< Jeremiah 38 >
1 Ṣefatia ọmọ Mattani, Gedaliah ọmọ Paṣuri, Jehukali ọmọ Ṣelemiah, àti Paṣuri ọmọ Malkiah, gbọ́ ohun tí Jeremiah ń sọ fún àwọn ènìyàn nígbà tí ó sọ wí pé,
Nao Shefatia mũrũ wa Matani, na Gedalia mũrũ wa Pashuri, na Jehukali mũrũ wa Shemalia, o na Pashuri mũrũ wa Malikija nĩmaiguire ũrĩa Jeremia eeraga andũ othe, rĩrĩa oigire atĩrĩ,
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ẹnikẹ́ni tó bá dúró nínú ìlú yìí yóò kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tó bá lọ sí Babeli yóò yè; yóò sá àsálà, yóò sì yè.’
“Jehova ekuuga atĩrĩ: ‘Mũndũ ũrĩa wothe ũgũikara itũũra-inĩ rĩĩrĩ inene nĩakooragwo na rũhiũ rwa njora, kana ngʼaragu, kana mũthiro, no ũrĩa ũgwĩtwara kũrĩ andũ a Babuloni nĩagatũũra muoyo. Nĩakahonokia muoyo wake; nĩagatũũra muoyo.’
3 Àti pé èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ìdánilójú wà wí pé a ó fi ìlú náà lé ọwọ́ àwọn ọmọ-ogun ọba Babeli; tí yóò sì kó wa nígbèkùn.’”
Ningĩ, Jehova ekuuga atĩrĩ: ‘Itũũra rĩĩrĩ inene no nginya rĩkaneanwo kũrĩ mbũtũ cia ita cia mũthamaki wa Babuloni, ũrĩa ũkaarĩtunyana.’”
4 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè wí fún ọba pé, “Ó yẹ kí a pa ọkùnrin yìí; ó ń kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ-ogun tókù nínú ìlú pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn nípa ohun tí ó ń sọ fún wọn. Ọkùnrin yìí kò fẹ́ ìre fún àwọn ènìyàn bí kò ṣe ìparun.”
Hĩndĩ ĩyo anene makĩĩra mũthamaki atĩrĩ, “Mũndũ ũyũ aagĩrĩire ooragwo. Nĩaratũma thigari iria itigaire gũkũ itũũra-inĩ rĩĩrĩ inene ciĩtigĩre, o ũndũ ũmwe na andũ aya othe, nĩ ũndũ wa maũndũ macio arameera. Mũndũ ũyũ ndarĩ ũndũ mwega areciirĩria andũ aya tiga o ũũru.”
5 Sedekiah ọba sì wí pé, “Ó wà lọ́wọ́ yín. Ọba kò lè ṣe ohunkóhun láti takò yín.”
Mũthamaki Zedekia agĩcookia atĩrĩ, “Arĩ moko-inĩ manyu; mũthamaki ndangĩgirĩrĩria mwĩke ũrĩa inyuĩ mũkwenda.”
6 Wọ́n gbé Jeremiah sọ sínú ihò Malkiah, ọmọ ọba, tí ó wà ní àgbàlá ilé túbú; wọ́n fi okùn sọ Jeremiah kalẹ̀ sí ìsàlẹ̀ ihò; kò sì ṣí omi nínú ihò náà bí kò ṣe ẹrọ̀fọ̀, Jeremiah sì rì sínú ẹrọ̀fọ̀ náà.
Nĩ ũndũ ũcio makĩnyiita Jeremia makĩmũikia irima rĩa maaĩ rĩa Malikija, ũrĩa mũrũ wa mũthamaki, rĩrĩa rĩarĩ kũu nja ĩyo ya arangĩri. Magĩikũrũkia Jeremia irima rĩu rĩa maaĩ na mĩkanda; no rĩtiarĩ na maaĩ, no mũtondo rĩarĩ, nake Jeremia agĩtoonyerera kũu mũtondo-inĩ ũcio.
7 Ṣùgbọ́n, Ebedimeleki, ará Kuṣi ìjòyè nínú ààfin ọba gbọ́ pé wọ́n ti ju Jeremiah sínú kànga. Nígbà tí ọba jókòó ní ẹnu-bodè Benjamini.
No rĩrĩ, Ebedi-Meleku ũrĩa Mũkushi, ũmwe wa arĩa mehokeirwo wĩra wa kũu nyũmba-inĩ ya ũthamaki, nĩaiguire atĩ nĩmaikĩtie Jeremia irima rĩu rĩa maaĩ. Hĩndĩ ĩyo mũthamaki aikarĩte Kĩhingo-inĩ kĩa Benjamini,
8 Ebedimeleki jáde kúrò láàfin ọba, ó sì sọ fún un pé,
Ebedi-Meleku akiuma hau nja ya nyũmba ya ũthamaki, akĩmwĩra atĩrĩ,
9 “Olúwa mi ọba, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti ṣe ohun búburú sí Jeremiah wòlíì Ọlọ́run. Wọ́n ti gbé e sọ sínú kànga níbi tí kò sí oúnjẹ kankan nínú ìlú mọ́.”
“Mũthamaki mwathi wakwa, andũ aya nĩmekĩte ũũru nĩ ũndũ wa maũndũ maya mothe mekĩte Jeremia ũrĩa mũnabii. Nĩmamũikĩtie irima rĩa maaĩ, akuĩre kuo nĩ ngʼaragu, tondũ mĩgate ĩkirie gũthira gũkũ itũũra-inĩ inene.”
10 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Ebedimeleki ará Kuṣi pé, “Mú ọgbọ̀n ọkùnrin láti ibí pẹ̀lú rẹ, kí ẹ sì fa wòlíì Jeremiah sókè láti inú ihò, kí ó tó kú.”
Hĩndĩ ĩyo mũthamaki agĩatha Ebedi-Meleku ũcio Mũkushi, akĩmwĩra atĩrĩ: “Oya andũ mĩrongo ĩtatũ kuuma haha mũthiĩ nao mũkarute Jeremia ũcio mũnabii kuuma irima rĩu rĩa maaĩ atanakua.”
11 Ebedimeleki kó àwọn ọkùnrin náà pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n lọ sínú yàrá kan nínú ààfin ọba. Ó mú àwọn aṣọ àkísà àti okùn tọ Jeremiah lọ nínú kànga.
Nĩ ũndũ ũcio Ebedi-Meleku akĩoya andũ acio, agĩthiĩ nao, nao magĩtoonya kanyũmba kaarĩ rungu rwa harĩa haaigagwo mũthiithũ wa indo cia bata kũu thĩinĩ wa nyũmba ya ũthamaki. Akĩoya ndangari imwe cia nguo ngũrũ, na nguo iria nduĩku ciarĩ kuo, agĩciikũrũkĩria Jeremia na mĩkanda kũu irima rĩa maaĩ.
12 Ebedimeleki ará Kuṣi sọ fún Jeremiah pé, “Fi àkísà àti okùn bọ abẹ́ abíyá rẹ, Jeremiah sì ṣe bẹ́ẹ̀.”
Ebedi-Meleku ũcio Mũkushi, akĩĩra Jeremia atĩrĩ: “Ĩkĩra nguo icio ngũrũ na ndangari icio njegeeke, wĩrigĩrĩrie gũkerwo nĩ mĩkanda ĩyo.” Nake Jeremia agĩĩka o ũguo,
13 Báyìí ni wọ́n ṣe fi okùn yọ Jeremiah jáde, wọ́n sì mu un gòkè láti inú ihò wá, Jeremiah sì wà ní àgbàlá ilé túbú.
nao makĩmũguucia na mĩkanda ĩyo, makĩmũruta irima rĩu rĩa maaĩ. Nake Jeremia agĩikara kũu nja ĩyo ya arangĩri.
14 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ pe, Jeremiah òjíṣẹ́ Ọlọ́run àti láti mú un wá sí ẹnu ibodè kẹta nílé Olúwa. Ọba sì sọ fún Jeremiah pé, “Èmi yóò bi ọ́ ní ohun kan; má sì ṣe fi ohun kan pamọ́ fún mi.”
Mũthamaki Zedekia agĩtũmanĩra Jeremia ũcio mũnabii, akiuga areehwo itoonyero-inĩ rĩa gatatũ rĩa hekarũ ya Jehova. Mũthamaki akĩĩra Jeremia atĩrĩ, “Nĩngũkũũria ũndũ. Nawe ndũkaahithe ũhoro o na ũrĩkũ.”
15 Jeremiah sì sọ fún Sedekiah pé, “Tí mo bá fún ọ ní èsì, ṣé o kò nípa mí? Tí mo bá gbà ọ́ nímọ̀ràn, o kò ní gbọ́ tèmi.”
Jeremia akĩĩra Zedekia atĩrĩ, “Ingĩkuumburĩra ũhoro-rĩ, githĩ ndũkũnjũraga? O na ingĩgũtaara-rĩ, wee ndũngĩĩthikĩrĩria.”
16 Ṣùgbọ́n ọba Sedekiah búra ní ìkọ̀kọ̀ fún Jeremiah wí pé, “Dájúdájú bí Olúwa ti ń bẹ, ẹni tí ó fún wa ní ẹ̀mí, èmi kò nípa ọ́ tàbí fà ọ́ fún àwọn tó ń lépa ẹ̀mí rẹ.”
Nake Mũthamaki Zedekia akĩĩhĩta mwĩhĩtwa na hitho harĩ Jeremia, akiuga ũũ: “Ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo, o we ũrĩa watũheire muoyo ũyũ tũrĩ naguo-rĩ, niĩ ndigũkũũraga kana ngũneane moko-inĩ ma acio mendaga gũkũruta muoyo.”
17 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún Sedekiah pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Àyàfi bí o bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn olóyè ọba Babeli, a ó dá ẹ̀mí rẹ sí àti pé ìlú yìí kò ní di jíjó ní iná; ìwọ àti ilé rẹ yóò sì wà láààyè.
Nake Jeremia akĩĩra Zedekia atĩrĩ, “Ũũ nĩguo Jehova Ngai-Mwene-Hinya-Wothe, o we Ngai wa Isiraeli, ekuuga: ‘Ũngĩĩneeana kũrĩ anene a mũthamaki wa Babuloni, muoyo waku nĩũkũhonokio, o na itũũra rĩĩrĩ inene rĩtigaacinwo; wee na andũ a nyũmba yaku nĩmũgũtũũra muoyo.
18 Ṣùgbọ́n tí o kò bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn ìjòyè ọba Babeli, a ó fa ìlú yìí lé ọwọ́ àwọn Babeli. Wọn yóò sì fi iná sun ún, ìwọ gan an kò ní le sá mọ́ wọn lọ́wọ́.’”
No ũngĩrega kwĩneana kũrĩ anene a mũthamaki wa Babuloni, itũũra rĩĩrĩ nĩrĩkũneanwo kũrĩ andũ a Babuloni, nao marĩcine na mwaki rĩthire; na wee mwene ndũkahonoka kuuma moko-inĩ mao.’”
19 Ọba Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Mò ń bẹ̀rù àwọn Júù tó ti sálọ sí ilẹ̀ Babeli, nítorí pé àwọn ará Babeli lè fà mí lé wọn lọ́wọ́ láti fìyà jẹ mí.”
Mũthamaki Zedekia akĩĩra Jeremia atĩrĩ, “Nĩndĩretigĩra Ayahudi arĩa meneanĩte kũrĩ andũ a Babuloni, nĩ ũndũ andũ a Babuloni mahota kũũneana kũrĩ Ayahudi acio nao maanyamarie.”
20 Jeremiah sì dáhùn wí pé, “Wọn kò ní fi ọ́ lé e lọ́wọ́. Pa ọ̀rọ̀ Olúwa mọ́ nípa ṣíṣe ohun tí mo sọ fún ọ; yóò sì dára fún ọ, ẹ̀mí rẹ yóò sì wà.
Nake Jeremia akĩmũcookeria atĩrĩ, “Matigaakũneana kũrĩ o. Wee athĩkĩra Jehova, wĩke ũguo ndĩrakwĩra. Hĩndĩ ĩyo nĩũkona wega, naguo muoyo waku nĩũkahonokio.
21 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kọ̀ láti jọ̀wọ́ ara rẹ, èyí ni ohun tí Olúwa ti fihàn mí.
No rĩrĩ, warega kwĩneana, ũũ nĩguo Jehova anguũrĩirie:
22 Gbogbo àwọn obìnrin tókù ní ààfin ọba Juda ni wọn yóò kó jáde fún àwọn ìjòyè ọba Babeli. Àwọn obìnrin náà yóò sì sọ fún ọ pé: “‘Àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tàn ọ́ jẹ, wọ́n sì borí rẹ. Ẹsẹ̀ rẹ rì sínú ẹrọ̀fọ̀; àwọn ọ̀rẹ́ rẹ ti fi ọ́ sílẹ̀.’
Andũ-a-nja othe arĩa matigaire thĩinĩ wa nyũmba ya mũthamaki wa Juda nĩmagatwarĩrwo anene a mũthamaki wa Babuloni. Andũ-a-nja acio nao magaakwĩra atĩrĩ: “‘Arata acio aku wehokeete nĩmakũhĩtithirie na magĩgũkĩria hinya. Magũrũ maku nĩmatoonyereire mũtondo-inĩ; nao arata aku nĩmagũtiganĩirie.’
23 “Wọn yóò kó àwọn ìyàwó àti ọmọ rẹ wá sí Babeli. Ìwọ gan an kò ní bọ́ níbẹ̀, ọba Babeli yóò mú ọ, wọn yóò sì jó ìlú yìí kanlẹ̀.”
“Atumia aku othe na ciana ciaku nĩmakaneanwo kũrĩ andũ a Babuloni. Wee mwene ndũkehonokia moko-inĩ mao, no nĩũkanyiitwo nĩ mũthamaki wa Babuloni; narĩo itũũra rĩĩrĩ inene nĩrĩgacinwo rĩthire.”
24 Nígbà náà ni Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí, tàbí kí o kú.
Hĩndĩ ĩyo Zedekia akĩĩra Jeremia atĩrĩ, “Ndũkareke mũndũ o na ũrĩkũ amenye ũhoro wa mĩario ĩno, ndũkae kũũragwo.
25 Tí àwọn ìjòyè bá mọ̀ pé mo bá ọ sọ̀rọ̀, tí wọ́n bá wá bá ọ wí pé, ‘Sọ fún wa ohun tí o bá ọba sọ tàbí ohun tí ọba sọ fún ọ; má ṣe fi pamọ́ fún wa tàbí kí a pa ọ́,’
Anene mangĩigua atĩ nĩtwaranĩirie nawe, nao moke kũrĩ we makũũrie atĩrĩ, ‘Twĩre ũrĩa wĩrĩte mũthamaki, na ũrĩa nake mũthamaki akwĩrĩte; ndũgatũhithe ũndũ kana tũkũũrage,’
26 nígbà náà kí o sọ fún wọn, ‘Mò ń bẹ ọba láti má jẹ́ kí n padà lọ sí ilé Jonatani láti lọ kú síbẹ̀.’”
hĩndĩ ĩyo nawe ũmeere atĩrĩ, ‘Nĩgũthaitha ndĩrathaithaga mũthamaki ndakae kũnjookia nyũmba-inĩ kwa Jonathani, ndigakuĩre kuo.’”
27 Gbogbo àwọn olóyè sì wá sí ọ̀dọ̀ Jeremiah láti bi í léèrè, ó sì sọ gbogbo ohun tí ọba ní kí ó sọ. Wọn kò sì sọ ohunkóhun mọ́, nítorí kò sí ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ tí òun àti ọba jọ sọ.
Anene acio othe nĩmookire kũrĩ Jeremia, makĩmũũria ũhoro ũcio, nake akĩmeera ũrĩa wothe aathĩtwo nĩ mũthamaki oige. Nĩ ũndũ ũcio matiamwĩrire ũndũ ũngĩ, nĩgũkorwo gũtirĩ mũndũ waiguĩte ũrĩa maarĩtie na mũthamaki.
28 Jeremiah wà nínú àgbàlá àwọn ẹ̀ṣọ́ títí di ọjọ́ tí wọ́n fi kó Jerusalẹmu:
Nake Jeremia agĩikara kũu kĩhingo-inĩ kĩa arangĩri nginya mũthenya ũrĩa itũũra rĩa Jerusalemu rĩatunyanirwo.