< Jeremiah 36 >

1 Ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wí pé:
Hagi Josaia nemofo Jehoiakimi'ma Juda vahe kinima manino egeno nampa 4ma hia kafufina, Ra Anumzamo'a amanage huno Jeremaiana asami'ne.
2 “Mú ìwé kíká fún ará rẹ, kí o sì kọ sínú rẹ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ nípa Israẹli àti ti Juda, àti sí gbogbo orílẹ̀-èdè láti ìgbà tí mo ti sọ fún ọ láti ọjọ́ Josiah títí di òní.
Kagra mago avontafe eritenka, Israeli vahete'ene Juda vahete'enena maka kumatamimpima fore'ma hania knazanku'ma kasami'noa nanekea ana maka avontafepi krento. Hagi ana nanekema krentesanana, Josaia'ma kinima mani'nea knafima agafama hu'na nanekema kasami'noregati krenteme enka ama knare ehanatio.
3 Ó lè jẹ́ wí pé ilé Juda yóò gbọ́ gbogbo ibi tí mo ti pinnu láti ṣe fún wọn; kí wọn kí ó sì yípadà, olúkúlùkù wọn kúrò ní ọ̀nà búburú rẹ̀. Kí èmi kí ó lè dárí àìṣedéédéé àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n.”
Hagi maka Juda vahe'mo'za zamazeri haviza hunaku'ma antahintahima nehua zamofo nanekema antahizaresina, kefo avu'ava zazmia atre'za zamagu'a rukrahe hazage'na, kumi zamia atre zmantoresine.
4 Nígbà náà ni Jeremiah pe Baruku ọmọ Neriah, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí Ọlọ́run bá a sọ fún, Baruku sì kọ láti ẹnu Jeremiah, gbogbo ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó ti sọ fún un sórí ìwé kíká náà.
Hagi anante Jeremaia'a Neria nemofo Barukuna ke higeno egeno, mika nanekema Ra Anumzamo'ma asami'nea nanekea nesamigeno, Baruku'a mago avontafepi miko krente'ne.
5 Nígbà náà ni Jeremiah wí fún Baruku pé, “A sé mi mọ́! Èmi kò lè lọ sí ilé Olúwa.
Hagi ana hutegeno anante Jeremaia'a Barukuna amanage huno asami'ne, Nagra amafi kina hu'na mani'noanki'na Ra Anumzamofo mono nontega ovugahue.
6 Nítorí náà, ìwọ lọ sí ilé Olúwa ní ọjọ́ àwẹ̀, kí o sì kà nínú ìwé kíká náà ọ̀rọ̀ Olúwa tí ìwọ ti ẹnu mi kọ; ìwọ ó sì kà á ní etí gbogbo Juda, tí wọ́n jáde wá láti ìlú wọn.
E'ina hu'negu Ra Anumzamofo nanekema kasamugenka avontafepima krentana nanekea, ne'zama a'o hu'za nemaniza kna zupa Ra Anumzamofo mono nompi erinka vunka, ome hamprige'za maka mono nompima mani'nesaza Juda vahe'mo'za antahi vagareho. Ana nehuge'za Juda mopafima me'nea ranra kumatamimpinti'ma esaza vahe'mo'zanena antahigahaze.
7 Ó lè jẹ́ pé, ẹ̀bẹ̀ wọn yóò wá sí iwájú Olúwa, wọ́n ó sì yípadà kúrò ní ọ̀nà búburú wọn; nítorí pé títóbi ni ìbínú àti ìrunú tí Olúwa ti sọ sí àwọn ènìyàn yìí.”
Hagi zamagra kefo avu'ava'ma nehaza zama atre'za makamo'za zamagu'a rukrahe nehu'za, nunamuma hanageno'a Ra Anumzamo'ma asunku'ma huzmantesiana knare hugahie. Na'ankure Ra Anumzamo'a vahe'agura huno, tusi narimpa ahenezamante'na zamazeri haviza hugahue huno huama hu'ne.
8 Baruku ọmọ Neriah sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí wòlíì Jeremiah sọ fún, láti ka ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé ní ilé Olúwa.
Hagi anante Neria nemofo Baruku'a, kasnampa ne' Jeremaia'ma asami'nea nanekea, Ra Anumzamofo mono nompi ana maka nanekea ome hampri'ne.
9 Ní oṣù kẹsànán ọdún karùn-ún Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda ni wọ́n kéde àwẹ̀ níwájú Olúwa fún gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu àti fún gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wá láti ìlú Juda.
Hagi Juda kini ne' Josaia nemofo Jehoakimi'ma kinima mani'negeno vuno 5fuma hia kafumofona 9ni ikantera, Jerusalemi kumapi vahe'mo'zane maka Juda mopafima me'nea kuma tamimpima nemaniza vahemo'zanena Jerusalemi kumate e'za, ne'zana a'o hu'za manine'za Anumzamofo mono huntenaku hu'naze.
10 Láti inú yàrá Gemariah ọmọ Ṣafani akọ̀wé, ní àgbàlá òkè níbi ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tuntun. Baruku sì ka ọ̀rọ̀ Jeremiah láti inú ìwé ní ilé Olúwa sí etí gbogbo ènìyàn.
Hagi avontafepima maka'zama krenentea ne' Safani nemofo Gemaria'ma Ra Anumzamofo mono nompima nemanifi, maka vahe'mo'za nentahizageno Baruku'a Jeremaia'ma hu'nea nanekea avontafepinti hampri'ne. Hagi hunaraginte'nageno Gemaria'ma nemania nomo'a Ra Anumzamofo mono nomofo anaga kazigama me'nea kumapima, Ra mono nompima ufre kafanku'ma, Kasefa Kafanema nehaza kafama me'nea tva'onte me'ne.
11 Nígbà tí Mikaiah ọmọ Gemariah ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo àkọsílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé náà;
Hagi Ra Anumzamofo nanekema Baruku'ma avontafepinti'ma hampriana Safani negeho Gemaria ne'mofo Mikaia'a ana maka nanekea antahi vagare'ne.
12 Ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé ọba sínú yàrá akọ̀wé; níbi tí gbogbo àwọn ìjòyè gbé jókòó sí: Eliṣama akọ̀wé, Delaiah ọmọ Ṣemaiah, Elnatani ọmọ Akbori, Gemariah ọmọ Ṣafani àti Sedekiah ọmọ Hananiah àti gbogbo àwọn ìjòyè.
Ana'ma huteno'a agra kini ne'mofo nonte uramino, avoma kreno erinte fatgoma nehia ne'mofo nonte'ma viana, ana maka kini ne'mofo eri'za vahetami mani'nazageno vu'ne. Ana vahetamina avonkreno erinte fatgo nehia ne' Elisamaki, Semaia nemofo Delaiaki, Akbori nemofo Elnataniki, Safani nemofo Gemariaki, Hanania nemofo Zedekaia e'ne maka eri'za vahe'amo'za mani'nageno ome zamage'ne.
13 Lẹ́yìn tí Mikaiah sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí o ti gbọ́ fún wọn, nígbà tí Baruku kà láti inú ìwé kíkà náà ní etí àwọn ènìyàn.
Anante Baruku'ma avontafepinti'ma hamprige'za maka vahe'mo'zama antahi'naza nanekea, Mikaia'a ana nanekea ome zamasami vagare'ne.
14 Gbogbo àwọn ìjòyè sì rán Jehudu ọmọ Netaniah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Kuṣi sí Baruku wí pé, mú ìwé kíká náà ní ọwọ́ rẹ láti inú èyí tí ìwọ kà ní etí àwọn ènìyàn; kí o si wá. Nígbà náà ni Baruku ọmọ Neriah wá sí ọ̀dọ̀ wọn pẹ̀lú ìwé kíká ní ọwọ́ rẹ̀.
Ana'ma hutege'za maka kini ne'mofo eri'za vahe'mo'za oti'za, Kusi nagapinti ne' Selemaia negeho Netania nemofo Jehudi hunte'za, Barukuna amanage hunka ome asamio, e'ima hamprige'zama veamo'zama antahiza avontafera erino eno hu'za huntazageno vuno ome asamigeno, Neria nemofo Baruku'a ana avontafera erino zamagritega e'ne.
15 Wọ́n sì wí fún pé, “Jókòó, jọ̀wọ́ kà á sí etí wa!” Nígbà náà ni Baruku sì kà á ní etí wọn.
Hagi ana vahe'mo'za Barukuna asami'za, muse hugantonanki amare mani'nenka ana avona hamprio, hu'za hazageno Baruku'a ana avona hamprige'za antahi'naze.
16 Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ náà tan; wọ́n ń wo ara wọn lójú pẹ̀lú ẹ̀rù. Wọ́n sì wí fún Baruku pé, “Àwa gbọdọ̀ jábọ̀ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún ọba.”
Hagi Baruku'ma ana maka nanekema hamprige'za antahi vagama rete'za, zamanogu hu'za ovufi avufi nehu'za, Barukuna amanage hu'za asami'naze. Tamagerfa huta maka ama nanekea vuta kini ne' ome asamigahune.
17 Wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ Baruku pé, “Sọ fún wa báwo ni o ṣe kọ gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí? Ṣé Jeremiah ló sọ wọ́n?”
Hagi anante Barukuna antahige'za, muse hugantonanki inankna hunka ama avona kre'nampi tasamio? Jeremaia'a agra'a agipinti nehigenka maka ama avona kre'nampi?
18 Baruku sì dá wọn lóhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, láti ẹnu rẹ̀ ni, ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ báyìí fún mi, èmi sì fi tàdáwà kọ wọ́n sínú ìwé náà.”
Anage hazageno Baruku'a kenona huno, Izo agra agipinti nehige'na avo zota eri'na ana maka nanekea ama avontafepina krente'noe.
19 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè sọ fún Baruku wí pé, “Lọ fi ara rẹ pamọ́ àti Jeremiah, má sì ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ibi tí ẹ̀yin wà.”
Anante maka kini ne'mofo eri'za vahe'mo'za Barukuna asamiza, vahe'mo'za onkesarega kagrane Jeremaia'enena vuta ome fraki'o.
20 Lẹ́yìn tí wọ́n fi ìwé kíká náà pamọ́ sí iyàrá Eliṣama akọ̀wé, wọ́n sì wọlé tọ ọba lọ nínú àgbàlá, wọ́n sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà ní etí ọba.
Hagi anagema hute'za ana avontafera eri'za kini ne'mo'ma nemania kumapi vu'za, avoma kreno eri fatgoma nehia ne' Elisama nompi ome antete'za, vu'za ana maka nanekea kini ne' ome asamizageno antahi'ne.
21 Ọba sì rán Jehudu láti lọ mú ìwé kíká náà wá, Jehudu sì mu jáde láti inú iyàrá Eliṣama akọ̀wé. Ó sì ka ìwé náà ní etí ọba àti ní etí gbogbo àwọn ìjòyè tí ó dúró ti ọba.
Hagi ana avontafe ome erinka eno huno kini ne'mo'a Jehudina huntegeno vuno, avoma kreno erinte fatgoma nehia ne' Elisama nompinti ome erino eno, kini ne'ma mani'nere agri eri'za vahe'amozanena oti'nazageno ana avona eme hamprige'za antahi'naze.
22 Ó sì jẹ́ ìgbà òtútù nínú oṣù kẹsànán, ọba sì jókòó ní ẹ̀bá iná ààrò, iná náà sì ń jó ní iwájú rẹ̀.
Hagi ama ana zama fore hu'neana, 9ni ikana zasi nehia knagino kini ne'mo'a zasi'ma nehigeno nemania nompi, teve hugre'za nemaniza zama kapareti'ma tro'ma hunte'nafi tevea hugreno tonehino mani'ne.
23 Nígbà tí Jehudu ka ojú ìwé mẹ́ta sí mẹ́rin nínú ìwé náà, ọba fi ọ̀bẹ gé ìwé, ó sì sọ sínú iná tí ó wà nínú ìdáná, títí tí gbogbo ìwé kíká náà fi jóná tán.
Hagi Jehudi'a ana avoma osi'a hamprino 3'o 4'a isama nevigeno'a, kini ne'mo'a osi kazinteti anama'a ahesagane huno teve hugre'zama nemaniza zama tro'ma huntenafi kretere hu'ne. Ana huno nevigeno ana avontafera tevemo teno eri fanane hu'ne.
24 Síbẹ̀, ọba àti gbogbo àwọn ẹ̀mẹwà rẹ̀ tí wọ́n gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí kò bẹ̀rù; wọn kò sì fa aṣọ wọn yá.
Hagi kini ne'mo'ene maka eri'za vahe'amo'za magore hu'za ana nanekema nentahi'za korora nehu'za, kukenazamia tagatora osu'naze.
25 Elnatani, Delaiah àti Gemariah sì bẹ ọba kí ó má ṣe fi ìwé kíká náà jóná, ṣùgbọ́n ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn.
Hagi Elnatani'ma Delaia'ma Gemariaki hu'za kini nekura ana avontafera tevefina onkro hu'za asami'nazanagi, zamagri nanekea ontahi'ne.
26 Dípò èyí ọba pàṣẹ fún Jerahmeeli ọmọ Hameleki, Seraiah ọmọ Asrieli àti Ṣelemiah ọmọ Abdeeli láti mú Baruku akọ̀wé àti Jeremiah wòlíì ṣùgbọ́n Olúwa fi wọ́n pamọ́.
Ana'ma huteno kini ne'mo'a nemofo Jeramilinki, Azrieli nemofo Seraianki, Abdili nemofo Selemianki huno hunezmanteno, avoma kreno erinte fatgoma nehia ne' Barukune, kasnampa ne' Jeremaia kiznia vuta ome zanazerita eho huno huzamantege'za vu'naze. Hianagi Ra Anumzamo'a ana netrena zanazeri fraki'ne.
27 Lẹ́yìn tí ọba fi ìwé kíká náà tí ọ̀rọ̀ tí Baruku kọ láti ẹnu Jeremiah jóná tán, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá:
Hagi Jeremaia'ma nehigeno Baruku'ma kre'nea avontafe'ma kini ne'mo'ma tevefima kretegeno'a, anante Ra Anumzamo'a Jeremaiana amanage huno asami'ne,
28 “Wí pé, tún mú ìwé kíká mìíràn kí o sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé kíká èkínní tí Jehoiakimu ọba Juda fi jóná.
kagra mago avontafe erinka, ko'ma krente'nankeno kini ne' Johoiakimima tevefima kre'nea nanekea ana avontafepi ana maka nanekea ete krento.
29 Kí o sì wí fún Jehoiakimu ọba Juda pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, ìwọ ti fi ìwé kíká náà jóná, o sì wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi kọ̀wé sínú rẹ̀, pé lóòtítọ́ ni ọba Babeli yóò wá, yóò sì pa ilẹ̀ run, àti ènìyàn, àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀.”
Ana nehunka kini ne' Jehoiakiminkura amanage hugahane. Ra Anumzamo'a huno, kagra avontafera tevefi negrenka amanage hu'nane. Nahigeno Jeremaia'a avontafepina kreno, Babiloni kini nemo'a eno ama kumara eri haviza nehuno vahe'ene, zagagafanena zamaheno erihana hugahie huno hu'ne?
30 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí ní ti Jehoiakimu ọba Juda pé, Òun kì yóò ní ẹni tí yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, à ó sì sọ òkú rẹ̀ nù fún ooru ní ọ̀sán àti fún òtútù ní òru.
E'ina hu'negu Ra Anumzamo'a Juda kini ne' Jehoiakiminkura amanage hu'ne. Agri nagapintira magore huno henka'a agri nona erino Deviti kini tratera kinia omanitfa hugahie. Hagi fri'nige'za avufga'a fegi eritre'nesageno, masarera zagemo renentesigeno, kenagera aisi komo runtegahie.
31 Èmi ó sì jẹ òun àti irú-ọmọ rẹ̀, ìránṣẹ́ rẹ̀ ní ìyà nítorí àìṣedéédéé wọn; èmi ó sì mú gbogbo ibi tí èmi ti sọ sí wọn wá sórí wọn, àti sórí àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn Juda, nítorí tí wọn kò fetísí mi.’”
Hagi zamagrama hu'naza kumitera, Nagra nona huzamante'na agri'ene mofavre naga'ane eri'za vahe'anena zamazeri haviza hugahue. Ana nehu'na zamagrite'ene Jerusalemi kumapi vahete'ene, Juda vahete'enena hazenke'za atresugeno egahie hu'na hu'noanagi ana nanekea ontahi'naze huno Anumzamo'a hu'ne.
32 Nígbà náà ni Jeremiah mú ìwé kíká mìíràn fún Baruku akọ̀wé ọmọ Neriah, ẹni tí ó kọ̀wé sínú rẹ̀ láti ẹnu Jeremiah gbogbo ọ̀rọ̀ inú ìwé tí Jehoiakimu ọba Juda ti sun níná. A sì fi onírúurú ọ̀rọ̀ bí irú èyí kún pẹ̀lú.
Hagi anante Jeremaia'a ru'ene mago avontafe erino avoma kreno erinte fatgoma nehia ne' Neria nemofo Barukuna nemino higeno, koma kre'nea avoma Juda kini ne' Jehoiakimi'ma tevefima kre'nea nanekeramina, ete Jeremaia'a nehigeno avontafepi krente'ne. Ana nehuno mago'ene ana agofetura rama'a anahukna nanekenena nehigeno krente'ne.

< Jeremiah 36 >