< Jeremiah 4 >

1 “Tí ìwọ yóò bá yí padà, ìwọ Israẹli, padà tọ̀ mí wá,” ni Olúwa wí. “Tí ìwọ yóò bá sì mú ìríra rẹ kúrò níwájú mi, ìwọ kí ó sì rìn kiri.
Oe, Isarel na ban pawiteh, kai koe vah ban, telah BAWIPA ni ati. Panuet na thonae hah ka hmaitung hoi na tâkhawng pawiteh, puen e lah na awm mahoeh toe.
2 Tí ó bá jẹ́ lóòtítọ́ àti òdodo ni ìwọ búra. Nítòótọ́ bí Olúwa ti wà láààyè, nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò di alábùkún fún nípasẹ̀ rẹ, àti nínú rẹ̀ ni wọn yóò ṣògo.”
BAWIPA teh a hring, telah lawkkatang hoi lawkcengnae hoi, lannae dawk lawk na kam vaiteh, BAWIPA lahoi miphunnaw pueng ni amamouh dawk yaw ka hawi e lah ao awh han. Ahnimouh dawk pholennae lah ao awh han telah ati.
3 Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu: “Hú gbogbo ilẹ̀ tí ẹ kò lò rí, kí o má sì ṣe gbìn sáàrín ẹ̀gún.
Bangkongtetpawiteh, Judah taminaw hoi Jerusalem taminaw koe BAWIPA ni hettelah a dei. Na laikawknaw hah kanawk awh nateh, pâkhing um vah cati tu hanh awh.
4 Kọ ara rẹ ní ilà sí Olúwa, kọ ọkàn rẹ ní ilà, ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìbínú mi yóò ru jáde yóò sì jó bí iná, nítorí ibi tí o ti ṣe kì yóò sí ẹni tí yóò pa á.
Nangmouh Judah taminaw hoi Jerusalem vah kho kasaknaw hanelah namamae lungthin vuensom hah a awh telah nahoeh pawiteh, yonnae na sak e kecu dawkvah, ka lungkhueknae teh hmai patetlah tawk vaiteh, apinihai padout thai laipalah na kang payon awh vaih.
5 “Kéde ní Juda, kí o sì polongo ní Jerusalẹmu, kí o sì wí pé: ‘Fun fèrè káàkiri gbogbo ilẹ̀!’ Kí o sì kígbe: ‘Kó ara jọ pọ̀! Jẹ́ kí a sálọ sí ìlú olódi.’
Judah ram dawk pathang nateh, Jerusalem vah pâpho awh. Ram thung vah, mongka ueng nateh hram awh. Cungtalah kamkhueng nateh, rapan ka tawn e kho dawkvah, kâen awh sei telah tet awh.
6 Fi àmì láti sálọ sí Sioni hàn, sálọ fún ààbò láìsí ìdádúró. Nítorí èmi ó mú àjálù láti àríwá wá, àní ìparun tí ó burú jọjọ.”
Zion mon koelah lukkarei pathout awh. Roumnae tawng awh nateh uet hanh awh. Bangkongtetpawiteh, atunglah hoi kalenpounge rawknae hoi kathoute ka pha sak han.
7 Kìnnìún ti sá jáde láti inú ibùgbé rẹ̀, apanirun orílẹ̀-èdè sì ti jáde. Ó ti fi ààyè rẹ̀ sílẹ̀ láti ba ilẹ̀ rẹ̀ jẹ́. Ìlú rẹ yóò di ahoro láìsí olùgbé.
Ratu thung hoi sendek tâcawt vaiteh, miphunnaw ka raphoekung a tho lahun. Na ram hah raphoe hanelah a onae hmuen koehoi a tâco toe. Na khopui hah tami ao hoeh na hanlah a raphoe awh han.
8 Nítorí náà, gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀ káàánú kí o sì pohùnréré ẹkún, nítorí ìbínú ńlá Olúwa kò tí ì kúrò lórí wa.
Hat kecu dawkvah, burihni kâkhu awh nateh kap awh haw. Hramki awh. Bangkongtetpawiteh, ka patawpoung e BAWIPA lungkhueknae hah maimouh koehoi kamlang hoeh rah.
9 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí pé, “Àwọn ọba àti ìjòyè yóò pàdánù ẹ̀mí wọn, àwọn àlùfáà yóò wárìrì, àwọn wòlíì yóò sì fòyà.”
Hote hnin dawk teh hettelah ao han telah BAWIPA ni ati. Siangpahrang hoi kahrawikungnaw e lungthin hah puen tâsue laihoi ao awh han. Vaihmanaw hah kângairu lah awm awh vaiteh, profetnaw ni a lungpout awh han.
10 Nígbà náà ni mo sì wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè, báwo ni ìwọ ti ṣe tan àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti Jerusalẹmu jẹ nípa sísọ wí pé, ‘Ìwọ yóò wà ní àlàáfíà,’ nígbà tí o jẹ́ wí pé idà wà ní ọ̀fun wa.”
Hahoi kai ni Oe! Bawipa Jehovah, hete taminaw hoi Jerusalem hah pueng hoi na dum toe, tahloi ni a hringnae a thut navah, roumnae na hmu han na ti telah ka ti.
11 Nígbà náà ni a ó sọ fún Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn pé, “Ẹ̀fúùfù líle láti aṣálẹ̀ fẹ́ lu àwọn ènìyàn mi, kì í ṣe láti sọ di mímọ́.
Hatnae tueng dawk teh, hete taminaw hoi Jerusalem koe, kahrawng arasangnae cailum hmuen koehoi kabetpoung e kahlî ni ka taminaw hoi ka canunaw koe lah ahnimouh palek sak hane hoi thoung sak hanelah laipalah kahlî a tho han.
12 Ẹ̀fúùfù líle tí ó wá láti ọ̀dọ̀ mi. Báyìí mo kéde ìdájọ́ mi lórí wọn.”
Hotnaw hanelah ka patawpoung e kahlî kai koehoi a tho han. Ahnimouh taranlahoi lawkcengnae hai ka dei han, telah tie lah ao han.
13 Wò ó! O ń bọ̀ bí ìkùùkuu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ sì wá bí ìjì líle ẹṣin rẹ̀ sì yára ju idì lọ. Ègbé ni fún wa àwa parun.
Khenhaw! tâmai patetlah bongparui patetlah kaawm e rangleng hoi a tho han. A marang teh mataw hlak hai aranghnawn. Maimouh teh yawkathout e lah o awh, rawknae koe lah pha awh toe.
14 Ìwọ Jerusalẹmu, mú búburú kúrò lọ́kàn rẹ kí o sì yè. Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò mú èrò búburú wà ní ọkàn rẹ?
Oe, Jerusalem rungngang lah na o thai nahan, ka thout e lungthin hah thoung sak totouh maw pouk payonnae na thung vah ao han.
15 Ohùn kan sì ń kéde ní Dani o ń kókìkí ìparun láti orí òkè Efraimu wá.
Bangkongtetpawiteh, Dan ram hoi lawk a tâco teh, Ephraim mon hoi kathoute hah a pâpho.
16 “Sọ èyí fún àwọn orílẹ̀-èdè, kéde rẹ̀ fún Jerusalẹmu pé: ‘Ọmọ-ogun ọ̀tá ń bọ̀ láti ilẹ̀ jíjìn wá wọ́n sì ń kígbe ogun láti dojúkọ ìlú Juda.
Miphun tangkuem koe dei awh. Oe Jerusalem taranlahoi pâpho awh. Khenhaw! ram hlanae koehoi katuetnaw a tho teh, Judah khopuinaw taran lah hoi a hram awh.
17 Wọ́n yí i ká bí ìgbà tí àwọn ọkùnrin bá ń ṣọ́ pápá, nítorí pé ó ti dìtẹ̀ sí mi,’” ni Olúwa wí.
Kai na taran awh dawkvah, law karingkungnaw patetlah a tengpam hoi a kalup awh telah BAWIPA ni ati.
18 “Ìwà rẹ àti ìṣe rẹ ló fa èyí bá ọ ìjìyà rẹ sì nìyìí. Báwo ló ti ṣe korò tó! Báwo ló ti ṣe gún ọkàn rẹ sí!”
Na hringnae na nuencang hoi na tawksak e ni hete hno heh, na lathueng vah a pha sak. Hetteh kakhat e, na hawi awh hoeh nae lah ao dawkvah, na lungthin hah a thut.
19 Háà! Ìrora mi, ìrora mi! Mo yí nínú ìrora. Háà, ìrora ọkàn mi! Ọkàn mi lù kìkì nínú mi, n kò le è dákẹ́. Nítorí mo ti gbọ́ ohùn ìpè, mo sì ti gbọ́ igbe ogun.
Oe, ka hringnae, ka hringnae, ka lungthin roeroe heh a patawpoung. Ka thung vah ka lungthin hanghangkâan. Duem kaawm thai hoeh. Tarantuknae pawlawk hoi kâhruetcuetnae mongka ueng e pawlawk hah na thai dawkvah Oe, ka hringnae duem kaawm thai hoeh.
20 Ìparun ń gorí ìparun; gbogbo ilẹ̀ náà sì ṣubú sínú ìparun lọ́gán ni a wó àwọn àgọ́ mi, tí ó jẹ́ ohun ààbò mi níṣẹ́jú kan.
Rawknae dawkvah rawknae a hram. Bangkongtetpawiteh, ramnaw pueng hah a rawk toe. Kaie lukkareiim hah vai touh hoi a rawk teh, lukkarei hai tawkkadek dawk a rawk.
21 Yóò ti pẹ́ tó, tí èmi yóò rí ogun tí èmi yóò sì gbọ́ ìró fèrè?
Atueng nâsittouh maw tarantuknae lukkarei hah ka hmu vaiteh, mongka lawk ka thai han vai.
22 “Aṣiwèrè ni àwọn ènìyàn mi; wọn kò mọ̀ mí. Wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n ọmọ; wọ́n sì jẹ́ aláìlóye. Wọ́n mọ ibi ni ṣíṣe; wọn kò mọ bí a ti í ṣe rere.”
Bangkongtetpawiteh, ka taminaw teh a pathu poung dawkvah, kai na panuek awh hoeh. Camo ka pathu e panuenae ka tawn hoeh e patetlah ao awh. Kathout e sak hanelah a lungang awh eiteh, hawinae sak hane panuek awh hoeh.
23 Mo bojú wo ayé, ó sì wà ní júujùu, ó sì ṣófo àti ní ọ̀run, ìmọ́lẹ̀ wọn kò sì ṣí.
Talai ka khet navah a hrawnghrang pui lah ao. Kalvan hai ka khet navah, a angnae awm hoeh.
24 Mo wo àwọn òkè ńlá, wọ́n wárìrì; gbogbo òkè kéékèèké mì jẹ̀jẹ̀.
Mon hai ka khet navah, koung a pâyaw. Monruinaw pueng hai koung kâkapek
25 Mo wò yíká n kò rí ẹnìkan; gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ló ti fò lọ.
Ka khet navah, taminaw hai awm hoeh. Kalvan e tavanaw pueng hai koung kamleng.
26 Mo bojú wò, ilẹ̀ eléso, ó sì di aṣálẹ̀ gbogbo àwọn ìlú inú rẹ̀ sì ṣubú sínú ìparun níwájú Olúwa àti níwájú ríru ìbínú rẹ̀.
Ka khet navah kahawi e law hah kahrawng lah ao toe. BAWIPA e hmalah, pueng hoi a lungkhueknae hmalah khopuinaw pueng hai a rawp awh.
27 Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Gbogbo ìlú náà yóò sì di ahoro, síbẹ̀ èmi kì yóò pa á run pátápátá.
Bangkongtetpawiteh, BAWIPA ni hettelah a dei. Ramnaw pueng kingdi han. Hateiteh, abuemlahoi teh ka pout sak mahoeh.
28 Nítorí náà, ayé yóò pohùnréré ẹkún àwọn ọ̀run lókè yóò ṣú òòkùn nítorí mo ti sọ, mo sì ti pète rẹ̀ mo ti pinnu, n kì yóò sì yí i padà.”
Hote hno kecu dawk talai ni a cingou han. Lathueng lae kalvan hai a hmo han. Bangkongtetpawiteh, ka dei toung dawkvah, ka kâcai toe. Pankângai vaiteh, bout kamlang mahoeh toe.
29 Nípa ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin àti àwọn tafàtafà gbogbo ìlú yóò sálọ. Ọ̀pọ̀ sálọ sínú igbó; ọ̀pọ̀ yóò sì gun orí àpáta lọ. Gbogbo ìlú náà sì di ahoro; kò sì ṣí ẹnìkan nínú rẹ̀.
Marangransanaw hoi licung ka e pawlawk hoi khopui koung a yawng han. Ka hmawt e ratu thung vah kâen awh vaiteh, talung dawk a luen awh han. Khonaw pueng cettakhai vaiteh kho ka sak e buet touh boehai awm awh mahoeh.
30 Kí ni ò ń ṣe, ìwọ tí o ti di ìjẹ tán? Ìwọ ìbá wọ ara rẹ ní aṣọ òdodo kí o sì fi wúrà ṣe ara rẹ lọ́ṣọ̀ọ́. Àwọn olólùfẹ́ rẹ kẹ́gàn rẹ; wọ́n sì ń lépa ẹ̀mí rẹ.
Na rawk torei teh, bangtelamaw na ti han. Ka paling e khohna nakunghai, sui puengcang hoi na kamthoup nakunghai, mitlakhuem na kâhluk nakunghai, aphu kaawm hoeh e na kamthoup rumram e doeh. Na thoundounnaw ni na dudam awh mingming han. Na hringnae thei hanlah a tawng awh han.
31 Mo gbọ́ ìró kan bí i igbe obìnrin tó ń rọbí, tí ó ń rọbí, ìrora bí i abiyamọ ọmọbìnrin Sioni tí ń pohùnréré ẹkún ara rẹ̀. Tí ó na ọwọ́ rẹ̀ tí ó sì wí pé, “Kíyèsi i mo gbé, nítorí a ti fi ẹ̀mí mi lé àwọn apani lọ́wọ́.”
Bangkongtetpawiteh, napui ni camo khe pataw khangnae kâhram pawlawk ka thai. Camin ka khe e ni pataw a khangnae doeh. Zion canu kâha a uek teh a kut a dâw teh ka yawthoe poung toe, bangtelah, tamikathoutnaw kecu dawk ka hringnae ka rei thai poung toe telah ati.

< Jeremiah 4 >