< Jeremiah 37 >

1 Sedekiah ọmọ Josiah sì jẹ ọba ní ipò Jehoiakini ọmọ Jehoiakimu ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli fi jẹ ọba ní ilẹ̀ Juda.
Na rĩrĩ, Zedekia mũrũ wa Josia nĩatuirwo mũthamaki wa Juda nĩ Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni, nake agĩthamaka ithenya rĩa Jekonia mũrũ wa Jehoiakimu.
2 Ṣùgbọ́n àti òun àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà kò fetísí ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ nípa wòlíì Jeremiah.
No rĩrĩ, we mwene o na kana arĩa maamũtungatagĩra, na andũ a bũrũri ũcio matiarũmbũirie ciugo iria Jehova aarĩtie na kanua ka Jeremia ũcio mũnabii.
3 Sedekiah ọba sì rán Jehukali ọmọ Ṣelemiah àti Sefaniah ọmọ Maaseiah sí Jeremiah wòlíì wí pé, “Jọ̀wọ́ gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run wa fún wa.”
Nake Mũthamaki Zedekia agĩtũma Jehukali mũrũ wa Shelemia marĩ na Zefania mũrũ wa Maaseia ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai mathiĩ kũrĩ Jeremia ũcio mũnabii, mamũtwarĩre ndũmĩrĩri ĩno: “Twagũthaitha ũtũhooere kũrĩ Jehova, Ngai witũ.”
4 Nígbà yìí Jeremiah sì ń wọlé, ó sì ń jáde láàrín àwọn ènìyàn nítorí wọ́n ti fi sínú túbú.
Na rĩrĩ, ihinda rĩu Jeremia aarĩ na wĩyathi wa gũceeranga gatagatĩ-inĩ ka andũ, nĩgũkorwo ndaakoretwo aikĩtio njeera.
5 Àwọn ọmọ-ogun Farao ti jáde kúrò nílẹ̀ Ejibiti àti nígbà tí àwọn ará Babeli tó ń ṣàtìpó ní Jerusalẹmu gbọ́ ìròyìn nípa wọn, wọ́n kúrò ní Jerusalẹmu.
Hĩndĩ ĩyo mbũtũ cia ita cia Firaũni nĩcioimagarĩte kuuma bũrũri wa Misiri, na rĩrĩa andũ a Babuloni arĩa maarigiicĩirie Jerusalemu maiguire ũhoro wacio, makĩhũndũka, makĩehera kũu Jerusalemu.
6 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì Ọlọ́run wá:
Hĩndĩ ĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩgĩkinyĩra Jeremia ũcio mũnabii, akĩĩrwo atĩrĩ,
7 “Èyí ni, ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ fún ọba àwọn Juda tó rán ọ láti wádìí nípa mi. ‘Àwọn ọmọ-ogun Farao tó jáde láti kún ọ lọ́wọ́ yóò padà sílẹ̀ wọn sí Ejibiti.
“Jehova, Ngai wa Isiraeli, ekuuga atĩrĩ: Ĩra mũthamaki wa Juda, ũcio ũgũtũmĩte ũũke ũhooe kĩrĩra harĩ niĩ, atĩrĩ, ‘Mbũtũ cia ita cia Firaũni icio irooka gũgũteithia-rĩ, nĩigũcooka bũrũri wacio, kũu bũrũri wa Misiri.
8 Nígbà náà ni àwọn ará Babeli yóò padà láti gbógun ti ìlú. Wọn yóò mú wọn nígbèkùn, wọn yóò sì fi iná jó ìlú náà kanlẹ̀.’
Hĩndĩ ĩyo nao andũ a Babuloni nĩmagacooka gũkũ na matharĩkĩre itũũra rĩĩrĩ inene, marĩtunyane na marĩcine na mwaki.’
9 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹ má ṣe tan ara yín jẹ ní èrò wí pé, ‘Àwọn ará Babeli yóò fi wá sílẹ̀ pẹ̀lú ìdánilójú.’ Wọn kò ní ṣe bẹ́ẹ̀.
“Jehova ekuuga atĩrĩ: Tigai kwĩheenia, mũgĩĩciiria atĩrĩ, ‘Andũ a Babuloni ti-itherũ nĩmegũtigana na ithuĩ matweherere.’ Matigeeka ũguo!
10 Kódà tó bá ṣe pé wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ọmọ-ogun Babeli tí ń gbóguntì yín àti àwọn tí ìjàǹbá ṣe, tí wọ́n ti fi sílẹ̀ ní ibùdó wọn; wọn yóò jáde láti jó ìlú náà kanlẹ̀.”
O na mũngĩhoota mbũtũ ciothe cia ita cia andũ a Babuloni icio iramũtharĩkĩra, na gũtuĩke atĩ no andũ arĩa matiihangĩtio matigĩtwo hema-inĩ ciao-rĩ, no moime kũu hema-inĩ na macine itũũra rĩĩrĩ na mwaki.”
11 Lẹ́yìn tí àwọn ọmọ-ogun Babeli ti kúrò ní Jerusalẹmu nítorí àwọn ọmọ-ogun Farao.
Thuutha wa mbũtũ icio cia ita cia andũ a Babuloni kwehera kũu Jerusalemu nĩ ũndũ wa mbũtũ cia Firaũni,
12 Jeremiah múra láti fi ìlú náà sílẹ̀, láti lọ sí olú ìlú Benjamini láti gba ẹ̀tọ́ rẹ̀ nínú ohun ìní láàrín àwọn ènìyàn tó wà níbẹ̀.
Jeremia nĩoimagarire kuuma itũũra-inĩ rĩu inene nĩguo athiĩ bũrũri wa Benjamini akenyiitĩre igai rĩake rĩa gĩthaka gatagatĩ-inĩ ka andũ arĩa maarĩ kuo.
13 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n dé ẹnu ibodè Benjamini, olórí àwọn olùṣọ́ tí orúkọ rẹ ń jẹ́ Irijah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Hananiah mú un, ó wí pé, “Ìwọ ń fi ara mọ́ àwọn ará Babeli.”
No rĩrĩa aakinyire Kĩhingo-inĩ kĩa Benjamini, mũnene wa arangĩri ũrĩa wetagwo Irija mũrũ wa Shelemia, mũrũ wa Hanania, akĩmũnyiita, akiuga atĩrĩ, “Wee nĩ kũũra ũroora ũthiĩ ũkeneane kũrĩ andũ a Babuloni!”
14 Jeremiah sọ wí pé, “Èyí kì í ṣe òtítọ́! Èmi kò yapa sí àwọn ará Babeli.” Ṣùgbọ́n Irijah ko gbọ́ tirẹ̀, dípò èyí a mú Jeremiah, ó sì mú un lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ìjòyè.
Jeremia akĩmwĩra atĩrĩ, “Aca ũguo tiguo! Niĩ ti kũũra ndĩroora ngeneane kũrĩ andũ a Babuloni.” No Irija akĩrega kũmũthikĩrĩria; handũ ha ũguo akĩnyiita Jeremia, akĩmũtwara kũrĩ anene.
15 Nítorí náà ni àwọn ìjòyè ṣe bínú sí Jeremiah, wọ́n jẹ ẹ́ ní yà, wọ́n tún fi sí túbú nílé Jonatani akọ̀wé nítorí wọ́n ti fi èyí ṣe ilé túbú.
Anene acio nĩmarakarĩire Jeremia, na magĩathana ahũũrwo na ahingĩrwo nyũmba ya Jonathani ũrĩa mwandĩki, ĩrĩa maatuĩte njeera.
16 Wọ́n fi Jeremiah sínú túbú tí ó ṣókùnkùn biribiri; níbi tí ó wà fún ìgbà pípẹ́.
Nake Jeremia agĩtoonyio mungu-inĩ warĩ kanyũmba ga thĩinĩ mũno kũu kĩoho-inĩ, kũrĩa aikarire matukũ maingĩ.
17 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ sí i, tí ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n mú wá sí ààfin níbi tí ó ti bi í ní ìkọ̀kọ̀ pé, “Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ kan wà láti ọ̀dọ̀ Olúwa?” Jeremiah fèsì pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, wọn ó fi ọ́ lé ọwọ́ ọba Babeli.”
Na thuutha ũcio Mũthamaki Zedekia agĩtũmana areehwo kũu nyũmba-inĩ ya ũthamaki. Arĩ kũu, mũthamaki akĩmũũria na hitho atĩrĩ, “Hihi nĩ harĩ ndũmĩrĩri yumĩte kũrĩ Jehova?” Nake Jeremia akĩmũcookeria atĩrĩ, “Ĩĩ, nĩ kũrĩ; wee nĩũkaneanwo moko-inĩ ma mũthamaki wa Babuloni.”
18 Nígbà náà, Jeremiah sọ fún ọba Sedekiah pé, “Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ yín, àwọn ìjòyè yín pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí ẹ fi sọ mí sínú túbú?
Ningĩ Jeremia akĩĩra Mũthamaki Zedekia atĩrĩ, “Nĩ ũndũ ũrĩkũ ngwĩhĩtie we mwene, kana ndungata ciaku, o na kana andũ aya, nĩguo njikio njeera?
19 Níbo ni àwọn wòlíì yín tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín wí pé ọba Babeli kò ní gbóguntì yín wá?
Marĩ ha anabii acio aku, acio maakũrathĩire ũhoro atĩrĩ, ‘Mũthamaki wa Babuloni ndagagũtharĩkĩra wee o na kana bũrũri ũyũ’?
20 Ṣùgbọ́n ní báyìí, olúwa mi ọba, èmí bẹ̀ ọ. Jẹ́ kí n mú ẹ̀dùn ọkàn mi tọ̀ ọ́ wá; má ṣe rán mi padà sí ilé Jonatani akọ̀wé, àfi kí n kú síbẹ̀.”
Na rĩu-rĩ, wee mũthamaki mwathi wakwa, ĩtĩkĩra gũthikĩrĩria. Njĩtĩkĩria ndeehe mathaithana makwa mbere yaku: Ndũkanjookie nyũmba ya Jonathani ũrĩa mwandĩki, ndigakuĩre kuo.”
21 Ọba Sedekiah wá pàṣẹ pé kí wọ́n fi Jeremiah sínú àgbàlá àwọn ẹ̀ṣọ́, àti kí wọn sì fún ní àkàrà ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan títí tí àkàrà tó wà ní ìlú yóò fi tán; bẹ́ẹ̀ ni Jeremiah wà nínú àgbàlá náà.
Nake Mũthamaki Zedekia akĩruta watho, akiuga atĩ Jeremia aigwo kũu nja ĩrĩa ya arangĩri, na aheagwo mũgate o mũthenya ũrutĩtwo barabara-inĩ ya arugi mĩgate, o nginya rĩrĩa mĩgate ĩgaathira kũu itũũra-inĩ inene. Nĩ ũndũ ũcio Jeremia agĩikara kũu nja ĩyo ya arangĩri.

< Jeremiah 37 >