< Jeremiah 38 >

1 Ṣefatia ọmọ Mattani, Gedaliah ọmọ Paṣuri, Jehukali ọmọ Ṣelemiah, àti Paṣuri ọmọ Malkiah, gbọ́ ohun tí Jeremiah ń sọ fún àwọn ènìyàn nígbà tí ó sọ wí pé,
En ce temps-là, dit le Seigneur, je serai le Dieu de la maison d'Israël, et elle sera mon peuple.
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ẹnikẹ́ni tó bá dúró nínú ìlú yìí yóò kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tó bá lọ sí Babeli yóò yè; yóò sá àsálà, yóò sì yè.’
Voici ce que dit le Seigneur: J'ai trouvé dans le désert mon peuple encore vivant parmi les cadavres d'hommes tués par le glaive; allez et ne perdez pas Israël.
3 Àti pé èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ìdánilójú wà wí pé a ó fi ìlú náà lé ọwọ́ àwọn ọmọ-ogun ọba Babeli; tí yóò sì kó wa nígbèkùn.’”
Le Seigneur lui est apparu de loin. Je t'ai aimé d'un amour éternel; c'est pourquoi, dans ma miséricorde, je t'ai attiré à moi.
4 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè wí fún ọba pé, “Ó yẹ kí a pa ọkùnrin yìí; ó ń kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ-ogun tókù nínú ìlú pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn nípa ohun tí ó ń sọ fún wọn. Ọkùnrin yìí kò fẹ́ ìre fún àwọn ènìyàn bí kò ṣe ìparun.”
Je te réédifierai, et tu seras réédifiée vierge d'Israël; tu prendras encore ton tambour, et tu sortiras avec une troupe de chanteurs.
5 Sedekiah ọba sì wí pé, “Ó wà lọ́wọ́ yín. Ọba kò lè ṣe ohunkóhun láti takò yín.”
Puisque vous avez planté des vignes sur les montagnes de Samarie, plantez, et chantez des louanges.
6 Wọ́n gbé Jeremiah sọ sínú ihò Malkiah, ọmọ ọba, tí ó wà ní àgbàlá ilé túbú; wọ́n fi okùn sọ Jeremiah kalẹ̀ sí ìsàlẹ̀ ihò; kò sì ṣí omi nínú ihò náà bí kò ṣe ẹrọ̀fọ̀, Jeremiah sì rì sínú ẹrọ̀fọ̀ náà.
Car c'est le jour où ceux qui plaident en la montagne d'Éphraïm appelleront leurs frères, disant: Levez-vous, et allez à Sion auprès du Seigneur, votre Dieu.
7 Ṣùgbọ́n, Ebedimeleki, ará Kuṣi ìjòyè nínú ààfin ọba gbọ́ pé wọ́n ti ju Jeremiah sínú kànga. Nígbà tí ọba jókòó ní ẹnu-bodè Benjamini.
Voici ce que dit le Seigneur à Jacob: Réjouissez-vous et tressaillez à la tête des nations; proclamez et chantez des louanges, disant: Le Seigneur a sauvé son peuple, le reste d'Israël.
8 Ebedimeleki jáde kúrò láàfin ọba, ó sì sọ fún un pé,
Voilà que je les ramènerai de l'aquilon; je les rassemblerai des extrémités de la terre pour la fête de la Pâque. Et mon peuple engendrera une nombreuse multitude, et ils reviendront ici.
9 “Olúwa mi ọba, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti ṣe ohun búburú sí Jeremiah wòlíì Ọlọ́run. Wọ́n ti gbé e sọ sínú kànga níbi tí kò sí oúnjẹ kankan nínú ìlú mọ́.”
Ils sont partis pleurant, et je les ramènerai consolés; ils logeront sur le bord des eaux, dans une voie droite, et ils ne s'y égareront pas; parce que je suis devenu pour Israël un père, et qu'Éphraïm est mon premier-né.
10 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Ebedimeleki ará Kuṣi pé, “Mú ọgbọ̀n ọkùnrin láti ibí pẹ̀lú rẹ, kí ẹ sì fa wòlíì Jeremiah sókè láti inú ihò, kí ó tó kú.”
Peuples, écoutez les paroles du Seigneur, publiez-les dans les lies lointaines, et dites: Celui qui a vanné Israël, le rassemblera; et il le gardera, comme le pasteur son troupeau.
11 Ebedimeleki kó àwọn ọkùnrin náà pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n lọ sínú yàrá kan nínú ààfin ọba. Ó mú àwọn aṣọ àkísà àti okùn tọ Jeremiah lọ nínú kànga.
Car le Seigneur est le rédempteur de Jacob; il l'a retiré des mains d'un plus fort que lui.
12 Ebedimeleki ará Kuṣi sọ fún Jeremiah pé, “Fi àkísà àti okùn bọ abẹ́ abíyá rẹ, Jeremiah sì ṣe bẹ́ẹ̀.”
Et ils viendront, et ils se réjouiront en la montagne de Sion, et ils viendront jouir des biens du Seigneur, en une terre pleine de blé et de vin, et de fruits, et de grand bétail, et de menus troupeaux; et leur âme sera comme un arbre fruitier, et ils n'auront plus faim.
13 Báyìí ni wọ́n ṣe fi okùn yọ Jeremiah jáde, wọ́n sì mu un gòkè láti inú ihò wá, Jeremiah sì wà ní àgbàlá ilé túbú.
Alors les jeunes filles se réjouiront dans l'assemblée des jeunes gens, et les vieillards se réjouiront, et je changerai leur deuil en fête, et je les remplirai d'allégresse.
14 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ pe, Jeremiah òjíṣẹ́ Ọlọ́run àti láti mú un wá sí ẹnu ibodè kẹta nílé Olúwa. Ọba sì sọ fún Jeremiah pé, “Èmi yóò bi ọ́ ní ohun kan; má sì ṣe fi ohun kan pamọ́ fún mi.”
Je glorifierai et j'enivrerai l'âme des prêtres fils de Lévi, et mon peuple se rassasiera de mes biens.
15 Jeremiah sì sọ fún Sedekiah pé, “Tí mo bá fún ọ ní èsì, ṣé o kò nípa mí? Tí mo bá gbà ọ́ nímọ̀ràn, o kò ní gbọ́ tèmi.”
Voici ce que dit le Seigneur: Une voix a été entendue en Rama, avec des lamentations, des gémissements et des larmes; et Rachel pleurante n'a point voulu être consolée sur ses fils, car ils ne sont plus.
16 Ṣùgbọ́n ọba Sedekiah búra ní ìkọ̀kọ̀ fún Jeremiah wí pé, “Dájúdájú bí Olúwa ti ń bẹ, ẹni tí ó fún wa ní ẹ̀mí, èmi kò nípa ọ́ tàbí fà ọ́ fún àwọn tó ń lépa ẹ̀mí rẹ.”
Voici ce que dit le Seigneur: Que tes sanglots s'arrêtent, que tes yeux cessent de verser des larmes; car tes œuvres auront leur récompense, et tes fils reviendront de la terre des ennemis.
17 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún Sedekiah pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Àyàfi bí o bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn olóyè ọba Babeli, a ó dá ẹ̀mí rẹ sí àti pé ìlú yìí kò ní di jíjó ní iná; ìwọ àti ilé rẹ yóò sì wà láààyè.
Il y aura une demeure stable pour tes fils.
18 Ṣùgbọ́n tí o kò bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn ìjòyè ọba Babeli, a ó fa ìlú yìí lé ọwọ́ àwọn Babeli. Wọn yóò sì fi iná sun ún, ìwọ gan an kò ní le sá mọ́ wọn lọ́wọ́.’”
J'ai entendu Ephraïm gémissant; il disait: Vous m'avez châtié, et je suis corrigé; j'étais comme un taureau indompté, ramenez-moi, et je reviendrai; car vous êtes le Seigneur, mon Dieu.
19 Ọba Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Mò ń bẹ̀rù àwọn Júù tó ti sálọ sí ilẹ̀ Babeli, nítorí pé àwọn ará Babeli lè fà mí lé wọn lọ́wọ́ láti fìyà jẹ mí.”
Après ma captivité je me suis repenti, et après m'être reconnu j'ai pleuré sur mes jours de honte, et je me suis montré à vous; car dès ma jeunesse j'ai porté mon opprobre.
20 Jeremiah sì dáhùn wí pé, “Wọn kò ní fi ọ́ lé e lọ́wọ́. Pa ọ̀rọ̀ Olúwa mọ́ nípa ṣíṣe ohun tí mo sọ fún ọ; yóò sì dára fún ọ, ẹ̀mí rẹ yóò sì wà.
Éphraïm est pour moi un fils bien-aimé, un enfant de prédilection, et, puisque mes paroles sont en lui, je ne l'oublierai pas; c'est pourquoi je l'ai secouru avec sollicitude, et je le traiterai avec miséricorde, dit le Seigneur
21 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kọ̀ láti jọ̀wọ́ ara rẹ, èyí ni ohun tí Olúwa ti fihàn mí.
Prononce sur toi-même, Sion, charge-toi de te punir; donne ton cœur aux droits chemins; reviens en la voie où tu marchais, vierge d'Israël, reviens pleurante en tes cités.
22 Gbogbo àwọn obìnrin tókù ní ààfin ọba Juda ni wọn yóò kó jáde fún àwọn ìjòyè ọba Babeli. Àwọn obìnrin náà yóò sì sọ fún ọ pé: “‘Àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tàn ọ́ jẹ, wọ́n sì borí rẹ. Ẹsẹ̀ rẹ rì sínú ẹrọ̀fọ̀; àwọn ọ̀rẹ́ rẹ ti fi ọ́ sílẹ̀.’
Quand reviendras-tu vers moi, fille déshonorée; car le Seigneur a fait naître le salut d'une plantation nouvelle, et des hommes la parcourront pour y trouver leur salut.
23 “Wọn yóò kó àwọn ìyàwó àti ọmọ rẹ wá sí Babeli. Ìwọ gan an kò ní bọ́ níbẹ̀, ọba Babeli yóò mú ọ, wọn yóò sì jó ìlú yìí kanlẹ̀.”
Voici ce que dit le Seigneur: On dira encore cette parole en la terre de Juda et en ses villes, lorsque j'aurai ramené ses captifs: Béni soit le Seigneur sur la montagne sainte qui lui est consacrée!
24 Nígbà náà ni Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí, tàbí kí o kú.
C'est là qu'habiteront les villes de Juda; et le laboureur et le pâtre, avec ses troupeaux, parcourront tout son territoire.
25 Tí àwọn ìjòyè bá mọ̀ pé mo bá ọ sọ̀rọ̀, tí wọ́n bá wá bá ọ wí pé, ‘Sọ fún wa ohun tí o bá ọba sọ tàbí ohun tí ọba sọ fún ọ; má ṣe fi pamọ́ fún wa tàbí kí a pa ọ́,’
J'ai enivré toute âme altérée; j'ai rassasié toute âme affamée,
26 nígbà náà kí o sọ fún wọn, ‘Mò ń bẹ ọba láti má jẹ́ kí n padà lọ sí ilé Jonatani láti lọ kú síbẹ̀.’”
Et après cela je me suis éveillé et j'ai vu, et mon sommeil avait été doux pour moi.
27 Gbogbo àwọn olóyè sì wá sí ọ̀dọ̀ Jeremiah láti bi í léèrè, ó sì sọ gbogbo ohun tí ọba ní kí ó sọ. Wọn kò sì sọ ohunkóhun mọ́, nítorí kò sí ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ tí òun àti ọba jọ sọ.
Voilà que les jours arrivent, me dit encore le Seigneur, où je sèmerai Israël et Juda, semence d'hommes et semence de bêtes.
28 Jeremiah wà nínú àgbàlá àwọn ẹ̀ṣọ́ títí di ọjọ́ tí wọ́n fi kó Jerusalẹmu:
Et ceci arrivera: comme j'avais veillé sur eux pour renverser et détruire, ainsi je veillerai sur eux pour bâtir et planter, dit le Seigneur:
En ces jours-là, on ne dira point: Les pères ont mangé le verjus, et les dents de leurs fils en ont été agacées.
Mais chacun mourra pour son péché, et celui qui mangera le verjus en aura les gencives agacées.
Voilà que les jours arrivent, dit le Seigneur, où je ferai une alliance nouvelle avec la maison d'Israël et la maison de Juda,
Non comme l'alliance que je fis avec leurs pères le jour où, les ayant pris par la main, je les tirai de la terre d'Égypte; car ils n'ont point maintenant mon alliance, et moi, je ne me suis plus occupé d'eux, dit le Seigneur.
Mais voici l'alliance qu'après ces jours-là je ferai avec la maison d'Israël, dit le Seigneur: je leur donnerai mes lois, et je les mettrai en leur pensée, et je les écrirai dans leur cœur; je serai leur Dieu, et ils seront mon peuple.
Et ils s'enseigneront plus chacun son concitoyen ou son frère, disant: Connais le Seigneur; car alors tous me connaîtront du petit au grand, et je serai miséricordieux pour leurs iniquités, et je ne me souviendrai plus de leurs péchés.
Comme le ciel ne peut s'élever, ni les fondements de la terre s'abaisser, dit le Seigneur, ainsi je n'éprouverai point la race d'Israël en retour de ce qu'ils ont fait.
Voici ce que dit le Seigneur: Celui qui a créé le soleil pour éclairer les jours, la lune et les étoiles pour éclairer les nuits; celui qui a donné à la mer ses bruits et aux vagues leur murmure, son nom est le Seigneur tout- puissant.
Si tes lois cessent d'être devant moi, dit le Seigneur, la race d'Israël cessera désormais d'être un peuple à mes yeux.
Et voilà que les jours arrivent, dit le Seigneur, où la ville du Seigneur sera rebâtie, depuis la tour d'Anaméhel jusqu'à la porte de l'Angle.
Et sa mesure s'étendra jusqu'à la colline de Gareb, et on l'entourera de pierres de choix.
Et tout le terrain, depuis Asarimoth jusqu'au torrent de Cédron et à l'angle de la porte orientale des chevaux, sera consacré au Seigneur; et il ne sera plus abandonné, et il n'y aura plus rien de détruit jusqu'à la fin des siècles.

< Jeremiah 38 >