĩguĩ-rĩ, andũ a matũũra mothe no makoora. Amwe ao makoorĩra ihinga-inĩ, nao amwe ao makahaica ndwaro-inĩ cia mahiga. Matũũra macio mothe nĩmathaamĩtwo; gũtirĩ mũndũ ũikaraga kuo.
30 Kí ni ò ń ṣe, ìwọ tí o ti di ìjẹ tán? Ìwọ ìbá wọ ara rẹ ní aṣọ òdodo kí o sì fi wúrà ṣe ara rẹ lọ́ṣọ̀ọ́. Àwọn olólùfẹ́ rẹ kẹ́gàn rẹ; wọ́n sì ń lépa ẹ̀mí rẹ.
Ũreka atĩa, wee ũnũhĩtwo? Ũkwĩhumba nguo ndune na ũkegemia na mathaga ma thahabu nĩkĩ? Ũrahaka mbutu ciaku cia maitho rangi nĩkĩ? Atĩrĩrĩ, kwĩgemia gwaku no gwa tũhũ. Endwa aku nĩmakwagĩire bata; rĩu maracaria ũrĩa mangĩkũruta muoyo.
31 Mo gbọ́ ìró kan bí i igbe obìnrin tó ń rọbí, tí ó ń rọbí, ìrora bí i abiyamọ ọmọbìnrin Sioni tí ń pohùnréré ẹkún ara rẹ̀. Tí ó na ọwọ́ rẹ̀ tí ó sì wí pé, “Kíyèsi i mo gbé, nítorí a ti fi ẹ̀mí mi lé àwọn apani lọ́wọ́.”
Nĩndĩraigua kĩrĩro ta kĩa mũndũ-wa-nja akĩrũmwo, arĩ na mũcaayo ta wa mũtumia agĩciara mwana wake wa irigithathi: nĩ kĩrĩro kĩa Mwarĩ wa Zayuni agĩteeha, atambũrũkĩtie moko make, akiugaga atĩrĩ, “Wũi-ĩ-iya-wakwa-ĩ! Nĩndĩraringĩka; muoyo wakwa nĩmũneane kũrĩ oragani.”