< Jeremiah 37 >

1 Sedekiah ọmọ Josiah sì jẹ ọba ní ipò Jehoiakini ọmọ Jehoiakimu ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli fi jẹ ọba ní ilẹ̀ Juda.
Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese da Yehoiagini (Yihoiagimi egefe) amo fadegale, ea ouligisu sogebi amo Sedegaia (Yousaia egefe) ema i.
2 Ṣùgbọ́n àti òun àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà kò fetísí ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ nípa wòlíì Jeremiah.
Be hina bagade Sedegaia amola ea eagene ouligisu dunu amola Yuda dunu huluane da Hina Gode Ea sia: nama i, amo hame nabasu.
3 Sedekiah ọba sì rán Jehukali ọmọ Ṣelemiah àti Sefaniah ọmọ Maaseiah sí Jeremiah wòlíì wí pé, “Jọ̀wọ́ gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run wa fún wa.”
Yuda hina bagade Sedegaia da Yihuga: le (Sielemaia egefe) amola gobele salasu dunu Sefanaia (Ma: iasia egefe) amo nama na da ninia fi fidima: ne, Hina Godema sia: ne gadoma: ne sia: musa: asunasi.
4 Nígbà yìí Jeremiah sì ń wọlé, ó sì ń jáde láàrín àwọn ènìyàn nítorí wọ́n ti fi sínú túbú.
Amo esoha, na da gagili ga: i diasu ganodini hame salabe ba: i. Be na da udigili dunu ilia esalebe ganodini ahoasu.
5 Àwọn ọmọ-ogun Farao ti jáde kúrò nílẹ̀ Ejibiti àti nígbà tí àwọn ará Babeli tó ń ṣàtìpó ní Jerusalẹmu gbọ́ ìròyìn nípa wọn, wọ́n kúrò ní Jerusalẹmu.
Ba: bilone dadi gagui wa: i da Yelusaleme amoma doagala: lalu. Be ilia da Idibidi dadi gagui wa: i da Idibidi alalo giadofai amo nababeba: le, ilia da sinidigili hobea: i.
6 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì Ọlọ́run wá:
Amalalu, Hina Gode, Isala: ili ilia Gode, da nama sia: i.
7 “Èyí ni, ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ fún ọba àwọn Juda tó rán ọ láti wádìí nípa mi. ‘Àwọn ọmọ-ogun Farao tó jáde láti kún ọ lọ́wọ́ yóò padà sílẹ̀ wọn sí Ejibiti.
E da na Sedegaiama amane sia: ma: ne sia: i, “Idibidi dadi gagui wa: i da di fidimusa: manebe. Be ilia da sinidigili, ilia sogega buhagimu.
8 Nígbà náà ni àwọn ará Babeli yóò padà láti gbógun ti ìlú. Wọn yóò mú wọn nígbèkùn, wọn yóò sì fi iná jó ìlú náà kanlẹ̀.’
Amasea, Ba: bilone dunu da bu misini, Yelusaleme amoma gegenanu, laluga ulagimu.
9 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹ má ṣe tan ara yín jẹ ní èrò wí pé, ‘Àwọn ará Babeli yóò fi wá sílẹ̀ pẹ̀lú ìdánilójú.’ Wọn kò ní ṣe bẹ́ẹ̀.
Na, Hina Gode, da dima sisasu iaha. Dilia ogogole Ba: bilone dunu da bu hame misunu mae dawa: ma. Bai ilia da dafawane bu misunu.
10 Kódà tó bá ṣe pé wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ọmọ-ogun Babeli tí ń gbóguntì yín àti àwọn tí ìjàǹbá ṣe, tí wọ́n ti fi sílẹ̀ ní ibùdó wọn; wọn yóò jáde láti jó ìlú náà kanlẹ̀.”
Amola dilia da Ba: bilone dadi gagui wa: i huluane hasali ganiaba, amola Ba: bilone fa: ginisi dunu fawane ilia abula diasu ganodini diasa: ili esala ganiaba, amo dunu da wa: legadole, dilia moilai bai bagade laluga nene dagoma: ne ulagila: loba.”
11 Lẹ́yìn tí àwọn ọmọ-ogun Babeli ti kúrò ní Jerusalẹmu nítorí àwọn ọmọ-ogun Farao.
Ba: bilone dadi gagui wa: i da Yelusaleme doagala: su yolesili, hobea: i. Bai ilia da Idibidi dadi gagui da doagala: musa: ahoanebe nabi.
12 Jeremiah múra láti fi ìlú náà sílẹ̀, láti lọ sí olú ìlú Benjamini láti gba ẹ̀tọ́ rẹ̀ nínú ohun ìní láàrín àwọn ènìyàn tó wà níbẹ̀.
Amaiba: le, na da Yelusaleme yolesili, na soge (na fi ilia soge la: idi sogebi) Bediamini soge bagade amo ganodini diala, amo lamusa: , na da masunu dawa: i galu.
13 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n dé ẹnu ibodè Benjamini, olórí àwọn olùṣọ́ tí orúkọ rẹ ń jẹ́ Irijah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Hananiah mú un, ó wí pé, “Ìwọ ń fi ara mọ́ àwọn ará Babeli.”
Be na da Bediamini Logo Holei amoga doaga: loba, dadi gagui ouligisu amoga hawa: hamonanu (ea dio da Ailaidia [Sielemaia egefe amola Ha: nanaia ea aowa]) e da na logo ga: le, nama amane sia: i, “Di da hohonone, Ba: bilone fi amoga masunu galebe!”
14 Jeremiah sọ wí pé, “Èyí kì í ṣe òtítọ́! Èmi kò yapa sí àwọn ará Babeli.” Ṣùgbọ́n Irijah ko gbọ́ tirẹ̀, dípò èyí a mú Jeremiah, ó sì mú un lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ìjòyè.
Be na da bu adole i, “Hame mabu! Na da hohonone dili yolesimu hame dawa: !” Be Ailaidia da na sia: hame nabi. E da na gagulaligili, eagene ouligisu dunu ilima hiouginana asi.
15 Nítorí náà ni àwọn ìjòyè ṣe bínú sí Jeremiah, wọ́n jẹ ẹ́ ní yà, wọ́n tún fi sí túbú nílé Jonatani akọ̀wé nítorí wọ́n ti fi èyí ṣe ilé túbú.
Ilia da nama bagadewane ougi amola ilia sia: beba: le, ilia da na fananu, sia: dedesu dunu Yonada: ne amo ea diasu ganodini sali. Bai ilia da ea diasu gagili ga: i diasu agoane hamoi dagoi.
16 Wọ́n fi Jeremiah sínú túbú tí ó ṣókùnkùn biribiri; níbi tí ó wà fún ìgbà pípẹ́.
Na da uli dogoi sesei osobo hagudu amo ganodini salabe ba: i. Amo ganodini na da eso bagohame esalu.
17 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ sí i, tí ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n mú wá sí ààfin níbi tí ó ti bi í ní ìkọ̀kọ̀ pé, “Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ kan wà láti ọ̀dọ̀ Olúwa?” Jeremiah fèsì pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, wọn ó fi ọ́ lé ọwọ́ ọba Babeli.”
Fa: no, hina bagade Sedegaia da na ema misa: ne sia: i. E da wamowane, nama amane adole ba: i, “Hina Gode da ninima sia: adole iasibala: ?” Na da bu adole i, “Sia: galaiou! Di da Ba: bilone hina bagade amo ea loboga gagulaligi ba: mu.”
18 Nígbà náà, Jeremiah sọ fún ọba Sedekiah pé, “Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ yín, àwọn ìjòyè yín pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí ẹ fi sọ mí sínú túbú?
Amalalu, na da amane adole ba: i, “Di da na gagili ga: i diasu ganodini sali dagoi. Be na da adi wadela: i hou, dima o dilia eagene ouligisu dunu ilima o Yuda fi dunu ilima hamobela: ?
19 Níbo ni àwọn wòlíì yín tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín wí pé ọba Babeli kò ní gbóguntì yín wá?
Dia balofede dunu da wali habila: ? Ilia da ogogole, Ba: bilone hina bagade da dima amola ninia soge amoma hame doagala: mu sia: i.
20 Ṣùgbọ́n ní báyìí, olúwa mi ọba, èmí bẹ̀ ọ. Jẹ́ kí n mú ẹ̀dùn ọkàn mi tọ̀ ọ́ wá; má ṣe rán mi padà sí ilé Jonatani akọ̀wé, àfi kí n kú síbẹ̀.”
Amola wali, hina bagade, dia na sia: nabima: ne, na edegesa! Dia na gagili ga: i diasu amo Yonada: ne ea diasu ganodini amoga mae asunasima. Di agoane hamosea, na da amogawi dafawane bogomu.”
21 Ọba Sedekiah wá pàṣẹ pé kí wọ́n fi Jeremiah sínú àgbàlá àwọn ẹ̀ṣọ́, àti kí wọn sì fún ní àkàrà ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan títí tí àkàrà tó wà ní ìlú yóò fi tán; bẹ́ẹ̀ ni Jeremiah wà nínú àgbàlá náà.
Amaiba: le, hina bagade Sedegaia da ilia da na hina bagade diasu gagoi amo ganodini gagili ga: i diasu agoane esaloma: ne, logo ga: sima: ne sia: i. Na da amogawi esalu. Eso huluane ilia da agi ga: gi afadafa (agi ga: gi hamosu diasuga lai) nama ianu, agi ga: gi huluane Yelusaleme ganodini galu huluane dagobeba: le fawane yolesi.

< Jeremiah 37 >